< Ezekiel 25 >

1 Ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá wí pé:
Hina Gode da nama amane sia: i,
2 “Ọmọ ènìyàn, kọ ojú rẹ sí àwọn ará Ammoni kí ó sì sọ àsọtẹ́lẹ̀ sí wọn.
“Dunu egefe! A: mone fi ilima amane sisa: i lama!
3 Sì wí fún àwọn ará Ammoni pé, ‘Ẹ gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa Olódùmarè tí ó wí pé. Nítorí tí ìwọ wí pé, “Á hà!” Sí ibi mímọ́ mi nígbà tí ó di àìlọ́wọ̀ àti sí orí ilẹ̀ Israẹli nígbà tí ó di ahoro; àti sí ilẹ̀ Juda, nígbà tí wọ́n lọ sí ìgbèkùn,
‘Ouligisu Hina Gode Ea sia: nabima! E da amane sia: sa; Dilia da Na Debolo da ledo hamoi dagoi ba: beba: le, hahawane galu. Isala: ili soge da wadela: lesi dagoi, amola Yuda fi dunu da mugululi asi. Amo amola, dilia da hahawane ba: i.
4 kíyèsi i, nítorí náà ni èmi yóò fi fi ọ lé àwọn ènìyàn ìlà-oòrùn lọ́wọ́ ni ohun ìní. Wọn yóò sì gbé ààfin wọn kalẹ̀ nínú rẹ, wọn yóò sì gbé ibùgbé wọn nínú rẹ, wọn yóò jẹ èso rẹ, wọn yóò sì mu wàrà rẹ.
Dilia da amo hou hahawane ba: beba: le, Na da fi ilia da eso mabe la: di hafoga: i sogega esala, amo dilima hasalasima: ne, logo doasimu. Ilia da dilia soge ganodini ha wa: i fisisu hamone esalumu. Ilia da dilia ha: i manu fage legei amola bulamagau dodo maga: me lale manu.
5 Èmi yóò sì sọ Rabba di ibùjẹ, fún àwọn ìbákasẹ àti àwọn ọmọ Ammoni di ibùsùn fún agbo ẹran. Nígbà náà ni ẹ̀yin yóò mọ̀ pé, Èmi ni Olúwa.
Na da La: ba moilai bai bagade wadela: lesili, e da bu ga: mele ea gisi moma: ne sogebi agoane ba: mu, amola A: mone soge huluane da sibi afugisu soge agoane ba: mu. Bai dilia da Na da Hina Gode dawa: ma: ne.’”
6 Nítorí báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí. Nítorí pé ìwọ pàtẹ́wọ́, ìwọ sì jan ẹsẹ̀ mọ́lẹ̀, tí ìwọ ń yọ̀ pẹ̀lú gbogbo àrankàn rẹ sí ilẹ̀ Israẹli
Ouligisudafa Hina Gode da amane sia: sa, “Dilia da lobo fane, nodone soagala: la gagadoi. Dilia da Isala: ili soge fi amo higasu.
7 nítorí náà, èmi yóò na ọwọ́ mi lé ọ, èmi yóò sì fi ọ fún àwọn aláìkọlà fún ìkógun. Èmi yóò sì gé ọ kúrò láàrín àwọn ènìyàn, èmi yóò sì jẹ́ kí o parun kúrò ni ilẹ̀ gbogbo. Èmi yóò sì pa ọ́ run, ìwọ yóò sì mọ̀ pé èmi ni Olúwa.’”
Dilia da agoane hamobeba: le, Na da dili eno fifi asi gala ilima iagamu. Ilia da dilia liligi gegenana lamu. Na da dafawanedafa dili wadela: lesimu. Amasea, dilia da fi agoane hame ba: mu, amola dilia da soge hame gagui ba: mu. Amasea, dilia da Na da Hina Gode dawa: mu.”
8 “Báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí: ‘Nítorí pé Moabu àti Seiri sọ wí pé, “Wò ó, ilé Juda ti dàbí gbogbo àwọn kèfèrí,”
Ouligisudafa Hina Gode da amane sia: i, “Moua: be fi ilia da amane sia: i, ‘Yuda fi da hisu hame. Ilia da fifi asi gala huluane ili defele gala.’
9 nítorí náà, Èmi yóò ṣí Moabu sílẹ̀ láti àwọn ìlú gbogbo tí ó wà ní ààlà rẹ̀, ògo ilẹ̀ náà, Beti-Jeṣimoti, Baali-Meoni àti Kiriataimu.
Amaiba: le, eno fi dunu da moilai bai bagade amo da Moua: be ea alalo defei gaga: lala (amo da moilai bai bagade ida: iwane gala - Bede Yesimode, Ba: ile Mione, Giliada: ime) amo doagala: musa: , Na da logo doasimu.
10 Èmi yóò fi Moabu pẹ̀lú àwọn ará Ammoni lé àwọn ènìyàn ìlà-oòrùn ní ìní, kí a má bà á lè rántí àwọn ará Ammoni láàrín orílẹ̀-èdè gbogbo.
Na da dunu fi eno ilia da eso mabe gusudili hafoga: i sogega esala, amo Moua: be amola A: mone gilisili hasalasima: ne, logo doasimu. Amasea, Moua: be da fidafa agoane bu hame ba: mu.
11 Èmi yóò sì mú ìdájọ́ sẹ sí Moabu lára, wọn yóò sì mọ̀ pé èmi ni Olúwa.’”
Na da Moua: be fi ilima se bidi imunu. Amasea, ilia da Na da Hina Gode dawa: mu.”
12 “Báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí pé: ‘Nítorí pé Edomu gbẹ̀san lára ilé Juda, ó sì jẹ̀bi gidigidi nípa ṣíṣe bẹ́ẹ̀,
Ouligisudafa Hina Gode da amane sia: i, “Idome fi dunu da Yuda dunu fi ilima nimi bagade dabe i. Ilia amo dabe iabeba: le, Na da ilima se imunusa: fofada: mu gala.
13 nítorí náà báyìí ní Olúwa Olódùmarè wí pé: Èmi yóò na ọwọ́ mi sórí Edomu èmi yóò sì pa àwọn ènìyàn àti àwọn ẹranko rẹ̀. Èmi yóò fi ṣófo láti Temani dé Dedani yóò ti ipa idà ṣubú.
Na da wali sia: sa. Na da Idome fi ilima se bidi imunu. Na da dunu huluanedafa amola ohe huluane amogai esala, amo medole legemu. Soge huluane, amo Dima: ne moilai amoinini asili Dida: ne sogega doaga: le, dogo soge amo huluane Na da wadela: lesimu, amola dunu huluane da gegesu ganodini medole legei dagoi ba: mu.
14 Èmi yóò gbẹ̀san lára Edomu láti ọwọ́ àwọn ènìyàn mi Israẹli, wọn sì ṣe sí Edomu gẹ́gẹ́ bí ìbínú àti ìrunú mi, wọn yóò mọ̀ ìgbẹ̀san mi ní Olúwa Olódùmarè wí.’”
Na da ilima sia: sea, Na fi dunu (Isala: ili fi) da Idome fi ilima dabe imunu. Ilia da Idome ilima gegemuba: le, Idome da Na ougidafa hou nabimu. Ilia da Na da ilima dabe i dagoi dawa: mu.” Ouligisu Hina Gode da sia: i dagoi.
15 “Báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí pé: ‘Nítorí tí àwọn ará Filistini hùwà ẹ̀san tí wọ́n sì gbẹ̀san pẹ̀lú odì ní ọkàn wọn, àti pẹ̀lú ìkórìíra gbangba àtijọ́ ní wíwá ọ̀nà láti pa Juda run,
Ouligisu Hina Gode da amane sia: i, “Filisidini fi dunu da ilia musa: ha lai dunu amoma nimi bagade dabe i. Ilia da ilia ha lai dunu bagade higa: iba: le, ili wadela: lesi dagoi.
16 nítorí náà báyìí ní Olúwa Olódùmarè wí pé, “Èmi ti ṣetán láti na ọwọ́ mi jáde sí àwọn ará Filistini, èmi yóò sì ké àwọn ará Kereti kúrò, èmi yóò sì pa àwọn tí ó kù ní etí kún run.
Amaiba: le, Na da amane sia: sa. Na da Filisidini fi dunu doagala: le, ili huluane medole legele ebelemu. Dunu huluane Filisidini Umi amogai esala, amo Na da wadela: lesili ebelemu.
17 Èmi yóò sì gbẹ̀san ńlá lára wọn nípa ìbáwí gbígbóná; wọn yóò sì mọ̀ wí pé, Èmi ni Olúwa. Nígbà tí èmi yóò gba ẹ̀san lára wọn.”’”
Na da gasa bagadewane ilima se dabe imunu. Ilia da Na ougi ba: mu. Amola ilia da Na da Hina Gode dawa: mu.”

< Ezekiel 25 >