< Ezekiel 24 >

1 Ní ọdún kẹsànán, oṣù kẹwàá, ọjọ́ kẹwàá, ni ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá wí pé:
Ke len se aksingoul in malem aksingoul ke yac akeu in sruoh lasr, LEUM GOD El kaskas nu sik ac fahk,
2 “Ọmọ ènìyàn, kọ ọjọ́ náà sílẹ̀, ọjọ́ náà gan an, nítorí ọba Babeli náà ti da ojú ti Jerusalẹmu ní ọjọ́ yìí gan an.
“Kom, mwet sukawil moul la, akilenya len se inge, mweyen pa inge len se ma tokosra lun Babylonia el mutawauk in kuhlusya acn Jerusalem.
3 Sì pa òwe yìí fún ilé ọlọ́tẹ̀ náà, sọ fún wọn pé: ‘Èyí yìí ni Olúwa Olódùmarè wí: “‘Gbé ìkòkò ìdáná náà ka iná, gbé e ka iná kí o sì da omi sí i nínú.
Fahkang nu sin mwet luk su lungse lainyu, pupulyuk se inge ma nga, LEUM GOD Fulatlana, oru nu selos: Filiya sie tup an fin e uh Ac nwakla ke kof.
4 Kó àwọn ègé ẹran tí a gé náà sínú rẹ̀, gbogbo àwọn ègé ẹran tí ó tóbi, itan àti apá. Kó àwọn egungun tí ó dára jù sínú rẹ̀,
Sang ipin ikwa ma wo emeet nu loac — Pap in pao ac pap in nia — Oayapa ikwa ma oasr sri kac su yu pac.
5 mú àwọn tí ó jọjú nínú agbo ẹran. Kó àwọn egungun sí abẹ́ ẹ rẹ̀; sì jẹ́ kí ó hó dáradára sì jẹ́ kí àwọn egungun náà bọ̀ nínú rẹ̀.
Orekmakin ikwen sheep ma arulana wo; Orani etong an nu ye tup an. Oru kof an in poel; Na poeleak kewa sri ac ikwa an.”
6 Nítorí báyìí ní Olúwa Olódùmarè wí: “‘Ègbé ni fún ìlú ẹlẹ́jẹ̀ náà, fún ìkòkò náà tí èérí rẹ̀ wà nínú rẹ̀, tí èérí kò dà kúrò lójú rẹ̀! Mú ẹran náà jáde ní ekìrí ekìrí má ṣe ṣà wọ́n mú.
Pa inge ma LEUM GOD Fulatlana El fahk: “We nu sin siti lun mwet akmas uh! El oana sie tup rasla ma tiana aknasnasyeyuk. Kais sie ipin ikwa ituk na ituk nwe ke wangin sie ip lula.
7 “‘Nítorí ẹ̀jẹ̀ tí ó ta sílẹ̀ wà ní àárín rẹ̀; à á sí orí àpáta kan lásán kò dà á sí orí ilẹ̀, níbi ti erùpẹ̀ yóò ti bò ó.
Akmas orek in siti uh, tusruktu srah uh tiana sororla nu fin fohk uh, yen kutkut uh ku in afinya, a sororla nu fin sie eot ma oan kalem.
8 Láti bá à le jẹ́ kí ìbínú kí ó dé láti gbẹ̀san mo da ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ sí orí àpáta kan lásán, kí o ma bà á wà ni bíbò.
Nga mansis srah uh in oanna insac, yen ma ac tia ku in wikinyukla, pwanang mwet uh in kasrkusrak ac suk in foloksak.”
9 Nítorí náà báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí: “‘Ègbé ni fún ìlú ẹlẹ́jẹ̀ náà! Èmi pàápàá yóò jẹ́ kí òkìtì iná náà tóbi.
“Pa inge ma LEUM GOD Fulatlana El fahk: We nu sin siti akmas sac! Nga ac sifacna elosak eol in etong uh in yohk.
10 Nítorí náà kó igi náà jọ sí i, kí o sì fi iná sí i. Ṣe ẹran náà dáradára, fi tùràrí dùn ún; kí o sì jẹ́ kí egungun náà jóná.
Use pac kutu etong an! Taun in ngeng! Akmolyela ikwa an! Poeli nwe ke na lisr sroano, ac lela sri an in firiryak.
11 Lẹ́yìn náà gbé òfìfo ìkòkò náà lórí ẹyin iná kí idẹ rẹ̀ lè gbóná, kí ó lè pọ́n àti ki ìfófó rẹ̀ le di yíyọ́ nínú rẹ̀ kí èérí rẹ̀ le jó dànù.
Filiya pisin tup osra sacn fin mulut an nwe ke na arulana folla ac srusrala. Na tup sacn ac fah sifil nasnasla ac ras kac uh ac isisla,
12 Ó ti ba gbogbo akitiyan jẹ: èérí rẹ̀ kò sì jáde kúrò lára rẹ̀, èérí náà gan an yóò wà nínú iná.
finne tia ku in wanginla nufon ras kac an ke e sac.
13 “‘Nísinsin yìí èérí rẹ̀ ni ìwà ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ wà. Nítorí mo gbìyànjú láti wẹ̀ ọ́ mọ́, ṣùgbọ́n ìwọ kò sì mọ́ kúrò nínú ìwà ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ rẹ, a kì yóò sì tún wẹ̀ ọ mọ́ kúrò nínú èérí rẹ, títí èmi yóò fi jẹ́ kí ìbínú mi balẹ̀ sórí rẹ̀.
Jerusalem, orekma koluk lom uh akfohkfokyekomla. Nga ne srike in aknasnasyekomla, tuh kom srakna fohkfok. Kom tia ku in sifil nasnasla nwe ke na kom pula kuiyen kasrkusrak luk uh.
14 “‘Èmi Olúwa ni ó sọ ọ́, yóò sì ṣe, èmi yóò sì ṣe é. Èmi kì yóò padà sẹ́yìn; bẹ́ẹ̀ ni èmi kì yóò dá sí i, bẹ́ẹ̀ ni èmi kì yóò yí ọkàn mi padà; gẹ́gẹ́ bí ọ̀nà rẹ, àti gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ rẹ, ni wọn yóò dá ọ lẹ́jọ́, ni Olúwa Olódùmarè wí.’”
Nga, LEUM GOD, pa fahk ma inge. Sun tari pacl fal nga in oru ma nga ac oru uh. Nga ac fah tia pilesru orekma koluk lom, ku pakomutom, ku nunak munas nu sum. Ac fah kalyeiyuk kom ke ma kom orala.” LEUM GOD Fulatlana pa fahk ma inge.
15 Ọ̀rọ̀ Olúwa sì tọ̀ mí wá pé:
Na LEUM GOD El kaskas nu sik,
16 “Ọmọ ènìyàn, kíyèsi i, mo mú ìfẹ́ ojú rẹ kúrò ní ọ̀dọ̀ rẹ, nípa lílù kan. Ṣùgbọ́n ìwọ kò gbọdọ̀ gbààwẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni ìwọ kò gbọdọ̀ sọkún, bẹ́ẹ̀ ni omijé ojú rẹ kò gbọdọ̀ kán sílẹ̀.
ac fahk, “Mwet sukawil, nga ac eisla moul lun mwet se kom lungse emeet ke sie ouiya na sa. Kom fah tiana torkaskas, ku tung, ku lela sroninmotom in sororla.
17 Má ṣe sọkún, má ṣe gbààwẹ̀ fún òkú. Wé ọ̀já sí orí rẹ, sì bọ bàtà sí ẹsẹ̀ rẹ, má ṣe bo ètè ìsàlẹ̀ rẹ, ma ṣe jẹ oúnjẹ tí àwọn tí ń ṣọ̀fọ̀ ń jẹ gẹ́gẹ́ bí àṣà.”
Nimet oru in lohngyuk pusren mwemelil lom. Nimet kom eisla susu liki sifom, ku sarukla fahluk liki niom in akkalemye lah kom asor. Nimet afinya motom, ku kang mwe mongo ma mwet asor uh kang.”
18 Báyìí ni mo sọ̀rọ̀ fún àwọn ènìyàn ní òwúrọ̀, ní àṣálẹ́ ìyàwó mi sì kú. Ní òwúrọ̀ ọjọ́ kejì, mo ṣe bí a ti pàṣẹ fún mi.
Ke lotutang sac, nga tuh sramsram nu sin mwet uh. Ke eku sacna, mutan kiuk uh misa, ac ke len toko ah nga oru oana ma sapkinyuk nu sik.
19 Lẹ́yìn náà àwọn ènìyàn bi mí léèrè pé, “Ṣe o kò ni sọ fún wa ohun ti nǹkan wọ̀nyí ní láti ṣe pẹ̀lú wa?”
Na mwet uh siyuk sik, “Efu ku kom oru ouingan?”
20 Mo sọ báyìí fún wọn pé, “Ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá wí pé:
Na nga fahk nu selos, “LEUM GOD El kaskas nu sik ac fahk nga in
21 Sọ fún ilé Israẹli, ‘Báyìí ní Olúwa Olódùmarè wí: Kíyèsi i, èmi yóò sọ ibi mímọ́ mi di ibi àìmọ́ tayọ agbára yín, ìfẹ́ ojú yín, ìkáàánú yín, àti ọmọ yín ọkùnrin àti àwọn ọmọ yín obìnrin tí ẹ̀yin fi sílẹ̀ sẹ́yìn yóò ṣubú nípa idà.
tafweot sap soko inge nu suwos, mwet Israel: Kowos insefulatkin ku lun Tempul uh. Kowos lungsena fahsri ac intoein. Tusruktu LEUM GOD El ac fah akfohkfokye. Ac mwet fusr in sou lowos su lula in acn Jerusalem ac fah anwuki ke mweun.
22 Ẹyin yóò sì ṣe bí mo ti ṣe. Ẹ̀yin kì yóò bo ìsàlẹ̀ ojú yín tàbí jẹ oúnjẹ ti àwọn tí ń ṣọ̀fọ̀ ń jẹ gẹ́gẹ́ bí àṣà.
Na kowos fah oru oana ma nga oru inge. Kowos fah tia afinya motowos, ku kang mwe mongo nun mwet asor.
23 Ẹ̀yin yóò fi àwọn ọ̀já wé àwọn orí yín àti àwọn bàtà ni ẹsẹ̀ yín, ẹ̀yin kì yóò ṣọ̀fọ̀ tàbí sọkún, ṣùgbọ́n ẹ̀yin yóò ṣòfò dànù nítorí àwọn àìṣedéédéé yín, ẹ̀yin yóò sì máa kérora láàrín ara yín.
Kowos ac fah susuyang ac fahlukyang, ac tia asor ku tung. Kowos ac fah srila ke sripen ma koluk lowos, ac kowos fah sasao inmasrlowos sifacna.
24 Esekiẹli yóò jẹ àmì fún un yín; ẹ̀yin yóò sì ṣe gẹ́gẹ́ bí òun ti ṣe. Nígbà tí èyí bá ṣẹlẹ̀, ẹ̀yin yóò mọ̀ pé èmi ni Olúwa Olódùmarè.’
Na nga ac fah sie mwe akul nu suwos. Kowos ac fah oru ma nukewa oana ma nga oru. LEUM GOD El fahk mu pacl se ma inge ac sikyak uh, kowos ac fah etu lah El pa LEUM GOD Fulatlana.”
25 “Pẹ̀lúpẹ̀lú ìwọ, Ọmọ ènìyàn, kì yóò ha jẹ́ pé, ní ọjọ́ náà, nígbà ti mo bá gba agbára wọn, ayọ̀ wọn àti ògo wọn, ìfẹ́ ojú wọn, ohun tí wọn gbé ọkàn wọn lé, àti àwọn ọmọ ọkùnrin wọn pẹ̀lú àwọn ọmọ obìnrin wọn kúrò lọ́dọ̀ wọn,
Na LEUM GOD El fahk, “Mwet sukawil, inge nga ac fah eisla lukelos Tempul fokoko se inge, su elos tuh engankin ac insefulatkin, su elos lungsena fahsri ac intoein. Ac nga fah eisla wen ac acn natulos lukelos.
26 ní ọjọ́ náà ẹni tí ó bá sálà yóò tọ̀ ọ́ wá láti sọ ìròyìn náà fún ọ.
Ke len se ma nga ac oru ma inge, sie mwet su kaingkunla ongoiya sac ac tuku ac fahkak ma inge nu sum.
27 Ní ọjọ́ náà ẹnu rẹ yóò sì ṣí; ìwọ yóò sọ̀rọ̀, ìwọ kì yóò sì yadi mọ́. Báyìí ìwọ yóò jẹ́ àmì fún wọn; wọn yóò sì mọ̀ pé èmi ní Olúwa.”
Ke len sacna, oalum ac fah ikakla ac kom ac ku in sifil kaskas, na kom fah sramsram nu sel. Ke ouiya se inge kom ac fah sie mwe akul nu sin mwet uh, na elos ac fah etu lah nga pa LEUM GOD.”

< Ezekiel 24 >