< Ezekiel 23 >

1 Ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá:
BAWIPA e lawk kai koe bout a pha teh,
2 “Ọmọ ènìyàn, obìnrin méjì wà, ọmọ ìyá kan náà.
tami capa napui e ca roi kahni touh
3 Wọn ń ṣe panṣágà ní Ejibiti, wọn ń ṣe panṣágà láti ìgbà èwe wọn. Ní ilẹ̀ yẹn ni wọn ti fi ọwọ́ pa ọyàn wọn, níbẹ̀ ni wọn sì fọwọ́ pa igbá àyà èwe wọn.
Izip ram vah a kâyo roi teh, a nawca hoi a kâyo roi toe, hatdawkvah a sanu hah a pânam pouh awh teh, a tanglanae banglahai noutna awh hoeh.
4 Èyí ẹ̀gbọ́n ń jẹ́ Ohola, àbúrò rẹ̀ sì ń jẹ́ Oholiba. Tèmi ni wọ́n, wọ́n sì bí àwọn ọmọkùnrin àti àwọn ọmọbìnrin. Ohola ni Samaria, Oholiba sì ni Jerusalẹmu.
Kacuehnawn e min teh Oholah, a nawngha teh Oholibah doeh. Kaie lah ao awh teh napui tongpa hah a khe awh. A min lah Oholah teh Samaria tami doeh, Oholibah teh Jerusalem doeh.
5 “Ohola ń ṣe panṣágà nígbà tí ó sì jẹ́ tèmi; Ó sì ṣe ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ sí àwọn olólùfẹ́ rẹ̀, àwọn jagunjagun ará Asiria.
Oholah teh kaie lah ao hnukkhu a kâyo teh, a lungpataw e a imri Assiria teh a noe.
6 Aṣọ aláró ni a fi wọ̀ wọ́n, àwọn gómìnà àti àwọn balógun, gbogbo wọn jẹ́ ọ̀dọ́mọkùnrin arẹwà àwọn tí ń gun ẹṣin.
Hnipaling hoi kamthoup e ukkung hoi lawkcengkungnaw, a pahren e thoundounnaw, Marangransanaw marangnaw dawk kâcuinaw hah,
7 O fi ara rẹ̀ fún gbajúmọ̀ ọkùnrin Asiria gẹ́gẹ́ bí panṣágà obìnrin, o fi òrìṣà gbogbo àwọn tí ó ní ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ sí i sọ ara rẹ̀ di aláìmọ́,
hete Assiria thoundoun kahawi pueng koevah, a kâyo teh a mit hoi a nôe e meikaphawk koevah a kâkhinsak.
8 kò fi ìwà panṣágà tí ó ti bẹ̀rẹ̀, ni Ejibiti sílẹ̀, ní ìgbà èwe rẹ̀ àwọn ọkùnrin n bá a sùn, wọn fi ọwọ́ pa àyà èwe rẹ̀ lára wọn sì ń ṣe ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ sí i.
A nawca hoi a sanu a pânam pou teh a ikhai awh dawkvah, Izip lahoi a kâyo e hah kâhat hoeh. Ahnimouh ni hai a cuk awh nahanelah, a lathueng vah lungkhuek ati nahanelah a hno awh.
9 “Nítorí náà mo fi i sílẹ̀ fún àwọn olólùfẹ́ rẹ̀, ará Asiria, tí ó ní ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ sí i.
A pahren teh mit ni a nôe e, Assiria kut roeroe dawkvah ka man sak.
10 Wọ́n bọ́ ọ sí ìhòhò, wọ́n sì gba àwọn ọmọkùnrin àti ọmọbìnrin rẹ̀ wọn sì pa wọn pẹ̀lú idà. Ó di ẹni ìfisọ̀rọ̀ sọ láàrín àwọn obìnrin wọ́n sì fi ìyà jẹ ẹ́.
Hetnaw ni caici lah ao nahan angki a rading pouh, a canu hoi a capanaw a la pouh. Ama haiyah tahloi hoi a thei awh teh, napuinaw thung dawk kamthang poung e lah ao. A lathueng vah lawkceng e patetlah a kuep sak.
11 “Àbúrò rẹ̀ Oholiba rí èyí, síbẹ̀ nínú ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ àti panṣágà rẹ̀, Ó ba ara rẹ jẹ́ ju ẹ̀gbọ́n rẹ̀ lọ.
A nawngha Oholibah ni hetheh a hmu. Hateiteh, a hmau hlak hai noenae hoe a len, a kâyonae hai a hmau hlak vah hoe a nut.
12 Òun náà ní ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ sí ará Asiria àwọn gómìnà àti àwọn balógun, jagunjagun nínú aṣọ ogun, àwọn tí ń gun ẹṣin, gbogbo àwọn ọ̀dọ́mọkùnrin arẹwà.
Assirianaw e imri ram kaukkungnaw hoi, lawkcengkung ngai han kaawm e thoundoun, Marangransanaw marang van kâcuinaw, kahawipoung lah kamthoup e hah a mit hoi a noe.
13 Mo rí i pé òun náà ba ara rẹ̀ jẹ́; àwọn méjèèjì rìn ojú ọ̀nà kan náà.
A khin e hah ka hmu, kahni touh hoi lamthung rei kâvan e a dawn awh.
14 “Ṣùgbọ́n ó tẹ̀síwájú nínú ṣíṣe panṣágà. O ri àwòrán àwọn ọkùnrin lára ògiri, àwòrán àwọn ara Kaldea àwòrán pupa,
Hateiteh, a kâyonae hoe a nut sak teh, tongpa meikaphawk rapan dawk kamnuek e Khaldeannaw e meilam, paling e lahoi kamthoup e,
15 pẹ̀lú ìgbànú ni ìdí wọn àti àwọn ìgbàrí ni orí wọn; gbogbo wọn dàbí olórí kẹ̀kẹ́ ogun Babeli ọmọ ìlú Kaldea.
a keng dawk taisawm kâyeng e, a lû dawk a pei lupawk kâmuk e, siangpahrang e mei koung ka lat e, Khaldean ram a tâconae ram, Babilonnaw patetlah a hmu.
16 Ní kété tí ó rí wọn, ó ní ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ sí wọn, ó sì rán oníṣẹ́ sí wọn ni Kaldea.
Ahnimouh a hmu awh tahma tang a ngai awh teh, ahnimouh koe Khaldean totouh patounenaw a patoun.
17 Àwọn ará Babeli wá sọ́dọ̀ rẹ̀, lórí ibùsùn ìfẹ́, nínú ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ wọn, wọ́n bà á jẹ́. Lẹ́yìn ìgbà tí wọ́n bà á jẹ́ tán, ó yípadà kúrò lọ́dọ̀ wọn ní ìtìjú.
Babilonnaw hah ahni koevah napui tongpa yonnae ikhun dawk a tho awh teh, a cuknae lahoi a khin sak awh teh, amahoima panuettho e lah be a kangcoung sak awh teh a khin awh.
18 Nígbà tí ó tẹ̀síwájú nínú iṣẹ́ panṣágà rẹ̀ ní gbangba wọ́n sì tú u sí ìhòhò, mo yí padà kúrò lọ́dọ̀ rẹ̀ ní ìtìjú, gẹ́gẹ́ bí mo ti yípadà kúrò lọ́dọ̀ ẹ̀gbọ́n rẹ̀.
Hottelah hoi a kâyonae a kamnue sak teh, caici lah onae hah a kamnue sak, a hmau ka panuet e patetlah a nawngha hai ka panuet van.
19 Síbẹ̀síbẹ̀ ó ń pọ̀ sí i nínú ìdàpọ̀ rẹ̀ bí ó ti ń rántí ìgbà èwe rẹ̀ tí ó jẹ́ panṣágà ní Ejibiti.
Hatei, a naw lahunnae Izip ram dawk a kâyo awh e hah pahnim pouh hoeh, hoehoe a kâyo awh.
20 Nítorí ó fẹ́ olùfẹ́ àwọn olùfẹ́ wọn ní àfẹ́jù, tí àwọn tí nǹkan ọkùnrin wọn dàbí ti kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́, àwọn ẹni tí ìtújáde ara wọn dàbí ti àwọn ẹṣin.
Hahoi kaipkhainaw e a tak teh la e tak patetlah a yangtui teh marang e yangtui doeh toe.
21 Báyìí ni ìwọ pe ìwà ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ ìgbà èwe rẹ wá sí ìrántí, ní ti rírin orí ọmú rẹ láti ọwọ́ àwọn ará Ejibiti, fún ọmú ìgbà èwe rẹ.
Hettelah na nawca nah na cuknae, Izipnaw ni na sanu a pânam pouh e hah bout na pouk rah.
22 “Nítorí náà, Oholiba, báyìí ní Olúwa Olódùmarè wí, Èmi yóò gbé olólùfẹ́ rẹ dìde sí ọ, àwọn tí o kẹ́yìn si ní ìtìjú, èmi yóò sì mú wọn dojúkọ ọ́ ní gbogbo ọ̀nà
Hatdawkvah Oe Oholibah, hettelah Bawipa Jehovah ni a dei. Khenhaw! kayonkhaikung, na lungthin hoi na maithoe e hah ka coun vaiteh, a hmuen tangkuem koehoi ka tho sak vaiteh, na tuk sak han.
23 àwọn ará Babeli àti gbogbo ara Kaldea àwọn ọkùnrin Pekodi àti Ṣoa àti Koa àti gbogbo ará Asiria pẹ̀lú wọn, àwọn ọ̀dọ́mọkùnrin arẹwà, gbogbo àwọn gómìnà àti balógun, olórí oníkẹ̀kẹ́ ogun àti àwọn onípò gíga, gbogbo àwọn tí ń gun ẹṣin.
Babilon, Khaldean, Pekod, Shoa, hoi Koa hoi ahnimouh koe kaawm e Assirianaw hoi, abuemlahoi ngai ka tho poung e thoundoun, ukkung hoi lawkcengkung, bawi hoi tami a min kamthang abuemlahoi marang dawk kâcui laihoi a tho awh han.
24 Wọn yóò wa dojúkọ ọ pẹ̀lú ohun ìjà, kẹ̀kẹ́ ogun pẹ̀lú kẹ̀kẹ́ ẹrù àti pẹ̀lú ìwọ́jọpọ̀ ènìyàn; wọn yóò mú ìdúró wọn lòdì sí ọ ní gbogbo ọ̀nà pẹ̀lú asà ńlá àti kékeré pẹ̀lú àṣíborí. Èmi yóò yí ọ padà sí wọn fun ìjìyà, wọn yóò sì fi ìyà jẹ ọ gẹ́gẹ́ bí wọn tí tó.
Tarantuknae puengcang, tarantuknae leng, leng hoi tamihupui hoi, a tuk awh han. Saiphei kalen kathoung sumluhuemnaw hoi, ahnimouh koe lawkcengnae hah ka poe han. Lawk a ceng awh e boiboe lah nange lathueng a kuep sak han.
25 Èmi yóò sì dojú ìbínú owú mi kọ ọ́, wọn yóò sì fìyà jẹ ọ́ ní ìrunú. Wọ́n yóò gé àwọn imú àti àwọn etí yín kúrò, àwọn tí ó kù nínú yín yóò ti ipá idà ṣubú. Wọn yóò mú àwọn ọmọkùnrin àti àwọn ọmọkùnrin yín lọ, àwọn tí o kù nínú yín ni iná yóò jórun.
Nang e lathueng utnae hah kamnue sak e lahoi, ka hring e hah tahloi hoi a due awh han. Na canu na capa naw hoi na lawp awh han, a hring nah thung hmai ni a kak awh han.
26 Wọn yóò sì kó àwọn aṣọ àti àwọn ohun ọ̀ṣọ́ iyebíye yín.
Na khohna hah na rading pouh awh vaiteh, na kamthoupnae kahawi poung e hah koung na la pouh awh han.
27 Èmi yóò sì fi òpin sí ìwà ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ àti iṣẹ́ panṣágà tí ẹ bẹ̀rẹ̀ ni Ejibiti. Ẹ̀yin kò ní wo àwọn nǹkan wọ̀nyí pẹ̀lú ìpòùngbẹ, bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò ní rántí Ejibiti mọ.
Na cuknae hoi Izip ram hoi na kâyonae hah na kâhat sak han. Hottelah ahnimouh koe lah na mit na hrueng mahoeh toe. Izip ram teh na pâkuem mahoeh toe.
28 “Nítorí báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí: Èmi yóò fi ọ lé ọwọ́ àwọn tí ó kórìíra, lọ́wọ́ àwọn ẹni tí ọkàn rẹ ti ṣí kúrò.
Bangkongtetpawiteh, Bawipa Jehovah ni, hettelah a dei khenhaw! na hmuhma poung e, na lungthin dawk hoi na hmuhma e naw kut dawk na man sak han.
29 Wọn yóò fìyà jẹ ọ́ pẹ̀lú ìkórìíra, wọn yóò sì kó gbogbo ohun tí o ṣiṣẹ́ fún lọ. Wọn yóò fi ọ́ sílẹ̀ ní ìhòhò goloto, ìtìjú iṣẹ́ panṣágà rẹ ni yóò farahàn. Ìwà ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ rẹ̀ àti panṣágà rẹ.
Na hmuhma katang awh han. Na tawk awh e a pawhiknaw hah, na la pouh awh han. Caici lah na hruek awh han, na kâyonae caici lah, na cuknae hoi na kâyonae hah kamnue sak e lah ao han.
30 Èmi yóò ṣe gbogbo nǹkan wọ̀nyí sí ọ, nítorí ìwọ ti bá àwọn kèfèrí ṣe àgbèrè lọ, o sì fi àwọn òrìṣà wọn ba ara rẹ̀ jẹ́.
Hete hnonaw heh nange lathueng a pha han. Alouke miphun koehoi na kâyo teh a meikaphawknaw dawk na kâkhinsak dawkvah,
31 Ìwọ ti rin ọ̀nà ti ẹ̀gbọ́n rẹ rìn, Èmi yóò sì fi ago rẹ̀ lé ọ lọ́wọ́.
na hmau e lamthung na dawn. Hatdawkvah, a neinae manang hah na kut dawk na poe han telah a ti.
32 “Èyí yìí ní ohun ti Olúwa Olódùmarè wí: “Ìwọ yóò mu nínú ago ẹ̀gbọ́n rẹ, ago tí ó tóbi tí ó sì jinnú: yóò mú ìfiṣẹ̀sín àti ìfiṣe ẹlẹ́yà wá, nítorí tí ago náà gba nǹkan púpọ̀.
Bawipa Jehovah ni hettelah a dei. Na hmau e a neinae manang kalenpounge thung hoi na nei vaiteh, pacekpahleknae hoi panuikhai e lah na o han. Bangkongtetpawiteh, hote manang dawk moikapap a kâen dawkvah.
33 Ìwọ yóò mu àmupara àti ìbànújẹ́, ago ìparun àti ìsọdahoro ago ẹ̀gbọ́n rẹ Samaria.
Yamuhrinae hoi lungmathoenae hoi na kawi vaiteh, kângairunae hoi rawknae, na hmau Samaria e manang hoi he na nei han.
34 Ìwọ yóò mú un ni àmugbẹ; ìwọ yóò sì fọ sí wẹ́wẹ́ ìwọ yóò sì fa ọmú rẹ̀ ya. Èmi ti sọ̀rọ̀ ni Olúwa Olódùmarè wí.
Na nei vaiteh be na yawn han. Manang na kâbang sak vaiteh, a sanu hah hawng pouh han, bangkongtetpawiteh kai ni ka dei toe telah Bawipa Jehovah ni a dei.
35 “Nítorí náà báyìí ní Olúwa Olódùmarè wí: Níwọ́n bí ìwọ ti gbàgbé mi, tí ìwọ sì ti fi mi sí ẹ̀yìn rẹ, ìwọ gbọdọ̀ gba àbájáde ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ àti panṣágà rẹ.”
Hatdawkvah Bawipa Jehovah ni hettelah a dei. Kâ na poe na hnin teh na kamlang takhai dawkvah, na cuknae hoi na kâyonae phu hah na phu hanelah ao.
36 Olúwa sọ fún mi pé: “Ọmọ ènìyàn, ń jẹ́ ìwọ yóò ṣe ìdájọ́ Ohola àti Oholiba? Nítorí náà dojúkọ wọn nípa ìkórìíra tí wọn ń ṣe,
Hothloilah BAWIPA ni kai koe lawk bout na dei pouh, tami capa Oholah hi Oholibah teh lawk na ceng han na maw. Panuet a thonae hah ahnimouh koe na pâpho han.
37 nítorí wọn ti dá ẹ̀ṣẹ̀ panṣágà ẹ̀jẹ̀ sì wà ní ọwọ́ wọn. Wọn dá ẹ̀ṣẹ̀ panṣágà pẹ̀lú àwọn òrìṣà wọn; kódà wọ́n fi àwọn ọmọ wọn tí wọn bí fún ni ṣe ìrúbọ, gẹ́gẹ́ bí oúnjẹ fún wọn.
Bangkongtetpawiteh, a uicuk awh, a thi hah a kut dawk a kâhluk teh, amamae meikaphawk koe a kâyo awh. Kai hanelah a khe e a capanaw hah, ahnimouh koe hmaisawi thueng hanelah a poe awh.
38 Bákan náà ni wọ́n ti ṣe èyí náà sí mi. Ní àkókò kan náà wọn ba ibi mímọ́ mi jẹ́, wọ́n sì lo ọjọ́ ìsinmi mi ní àìmọ́.
Hothloilah kai koe hetheh a sak awh, ahnimouh ni ka min kathoung hah a khin sak awh teh, kaie sabbath hai a tapoe awh.
39 Ní ọjọ́ náà gan an wọ́n fi àwọn ọmọ wọn rú ẹbọ sí àwọn òrìṣà, wọn wọ ibi mímọ́ mi lọ wọn sì lò ó ní ìlòkulò. Ìyẹn ní wọn ṣe ní ilé mi.
Amamae meikaphawk hanelah a canaw a thei awh hnukkhu, a mamanaw letlang hah, kaie hmuen kathoung kamhnawng sak hanelah a kâen awh. Khenhaw, hettelah ka imthung roeroe vah ouk a sak awh.
40 “Wọn tilẹ̀ rán oníṣẹ́ sí àwọn ènìyàn tí wọ́n wá láti ọ̀nà jíjìn, nígbà tí wọ́n dé, ìwọ wẹ ara rẹ fún wọn, ìwọ kún ojú rẹ, ìwọ sì fi ọ̀ṣọ́ iyebíye sára.
Hat dueng nahoeh rah, kho hlanae koe kaawm e hah a tho nahan lawk na thui awh teh, patoune hah na patoun awh. Khenhaw a tho awh teh, ahnimouh kecu dawk na kamhluk teh, na mit dawk puk na hluk teh, aphunphun lah kamthoupnae hoi na kamthoup.
41 Ìwọ jókòó lórí ibùsùn ti o lẹ́wà, pẹ̀lú tábìlì tí a tẹ́ ní iwájú rẹ lórí, èyí tí o gbé tùràrí àti òróró tí ó jẹ́ tèmi kà.
Kahawi e tahungnae dawk na tahung teh, a hmalah caboi na hung teh hmuitui hoi satui hah hote hmuen koe na pâhung.
42 “Ariwo ìjọ ènìyàn tí kò bìkítà wà ní àyíká rẹ̀; a mú àwọn ara Sabeani láti aginjù pẹ̀lú àwọn ọkùnrin láti ara àwọn ọ̀pọ̀ ènìyàn aláìníláárí, wọ́n sì mú àwọn ẹ̀gbà ọrùn ọwọ́ sí àwọn ọwọ́ obìnrin náà àti ẹ̀gbọ́n rẹ̀, adé dáradára sì wà ní orí wọn.
A nawmnae lahoi taminaw a hramnae hai ka thai. Alouke taminaw hoi kahrawng hoi rei a tho awh teh, a kut dawk laikaw, a lû dawk kahawipoung e bawilakhungnaw a kâmuk, yamu ka parui e hai a thokhai awh.
43 Lẹ́yìn náà mo sọ̀rọ̀ nípa èyí tí ó lo ara rẹ̀ sá nípa panṣágà ṣíṣe, ‘Nísinsin yìí jẹ kí wọn lo o bí panṣágà, nítorí gbogbo ohun tí ó jẹ́ nìyẹn.’
Kai ni ka uicuk tangcoung e napui hah a yonkhai ngai awh han na maw telah ka ti.
44 Wọn ba sùn bí ọkùnrin ti bá panṣágà sùn, bẹ́ẹ̀ ni wọ́n ṣe sùn pẹ̀lú obìnrin onífẹ̀kúfẹ̀ẹ́, Ohola àti Oholiba.
Kâyawtnaw koe a cei awh toteh, ahnimouh koe mingming doeh a kâen awh. Hottelah ka cuk e napui Oholah hoi Oholibah koe a kâen awh.
45 Ṣùgbọ́n àwọn ọkùnrin olódodo yóò pàṣẹ pé kí wọ́n fi ìyà jẹ àwọn obìnrin tí ó dá ẹ̀ṣẹ̀ àgbèrè tí ó sì ta ẹ̀jẹ̀ sílẹ̀ nítorí pé panṣágà ni wọ́n ẹ̀jẹ̀ sì wà ní ọwọ́ wọn.
Hateiteh, tamikalan ni ka uicuk e hoi kaawm e napui hoi ka tami ka thet e napui lawkceng e patetlah lawk a ceng awh han. Bangkongtetpawiteh, ka uicuk e hoi kaawm e a kâbet.
46 “Èyí ni ohun tí Olúwa Olódùmarè wí: Mú àgbájọ àwọn ènìyànkénìyàn wá sọ́dọ̀ wọn ki ó sì fi wọn lé ọwọ́ ìpayà àti ìkógun.
Bangkongtetpawiteh, Bawipa Jehovah ni hettelah a dei. Nangmouh taran e lahoi tamihu hah ka coun han. Na lawp awh vaiteh, ka patawpoung lah na katin sak han.
47 Àwọn ènìyànkénìyàn náà yóò sọ wọ́n ni òkúta, yóò sì gé wọn lulẹ̀ pẹ̀lú idà wọn; wọn ó sì pa àwọn ọmọkùnrin àti àwọn ọmọbìnrin wọn, wọ́n ó sì jó àwọn ilé wọn kanlẹ̀.”
Hahoi kamkhueng e tamihu ni talung hoi na dei awh han. Tahloi hoi na bouk awh vaiteh, a canunaw hoi a capanaw a thei awh han. A imnaw hai hmai be a sawi pouh.
48 “Èmi yóò sì fi òpin sí ìwà ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ ni ilẹ̀ náà, kí gbogbo àwọn obìnrin le gba ìkìlọ̀ kí wọn kí ó ma sì ṣe fi ara wé ọ.
Napuinaw pueng ni, cuknae hah sak hane nahoeh tie a panue thai awh nah, het patetlah cuknae hah ram thung hoi ka pahma han.
49 Ìwọ yóò sì jìyà fún ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ rẹ, ìwọ yóò sì gba àbájáde àwọn ẹ̀ṣẹ̀ panṣágà tí o dá. Nígbà náà ìwọ yóò mọ̀ pé èmi ni Olúwa Olódùmarè.”
Namamae lathueng na cuknae hah a moi na pathung awh vaiteh, meikaphawk yonnae hah na khan awh han. Hahoi kai heh Bawipa Jehovah lah ka o tie na panue awh han telah a ti.

< Ezekiel 23 >