< Ezekiel 23 >

1 Ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá:
BOEIPA ol te kai taengla ha pawk tih,
2 “Ọmọ ènìyàn, obìnrin méjì wà, ọmọ ìyá kan náà.
“Hlang capa aw, manu pakhat kah a canu huta panit om.
3 Wọn ń ṣe panṣágà ní Ejibiti, wọn ń ṣe panṣágà láti ìgbà èwe wọn. Ní ilẹ̀ yẹn ni wọn ti fi ọwọ́ pa ọyàn wọn, níbẹ̀ ni wọn sì fọwọ́ pa igbá àyà èwe wọn.
Tedae a camoe lamloh pahoi cukhalh rhoi tih Egypt ah cukhalh rhoi. A rhangsuk te a duep rhoi tih a cuemnah sukbam te hnap a saii.
4 Èyí ẹ̀gbọ́n ń jẹ́ Ohola, àbúrò rẹ̀ sì ń jẹ́ Oholiba. Tèmi ni wọ́n, wọ́n sì bí àwọn ọmọkùnrin àti àwọn ọmọbìnrin. Ohola ni Samaria, Oholiba sì ni Jerusalẹmu.
A ming ah a ham te Oholah tih a mana te Oholibah ni. Ka taengah a om rhoi hatah canu capa a sak rhoi tih a ming ah Samaria Oholah neh Jerusalem Oholibah la om.
5 “Ohola ń ṣe panṣágà nígbà tí ó sì jẹ́ tèmi; Ó sì ṣe ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ sí àwọn olólùfẹ́ rẹ̀, àwọn jagunjagun ará Asiria.
Oholah he kai hmanah cukhalh tih a lungnah khoyoei Assyria taengah pumben coeng.
6 Aṣọ aláró ni a fi wọ̀ wọ́n, àwọn gómìnà àti àwọn balógun, gbogbo wọn jẹ́ ọ̀dọ́mọkùnrin arẹwà àwọn tí ń gun ẹṣin.
Rhalboei rhoek kah pueinak thim neh, ukkung tongpang naidoeh rhoek, amih marhang dongah aka ngol khaw marhang caem boeih ni.
7 O fi ara rẹ̀ fún gbajúmọ̀ ọkùnrin Asiria gẹ́gẹ́ bí panṣágà obìnrin, o fi òrìṣà gbogbo àwọn tí ó ní ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ sí i sọ ara rẹ̀ di aláìmọ́,
Amih taengkah a cukhalhnah te amih Assyria koca kah hlangrhoei boeih taengah a paek uh tih amih kah mueirhol cungkuem neh aka pumben boeih taengah poeih uh.
8 kò fi ìwà panṣágà tí ó ti bẹ̀rẹ̀, ni Ejibiti sílẹ̀, ní ìgbà èwe rẹ̀ àwọn ọkùnrin n bá a sùn, wọn fi ọwọ́ pa àyà èwe rẹ̀ lára wọn sì ń ṣe ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ sí i.
Egypt lamkah a cukhalhnah te toeng pawt tih a camoe pueng ah anih te a ih puei uh. Amih taengah ah a cuemnah sukbam te a saii tih a cukhalhnah te amah soah a hawk uh.
9 “Nítorí náà mo fi i sílẹ̀ fún àwọn olólùfẹ́ rẹ̀, ará Asiria, tí ó ní ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ sí i.
Te dongah anih te a lungnah kut a pumben Assyria ca rhoek kut ah ka paek.
10 Wọ́n bọ́ ọ sí ìhòhò, wọ́n sì gba àwọn ọmọkùnrin àti ọmọbìnrin rẹ̀ wọn sì pa wọn pẹ̀lú idà. Ó di ẹni ìfisọ̀rọ̀ sọ láàrín àwọn obìnrin wọ́n sì fi ìyà jẹ ẹ́.
Amih loh a capa rhoek neh a canu kah a yah te a poelyoe uh. A khuen uh tih anih te cunghang neh a ngawn uh. Te dongah huta khuiah a ming om tih tholhphu te anih soah a suk uh.
11 “Àbúrò rẹ̀ Oholiba rí èyí, síbẹ̀ nínú ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ àti panṣágà rẹ̀, Ó ba ara rẹ jẹ́ ju ẹ̀gbọ́n rẹ̀ lọ.
A mana Oholibah loh a hmuh vaengah a cuknah dongah poci ngai tih a cukhalhnah neh a maya kah pumyoihnah lakah nah.
12 Òun náà ní ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ sí ará Asiria àwọn gómìnà àti àwọn balógun, jagunjagun nínú aṣọ ogun, àwọn tí ń gun ẹṣin, gbogbo àwọn ọ̀dọ́mọkùnrin arẹwà.
Assyria hlang rhoek neh pueinak aka soep ukkung hmaiben, amih boeih tongpang naidoeh, marhang dongah aka ngol marhang caem kah rhalboei te a pumben.
13 Mo rí i pé òun náà ba ara rẹ̀ jẹ́; àwọn méjèèjì rìn ojú ọ̀nà kan náà.
Te dongah longpuei pakhat ah a boktlap la a poeih uh te ka hmuh.
14 “Ṣùgbọ́n ó tẹ̀síwájú nínú ṣíṣe panṣágà. O ri àwòrán àwọn ọkùnrin lára ògiri, àwòrán àwọn ara Kaldea àwòrán pupa,
Tedae a cukhalhnah te a koei tih hlang a hmuh te pangbueng dongah a vuel. Khalden, Khalden kah mueihlip tah pangcik neh a tarhit pah.
15 pẹ̀lú ìgbànú ni ìdí wọn àti àwọn ìgbàrí ni orí wọn; gbogbo wọn dàbí olórí kẹ̀kẹ́ ogun Babeli ọmọ ìlú Kaldea.
A cinghen ah hailaem phaivaep neh a lu kah lupong khaw cawklawih. Amih boeilu boeih kah a mueimae he a pacaboeina khohmuen kah Khalden Babylon ca phek ni.
16 Ní kété tí ó rí wọn, ó ní ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ sí wọn, ó sì rán oníṣẹ́ sí wọn ni Kaldea.
A mik dongah a mueimae dongah amih te a pumben a pumben tih Khalden kah amih taengah puencawn te a tueih.
17 Àwọn ará Babeli wá sọ́dọ̀ rẹ̀, lórí ibùsùn ìfẹ́, nínú ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ wọn, wọ́n bà á jẹ́. Lẹ́yìn ìgbà tí wọ́n bà á jẹ́ tán, ó yípadà kúrò lọ́dọ̀ wọn ní ìtìjú.
Te vaengah Babylon ca rhoek tah a taengkah a hlo thingkong dongla ha pawk tih anih te amih cukhalhnah neh a poeih uh. Amih loh a poeih daengah a hinglu te amih taeng lamloh a hoeng.
18 Nígbà tí ó tẹ̀síwájú nínú iṣẹ́ panṣágà rẹ̀ ní gbangba wọ́n sì tú u sí ìhòhò, mo yí padà kúrò lọ́dọ̀ rẹ̀ ní ìtìjú, gẹ́gẹ́ bí mo ti yípadà kúrò lọ́dọ̀ ẹ̀gbọ́n rẹ̀.
A cukhalhnah a poelyoe tih a yah a hliphen. Ka hinglu loh a maya a moeng bangla anih taeng lamloh ka hinglu a hoeng.
19 Síbẹ̀síbẹ̀ ó ń pọ̀ sí i nínú ìdàpọ̀ rẹ̀ bí ó ti ń rántí ìgbà èwe rẹ̀ tí ó jẹ́ panṣágà ní Ejibiti.
A camoe tue vaengah Egypt khohmuen ah a cukhalh thoelh ham nim te a cukhalhnah loh ping.
20 Nítorí ó fẹ́ olùfẹ́ àwọn olùfẹ́ wọn ní àfẹ́jù, tí àwọn tí nǹkan ọkùnrin wọn dàbí ti kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́, àwọn ẹni tí ìtújáde ara wọn dàbí ti àwọn ẹṣin.
A taengcaeh rhoek hnukah pumben. Amih saa tah laak saa tih amih yangtui tah marhang yangtui pawn ni.
21 Báyìí ni ìwọ pe ìwà ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ ìgbà èwe rẹ wá sí ìrántí, ní ti rírin orí ọmú rẹ láti ọwọ́ àwọn ará Ejibiti, fún ọmú ìgbà èwe rẹ.
Na camoe kah khonuen rhamtat te na hue vaengah na camoe kah rhangsuk neh na sukbam Egypt ah na duep.
22 “Nítorí náà, Oholiba, báyìí ní Olúwa Olódùmarè wí, Èmi yóò gbé olólùfẹ́ rẹ dìde sí ọ, àwọn tí o kẹ́yìn si ní ìtìjú, èmi yóò sì mú wọn dojúkọ ọ́ ní gbogbo ọ̀nà
Te dongah Oholibah aw, ka Boeipa Yahovah loh he ni a thui. Kai loh nang taengkah na lungnah te ka haeng coeng ne. Na hinglu lohamih te a moeng dae amih te a kaepvai lamloh nang taengla kang khuen ni.
23 àwọn ará Babeli àti gbogbo ara Kaldea àwọn ọkùnrin Pekodi àti Ṣoa àti Koa àti gbogbo ará Asiria pẹ̀lú wọn, àwọn ọ̀dọ́mọkùnrin arẹwà, gbogbo àwọn gómìnà àti balógun, olórí oníkẹ̀kẹ́ ogun àti àwọn onípò gíga, gbogbo àwọn tí ń gun ẹṣin.
Babylon ca rhoek neh Pekod Khalden boeih khaw, Shoa neh Koa, amih taengkah Assyria koca boeih, rhalboei naidoeh tongpang neh amih boeilu ukkung boeih khaw marhang dongah aka ngol la boeih a khue uh.
24 Wọn yóò wa dojúkọ ọ pẹ̀lú ohun ìjà, kẹ̀kẹ́ ogun pẹ̀lú kẹ̀kẹ́ ẹrù àti pẹ̀lú ìwọ́jọpọ̀ ènìyàn; wọn yóò mú ìdúró wọn lòdì sí ọ ní gbogbo ọ̀nà pẹ̀lú asà ńlá àti kékeré pẹ̀lú àṣíborí. Èmi yóò yí ọ padà sí wọn fun ìjìyà, wọn yóò sì fi ìyà jẹ ọ gẹ́gẹ́ bí wọn tí tó.
Nang taengah leng neh humhae cungpoel khaw, pilnam hlangping te photlinglen neh photlingca neh lumuek neh ha pawk uh vetih na kaepvai ah a khueh uh ni. Amih mikhmuh ah laitloeknah kang khueh vetih amih kah laitloeknah neh nang lai kan tloek ni.
25 Èmi yóò sì dojú ìbínú owú mi kọ ọ́, wọn yóò sì fìyà jẹ ọ́ ní ìrunú. Wọ́n yóò gé àwọn imú àti àwọn etí yín kúrò, àwọn tí ó kù nínú yín yóò ti ipá idà ṣubú. Wọn yóò mú àwọn ọmọkùnrin àti àwọn ọmọkùnrin yín lọ, àwọn tí o kù nínú yín ni iná yóò jórun.
Ka thatlainah he nang taengah kam paek vetih nang te kosi neh n'saii uh ni. Na hnarhong neh na hna te han hlap uh vetih na hmailong ah cunghang loh a cungku sak ni. Na capa neh na canu a khuen uh vetih na hmailong ah hmai loh a hlawp uh ni.
26 Wọn yóò sì kó àwọn aṣọ àti àwọn ohun ọ̀ṣọ́ iyebíye yín.
Nang te na himbai ham pit uh vetih na boeimang hnopai khaw han loh uh ni.
27 Èmi yóò sì fi òpin sí ìwà ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ àti iṣẹ́ panṣágà tí ẹ bẹ̀rẹ̀ ni Ejibiti. Ẹ̀yin kò ní wo àwọn nǹkan wọ̀nyí pẹ̀lú ìpòùngbẹ, bẹ́ẹ̀ ni ẹ kò ní rántí Ejibiti mọ.
Te vaengah nang lamkah na khonuen rhamtat neh Egypt khohmuen lamkah na thurha te ka kangkuen sak ni. Te daengah ni amih soah mik na huel pawt vetih Egypt khaw koep na poek pawt eh.
28 “Nítorí báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí: Èmi yóò fi ọ lé ọwọ́ àwọn tí ó kórìíra, lọ́wọ́ àwọn ẹni tí ọkàn rẹ ti ṣí kúrò.
Te dongah ka Boeipa Yahovah loh he ni a thui. Kai loh nang te rhoek kut ah kan tloeng coeng ne. Te rhoek kut te na hmuhuet tih na hinglu loh amih te a moeng dae ta.
29 Wọn yóò fìyà jẹ ọ́ pẹ̀lú ìkórìíra, wọn yóò sì kó gbogbo ohun tí o ṣiṣẹ́ fún lọ. Wọn yóò fi ọ́ sílẹ̀ ní ìhòhò goloto, ìtìjú iṣẹ́ panṣágà rẹ ni yóò farahàn. Ìwà ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ rẹ̀ àti panṣágà rẹ.
Hmuhuetnah neh nang te n'saii uh vetih na thaphu boeih han loh uh ni. Nang te pumtling neh yangyal la n'hnoo uh vetih na yah neh pumyoihnah, na khonuen rhamtat neh na cukhalhnah a hliphen ni.
30 Èmi yóò ṣe gbogbo nǹkan wọ̀nyí sí ọ, nítorí ìwọ ti bá àwọn kèfèrí ṣe àgbèrè lọ, o sì fi àwọn òrìṣà wọn ba ara rẹ̀ jẹ́.
Namtom hnukah na cukhalh tih amih kah mueirhol neh na poeih uh dongah ni te rhoek te nang soah a saii.
31 Ìwọ ti rin ọ̀nà ti ẹ̀gbọ́n rẹ rìn, Èmi yóò sì fi ago rẹ̀ lé ọ lọ́wọ́.
Na maya kah longpuei ah na pongpa dongah a boengloeng te nang kut ah kam paek ni.
32 “Èyí yìí ní ohun ti Olúwa Olódùmarè wí: “Ìwọ yóò mu nínú ago ẹ̀gbọ́n rẹ, ago tí ó tóbi tí ó sì jinnú: yóò mú ìfiṣẹ̀sín àti ìfiṣe ẹlẹ́yà wá, nítorí tí ago náà gba nǹkan púpọ̀.
Ka Boeipa Yahovah loh he ni a thui. Na maya boengloeng te ki na ok vaengah nueihcil la om mungkung vetih tamdaengnah te muep eal ni.
33 Ìwọ yóò mu àmupara àti ìbànújẹ́, ago ìparun àti ìsọdahoro ago ẹ̀gbọ́n rẹ Samaria.
Rhuihahnah neh kothae, na maya Samaria kah imsuep boengloeng neh khopong boengloeng na hah bitni.
34 Ìwọ yóò mú un ni àmugbẹ; ìwọ yóò sì fọ sí wẹ́wẹ́ ìwọ yóò sì fa ọmú rẹ̀ ya. Èmi ti sọ̀rọ̀ ni Olúwa Olódùmarè wí.
Te te na ok tih na caep phoeiah a paikaek te na cilh vetih na rhangsuk na phuet ni. Ka Boeipa Yahovah kamah loh olphong ka thui coeng.
35 “Nítorí náà báyìí ní Olúwa Olódùmarè wí: Níwọ́n bí ìwọ ti gbàgbé mi, tí ìwọ sì ti fi mi sí ẹ̀yìn rẹ, ìwọ gbọdọ̀ gba àbájáde ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ àti panṣágà rẹ.”
Te dongah ka Boeipa Yahovah loh he ni a thui. Kai nan hnilh tih na nam la kai nan rhoe dongah namah loh namah kah khonuen rhamtat neh na cukhalhnah te khaw phuei laeh,” a ti.
36 Olúwa sọ fún mi pé: “Ọmọ ènìyàn, ń jẹ́ ìwọ yóò ṣe ìdájọ́ Ohola àti Oholiba? Nítorí náà dojúkọ wọn nípa ìkórìíra tí wọn ń ṣe,
Te phoeiah BOEIPA loh kai taengah, “Hlang capa aw, Oholah neh Oholibah te lai na tloek tih amih rhoi kah tueilaehkoi te amih rhoi taengah na thui aya?
37 nítorí wọn ti dá ẹ̀ṣẹ̀ panṣágà ẹ̀jẹ̀ sì wà ní ọwọ́ wọn. Wọn dá ẹ̀ṣẹ̀ panṣágà pẹ̀lú àwọn òrìṣà wọn; kódà wọ́n fi àwọn ọmọ wọn tí wọn bí fún ni ṣe ìrúbọ, gẹ́gẹ́ bí oúnjẹ fún wọn.
Samphaih uh tih a kut ah thii kap. A mueirhol neh samphaih uh tih kai ham a sak a ca rhoek pataeng amih taengah toihthing bangla a cum uh.
38 Bákan náà ni wọ́n ti ṣe èyí náà sí mi. Ní àkókò kan náà wọn ba ibi mímọ́ mi jẹ́, wọ́n sì lo ọjọ́ ìsinmi mi ní àìmọ́.
Kai taengah a saii rhoi he khaw te khohnin ah ka rhokso ni a poeih rhoi tih ka Sabbath ni a poeih rhoi.
39 Ní ọjọ́ náà gan an wọ́n fi àwọn ọmọ wọn rú ẹbọ sí àwọn òrìṣà, wọn wọ ibi mímọ́ mi lọ wọn sì lò ó ní ìlòkulò. Ìyẹn ní wọn ṣe ní ilé mi.
Te vaengah a ca rhoek te a mueirhol ham a ngawn uh tih te khohnin ah ka rhokso te poeih ham a kun thil uh. Te dongah ka im khui ah a saii uh tangkhuet he.
40 “Wọn tilẹ̀ rán oníṣẹ́ sí àwọn ènìyàn tí wọ́n wá láti ọ̀nà jíjìn, nígbà tí wọ́n dé, ìwọ wẹ ara rẹ fún wọn, ìwọ kún ojú rẹ, ìwọ sì fi ọ̀ṣọ́ iyebíye sára.
Amih taengah puencawn la a tueih tih khohla bangsang lamloh aka pawk hlang ham pataeng khaw a tueih thiluh. Ha pawk uh vaengah tuihlu lamtah na mik duum ne. Te phoeiah cangen te oi ne.
41 Ìwọ jókòó lórí ibùsùn ti o lẹ́wà, pẹ̀lú tábìlì tí a tẹ́ ní iwájú rẹ lórí, èyí tí o gbé tùràrí àti òróró tí ó jẹ́ tèmi kà.
Khuehtawn thingkong dongah na ngol tih a mikhmuh ah caboei a phaih. Kai kah bo-ul neh ka situi tah amah dongah na khueh van.
42 “Ariwo ìjọ ènìyàn tí kò bìkítà wà ní àyíká rẹ̀; a mú àwọn ara Sabeani láti aginjù pẹ̀lú àwọn ọkùnrin láti ara àwọn ọ̀pọ̀ ènìyàn aláìníláárí, wọ́n sì mú àwọn ẹ̀gbà ọrùn ọwọ́ sí àwọn ọwọ́ obìnrin náà àti ẹ̀gbọ́n rẹ̀, adé dáradára sì wà ní orí wọn.
A kaepvai hlangping kah thayoeituipan ol neh bitun tongpa khuikah hlang khaw, khosoek lamkah yumii, yumii khaw hang khuen. Te vaengah a kut dongkah khungpak neh a lu dongah boeimang rhuisam a khuem uh.
43 Lẹ́yìn náà mo sọ̀rọ̀ nípa èyí tí ó lo ara rẹ̀ sá nípa panṣágà ṣíṣe, ‘Nísinsin yìí jẹ kí wọn lo o bí panṣágà, nítorí gbogbo ohun tí ó jẹ́ nìyẹn.’
Te vaengah, 'Samphaihnah neh rhuem coeng tih anih ham tah a cukhalhnah dongah cukhalh la cukhalh laeh saeh,’ ka ti.
44 Wọn ba sùn bí ọkùnrin ti bá panṣágà sùn, bẹ́ẹ̀ ni wọ́n ṣe sùn pẹ̀lú obìnrin onífẹ̀kúfẹ̀ẹ́, Ohola àti Oholiba.
Pumyoi nu taengah aka kun bangla anih te a paan uh. Te dongah khonuen rhamtat nu Oholah taeng neh Oholibah taengla pawk uh tangkhuet.
45 Ṣùgbọ́n àwọn ọkùnrin olódodo yóò pàṣẹ pé kí wọ́n fi ìyà jẹ àwọn obìnrin tí ó dá ẹ̀ṣẹ̀ àgbèrè tí ó sì ta ẹ̀jẹ̀ sílẹ̀ nítorí pé panṣágà ni wọ́n ẹ̀jẹ̀ sì wà ní ọwọ́ wọn.
Tedae amih hlang dueng loh amih te samphaih laitloeknah neh thii hawk kah laitloeknah dongah lai a tloek uh ni. Amih te samphaih uh tih a kut ah thii kap.
46 “Èyí ni ohun tí Olúwa Olódùmarè wí: Mú àgbájọ àwọn ènìyànkénìyàn wá sọ́dọ̀ wọn ki ó sì fi wọn lé ọwọ́ ìpayà àti ìkógun.
Ka Boeipa Yahovah loh he ni a thui. Amih te hlangping paan sak lamtah amih te ngaihuetnah neh maeh la pae.
47 Àwọn ènìyànkénìyàn náà yóò sọ wọ́n ni òkúta, yóò sì gé wọn lulẹ̀ pẹ̀lú idà wọn; wọn ó sì pa àwọn ọmọkùnrin àti àwọn ọmọbìnrin wọn, wọ́n ó sì jó àwọn ilé wọn kanlẹ̀.”
Amih te hlangping loh lungto neh dae saeh lamtah amih te a cunghang neh hum saeh. A ca tongpa rhoek neh a ca huta rhoek te a ngawn pah vetih a im te hmai neh a hoeh uh ni.
48 “Èmi yóò sì fi òpin sí ìwà ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ ni ilẹ̀ náà, kí gbogbo àwọn obìnrin le gba ìkìlọ̀ kí wọn kí ó ma sì ṣe fi ara wé ọ.
Tedae khohmuen kah na khonuen rhamtat te ka paa sak daengah ni huta boeih te thuituen uh vetih nangmih kah khonuen rhamtat bangla a saii uh pawt eh.
49 Ìwọ yóò sì jìyà fún ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ rẹ, ìwọ yóò sì gba àbájáde àwọn ẹ̀ṣẹ̀ panṣágà tí o dá. Nígbà náà ìwọ yóò mọ̀ pé èmi ni Olúwa Olódùmarè.”
Nangmih kah khonuen rhamtat te namamih soah han tloeng vetih na mueirhol tholhnah khaw na phueih ni. Te vaengah ka Boeipa Yahovah kamah he nan ming uh bitni.

< Ezekiel 23 >