< Ezekiel 22 >
HIKI mai la ka olelo a Iehova ia'u, i mai la,
2 “Ọmọ ènìyàn ǹjẹ́ ìwọ yóò ha ṣe ìdájọ́ rẹ̀? Ǹjẹ́ ìwọ ha ṣe ìdájọ́ ìlú atàjẹ̀sílẹ̀? Tó bá rí bẹ́ẹ̀ dojúkọ wọn pẹ̀lú gbogbo ìwà ìríra wọn.
Ano hoi, e ke keiki a ke kanaka, e hoohewa anei oe, e hoohewa oe i ke kulanakauhale koko? Oia, e hoike no oe ia ia i kona mau mea a pau i inainaia.
3 Kí ó sì wí pé, ‘Èyí yìí ní ohun tí Olúwa Olódùmarè wí: Ìwọ ìlú ńlá tí ó mú ìparun wá sórí ara rẹ nípa títàjẹ̀sílẹ̀ ní àárín rẹ, tí ó sì ba ara rẹ̀ jẹ́ nípa ṣíṣe àwọn ère.
E olelo aku oe, Ke i mai nei Iehova ka Huku, penei; Ke hookahe nei ke kulanakauhale i ke koko iwaenakonu ona, i hiki mai kona manawa, a ua hana oia i na akua kii e ku e ia ia iho, e hoohaumia ia ia iho.
4 Ìwọ ti jẹ̀bi nítorí ẹ̀jẹ̀ tí ìwọ ti ta sílẹ̀, àti pé àwọn ère tí ó ṣe tí bà ọ́ jẹ́. Ìwọ tí mú ọjọ́ rẹ súnmọ́ tòsí, ìparí àwọn ọdún rẹ sì ti dé. Nítorí náà èmi yóò fi ọ ṣe ohun ẹ̀gàn lójú àwọn orílẹ̀-èdè àti ohun ẹ̀sín lójú gbogbo ìlú.
I ke koko au i hookahe ai, ua hewa oe, a ma na akua kii au i hana'i, ua hoohaumia oe ia oe iho; a ua hookokoke no oe i kou mau la, a ua hiki mai hoi i kou mau makahiki; nolaila i hoolilo aku ai au ia oe i mea e hoinoia e na lahuikanaka, a i mea e henehene ai ko na aina a pau.
5 Àwọn tí ó wà ní tòsí àti àwọn tí ó jìnnà sí ọ, yóò fi ọ ṣe ẹlẹ́yà, ìwọ ìlú ẹlẹ́gàn, tí ó kún fún làálàá.
O ka poe kokoke mai a me ka poe mamao aku ia oe, e henehene no lakou ia oe ka mea inoa haumia, a ua hoouluhua nui ia.
6 “‘Wo bí ọ̀kọ̀ọ̀kan nínú àwọn ọmọbìnrin ọba Israẹli tí ó wà nínú yín ti ń lo agbára rẹ̀ láti tàjẹ̀ sílẹ̀.
Eia hoi, o na'lii o ka Iseraela, kela mea keia mea iloko ou ma ka hookahe koko lakou me ko lakou ikaika.
7 Nínú rẹ wọn ti hùwà sí baba àti ìyá pẹ̀lú ìfojú tínrín; nínú rẹ wọn ti ni àwọn àlejò lára, wọn sì hùwàkiwà sí aláìní baba àti opó.
O ka makuakane a me ka makuwahine ka lakou i hoowahawaha ai iloko ou; ma ka hooluhihewa i hana aku ai lakou i ka malihini iloko ou; a maloko ou i hoopilikia ai lakou i na mea makua ole a me na wahine kanemake.
8 Ìwọ tí kọ àwọn ohun mímọ́ mi sílẹ̀, ìwọ sì ti lo ọjọ́ ìsinmi mi ní ìlòkulò.
Ua hoowahawaha oe i ko'u mau mea hoano, a ua hoohaumia hoi oe i ko'u mau Sabati.
9 Nínú rẹ ni àwọn ayannijẹ ènìyàn pinnu láti tàjẹ̀ sílẹ̀; nínú rẹ ní àwọn tí ó ń jẹun ní orí òkè ojúbọ òrìṣà, wọn sì hùwà ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́.
Maloko ou na kanaka holoholo olelo e hookahe i ke koko; ua ai hoi lakou maluna o na mauna iloko ou; a iwaenakonu ou ua hana lakou ma ka moe kolohe.
10 Nínú rẹ ní àwọn ti kò bu ọlá fún àwọn àkéte baba wọn; nínú rẹ ni àwọn tí o ń bá àwọn obìnrin lò nígbà tí wọ́n ń ṣe àkókò lọ́wọ́, ní àsìkò tí a ka wọn sì aláìmọ́.
Maloko ou, ua wehe lakou i kahi huna o ko lakou makuakane; a maloko ou ua hoohaahaa lakou i ka wahine i hookaawaleia'e no ka heekoko.
11 Nínú rẹ ọkùnrin kan ti dá ẹ̀ṣẹ̀ ìríra pẹ̀lú aya aládùúgbò rẹ̀, òmíràn bá ìyàwó ọmọ rẹ̀ jẹ́, òmíràn sì bá arábìnrin rẹ̀ lòpọ̀ èyí tí í ṣe ọbàkan rẹ̀.
Ua hana kekahi i ka mea inainaia me ka wahine a kona hoalauna, a ua hoohaumia kekahi i kana hunona wahine ma ka moo kolohe; a ua hoohaahaa kekahi iloko ou i kona kaikuwahine, he kaikamahine a kona makuakane.
12 Nínú rẹ àwọn ènìyàn gba àbẹ̀tẹ́lẹ̀ láti tàjẹ̀ sílẹ̀; ìwọ gba èlé ìlọ́po láti mú aláìṣòótọ́ jèrè láti ara aládùúgbò rẹ nípa ìrẹ́jẹ. Ìwọ sì ti gbàgbé èmi; ni Olúwa Olódùmarè wí.
Maloko ou ua lawe lakou i na kipe e hookahe i ke koko; ua lawe oe i ke kuala a me ka uku panee, a ua loaa ia oe me ka makee, o ka kou mau hoalauna, ma ka hooluhihewa, a ua hoopoina mai ia'u, wahi a Iehova ka Haku.
13 “‘Èmi yóò kúkú pàtẹ́wọ́ lórí èrè àìmọ̀ tí ìwọ ti jẹ, àti lórí ẹ̀jẹ̀ tí ìwọ ti ta sílẹ̀ ní àárín yín.
Nolaila ea, ua pai au i kuu mau lima i kou waiwai alunu i loaa ia oe, a me kou koko i hookaheia iwaenakonu ou.
14 Ọkàn rẹ le gbà á, tàbí ọwọ́ rẹ lè le, ní ọjọ́ tí èmi yóò bá ọ ṣé? Èmi Olúwa ti sọ̀rọ̀, Èmi yóò sì ṣe é.
E hiki anei i kou naau ke hoomanawanui, a e ikaika anei kou mau lima i na la e lalau aku ai au ia oe? Na'u na Iehova i olelo, a na'u no ia o hana.
15 Èmi yóò tú yin ká ní àárín àwọn orílẹ̀-èdè, èmi yóò fọ́n ọ ká sí àwọn ìlú; èmi yóò sì fi òpin sí àìmọ́ rẹ.
E lulu aku au ia oe iwaena o na lahuikanaka, a e hooleilei aku ia oe iwaena o na aina, a e hoopau aku i kou haumia mailoko aku ou.
16 Nígbà tí a ó bà ọ́ jẹ́ lójú àwọn orílẹ̀-èdè, ìwọ yóò mọ̀ pé, Èmi ni Olúwa.’”
A e lawe oe i kou hooilina iloko ou iho, imua i ke alo o na lahuikanaka, a e ike oe owau no Iehova.
17 Nígbà náà ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá:
Hiki mai la ka olelo a Iehova ia'u, i mai la,
18 “Ọmọ ènìyàn, ilé Israẹli ti di ìdàrọ́ sí mi; gbogbo wọn jẹ́ bàbà, idẹ, irin àti òjé ti a fi sínú iná ìléru. Wọn jẹ́ ìdàrọ́ ti fàdákà.
E ke keiki a ke kanaka, ua lilo ka ohana a Iseraela i lepo ia'u nei; o lakou a pau he keleawe, he piuta, he hao, a he kepaupoka, iloko o ka umu hoohehee; he lepo no hoi o ke kala.
19 Nítorí náà èyí yìí ni ohun ti Olúwa Olódùmarè wí: ‘Nítorí tí ìwọ ti di ìdàrọ́, èmi yóò kó yín jọ sí Jerusalẹmu.
Nolaila, wahi a Iehova ka Haku; no ka lilo ana o oukou a pau i lepo, nolaila, ea, e hoakoakoa au ia oukou iwaenakonu o Ierusalema;
20 Gẹ́gẹ́ bí ènìyàn ṣe ń kó fàdákà, bàbà, irin, òjé àti idẹ jọ sínú iná ìléru láti fi iná yọ́ ọ, bẹ́ẹ̀ ni èmi yóò kó ọ jọ ní ìbínú àti ìrunú mi, èmi yóò sì fi ọ sì àárín ìlú, èmi yóò sì yọ́ ọ. Níbẹ̀ ní ìwọ yóò sì ti yọ́.
E like me ko lakou houluulu ana i ke kala, a me ke keleawe, a me ka hao, a me ke kepaupoka a me ka piuta iwaenakonu o ka umu hoohehee, e puhi i ke ahi maluna olaila, e hoohehee iho; pela e houluulu ai au, me ko'u huhu a me ko'u ukiuki, a e waiho iho, a e hoohehee ia oukou.
21 Èmi yóò kó yín jọ, èmi o sì fín iná ìbínú mi si yin lára, ẹ o si di yíyọ́ láàrín rẹ̀.
Oia, e houluulu au ia oukou, a e puhi maluna o oukou iloko o ke ahi o ko'u ukiuki, a pau oukou i ka hooheheeia iwaenakonu ona.
22 Bí a ti ń yọ́ fàdákà nínú iná ìléru bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ ní ìwọ yóò ṣe yọ́ nínú rẹ̀, ìwọ yóò sì mọ̀ wí pé, Èmi Olúwa ti tú ìbínú mi sórí rẹ.’”
Me he kala la i hooheheeia iwaena konu o ka umu hoohehee, pela oukou e hooheheeia'i iloko ona; a e ike oukou ua ninini aku au i ko'u huhu, maluna o oukou.
23 Lẹ́ẹ̀kan sí i ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá wí pé,
Hiki mai la hoi ka olelo a Iehova ia'u, i mai la,
24 “Ọmọ ènìyàn, sọ fún ilẹ̀ náà, ‘Ìwọ ní ilẹ̀ tí kò gbá mọ́, ti kò sì rọ òjò tàbí ìrì ní àkókò ìbínú.’
E ke keiki a ke kanaka, e olelo aku oe ia ia, O oe no ka aina i waele ole ia, a i ua ole ia i ka la i huhu ai.
25 Ìdìtẹ̀ sì wà láàrín àwọn ọmọ-aládé inú rẹ̀, tó dàbí bíbú kìnnìún tó ń fà ẹran ya, wọ́n ń ba àwọn ènìyàn jẹ́, wọ́n ń kó ìṣúra àti àwọn ohun iyebíye wọ́n sì ń sọ púpọ̀ di opó nínú rẹ̀.
He ohumu kipi o kona mau kaula iwaenakonu ona, e like me ka liona e uwo ana, e haehae ana i ka mea pio; ua ai lakou i na uhane, ua lawe lakou i ke kala, a me na mea makamae; a ua hoonui lakou nona i na wahinekanemake iwaena konu ona.
26 Àwọn àlùfáà rẹ̀ ti rú òfin mi, wọn si ti sọ ohun mímọ́ mi di àìlọ́wọ̀: wọn kò fi ìyàtọ̀ sáàrín ohun mímọ́ àti àìlọ́wọ̀, bẹ́ẹ̀ ni wọn kò fi ìyàtọ̀ hàn láàrín ohun àìmọ́, àti mímọ́, wọn sì ti fi ojú wọn pamọ́ kúrò ní ọjọ́ ìsinmi mi, mó sì dí ẹni àìlọ́wọ̀ láàrín wọn.
Ua hana ino kona mau kahuna pule i kuu kanawai, a ua hoohaumia lakou i kuu mea hoano; aole lakou i hookaawale iwaena o na mea hoano a me na mea haumia, aole hoi i hoakaka lakou iwaena o ka mea maemae a me ka mea maemae ole, ua huna hoi lakou i ko lakou mau maka i ko'u mau Sabati, a ua hoohaumiaia wau iwaena o lakou.
27 Àwọn ọmọ-aládé àárín rẹ̀ dàbí ìkookò ti ń ṣọdẹ, láti tàjẹ̀ sílẹ̀, láti pa ọkàn run, láti jèrè àìṣòótọ́.
O kona mau alii, iwaenakonu ona, ua like me na ilio hihiu hae e haehae ana i ka mea pio, e hookahe i ke koko, a e luku hoi i na uhane e loaa ia lakou ka waiwai alunu.
28 Àti àwọn wòlíì rẹ́ ti ṣẹ̀tàn sí wọn, wọn ń rì ìran asán, wọn sì ń fọ àfọ̀ṣẹ èké sí wọn, wí pé, ‘Báyìí ní Olúwa Olódùmarè wí,’ nígbà tí ó ṣépè Olúwa kò sọ̀rọ̀.
Ua hamo aku kona mau kaula ia lakou me ka puna ikaika ole, e nana ana i ka mea lapuwale, a e wanana ana i na mea wahahee no lakou, e olelo ana, Ke i mai nei Iehova ka Haku penei, aole nae i olelo Iehova.
29 Àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà, tí lo ìwà ìninilára, wọn sì já olè, wọn sì ni àwọn tálákà àti aláìní lára; nítòótọ́, wọn tí ní àlejò lára láìnídìí. Kò sì ṣí ìdájọ́ òdodo.
Ua hooluhihewa na kanaka o ka aina, a kaili wale i ka mea kaili, ua hookaumaha lakou i ka mea haahaa, a me ka mea nele; oia, ua hookaumaha lakou i ka malihini ma ka pono ole.
30 “Èmi si wá ẹnìkan láàrín wọn, tí ìbá tún odi náà mọ́, tí ìbá dúró ní ibi tí ó ya náà níwájú mi fún ilẹ̀ náà, kí èmi má bá à parun: ṣùgbọ́n èmi kò rí ẹnìkan.
Imi aku la au i kahi kanaka iwaena o lakou e hana hou i ka pa, a e ku ma kahi naha imua o ko'u alo no ka aina, i ole au e luku aku ia ia; aole hoi i loaa ia'u.
31 Nítorí náà ni mo ṣe da ìbínú mi sí wọn lórí, mo ti fi iná ìbínú mi run wọn, mo si ti fi ọ̀nà wọn gbẹ̀san lórí ara wọn, ní Olúwa Olódùmarè wí.”
Nolaila ninini aku la au i ko'u ukiuki maluna o lakou, ua hoopau au ia lakou me ke ahi o ko'u huhu; o ko lakou aoao ponoi ka'u i hoopai aku ai maluna o ko lakou mau poo, wahi a Iehova ka Haku.