< Ezekiel 22 >

1 Ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá:
Kiugo kĩa Jehova nĩkĩanginyĩrĩire, ngĩĩrwo atĩrĩ:
2 “Ọmọ ènìyàn ǹjẹ́ ìwọ yóò ha ṣe ìdájọ́ rẹ̀? Ǹjẹ́ ìwọ ha ṣe ìdájọ́ ìlú atàjẹ̀sílẹ̀? Tó bá rí bẹ́ẹ̀ dojúkọ wọn pẹ̀lú gbogbo ìwà ìríra wọn.
“Mũrũ wa mũndũ, nĩũkũrĩtuĩra ciira? Nĩũgũtuĩra ciira itũũra rĩĩrĩ inene rĩitithagia thakame? Nĩ ũndũ ũcio rĩonie maũndũ marĩa mothe rĩĩkaga marĩ magigi,
3 Kí ó sì wí pé, ‘Èyí yìí ní ohun tí Olúwa Olódùmarè wí: Ìwọ ìlú ńlá tí ó mú ìparun wá sórí ara rẹ nípa títàjẹ̀sílẹ̀ ní àárín rẹ, tí ó sì ba ara rẹ̀ jẹ́ nípa ṣíṣe àwọn ère.
ũrĩĩre atĩrĩ, ‘Mwathani Jehova ekuuga atĩrĩ: Wee itũũra inene rĩrĩa rĩĩrehithagĩria mũtino nĩ ũndũ wa gũitithia thakame kũu thĩinĩ warĩo, na rĩgethaahia nĩ ũndũ wa gũthondeka mĩhianano,
4 Ìwọ ti jẹ̀bi nítorí ẹ̀jẹ̀ tí ìwọ ti ta sílẹ̀, àti pé àwọn ère tí ó ṣe tí bà ọ́ jẹ́. Ìwọ tí mú ọjọ́ rẹ súnmọ́ tòsí, ìparí àwọn ọdún rẹ sì ti dé. Nítorí náà èmi yóò fi ọ ṣe ohun ẹ̀gàn lójú àwọn orílẹ̀-èdè àti ohun ẹ̀sín lójú gbogbo ìlú.
nĩũhĩtĩtie nĩ ũndũ wa thakame ĩrĩa ũitĩte, na nĩũthaahĩtio nĩ mĩhianano ĩrĩa ũthondekete. Nĩũtũmĩte matukũ maku makinye mũthia, o naguo mũthia wa mĩaka yaku nĩmũkinyu. Nĩ ũndũ ũcio nĩngatũma ũtuĩke kĩndũ kĩmeneku harĩ ndũrĩrĩ, na kĩndũ gĩa gũthekererwo nĩ mabũrũri macio mothe.
5 Àwọn tí ó wà ní tòsí àti àwọn tí ó jìnnà sí ọ, yóò fi ọ ṣe ẹlẹ́yà, ìwọ ìlú ẹlẹ́gàn, tí ó kún fún làálàá.
Andũ arĩa marĩ gũkuhĩ na arĩa marĩ kũraya nĩmagakũnyũrũragia, wee itũũra rĩĩrĩ inene ũrĩ ngumo njũru, na ũkaiyũra ngũĩ.
6 “‘Wo bí ọ̀kọ̀ọ̀kan nínú àwọn ọmọbìnrin ọba Israẹli tí ó wà nínú yín ti ń lo agbára rẹ̀ láti tàjẹ̀ sílẹ̀.
“‘Ta rora ũrĩa o ũmwe wa athamaki a Isiraeli arĩa marĩ thĩinĩ waku ahũthagĩra hinya wake ũũru agĩitithia thakame.
7 Nínú rẹ wọn ti hùwà sí baba àti ìyá pẹ̀lú ìfojú tínrín; nínú rẹ wọn ti ni àwọn àlejò lára, wọn sì hùwàkiwà sí aláìní baba àti opó.
Nĩmagithĩtie ithe wa ciana o na nyina gĩtĩĩo marĩ kũu thĩinĩ waku; na marĩ thĩinĩ waku nĩmahinyĩrĩirie ageni na makanyariira mwana ũrĩa ũkuĩrĩirwo nĩ ithe, o na mũtumia wa ndigwa.
8 Ìwọ tí kọ àwọn ohun mímọ́ mi sílẹ̀, ìwọ sì ti lo ọjọ́ ìsinmi mi ní ìlòkulò.
Wee-rĩ, nĩũnyararĩte indo ciakwa iria nyamũre, o na ũgathaahia Thabatũ ciakwa.
9 Nínú rẹ ni àwọn ayannijẹ ènìyàn pinnu láti tàjẹ̀ sílẹ̀; nínú rẹ ní àwọn tí ó ń jẹun ní orí òkè ojúbọ òrìṣà, wọn sì hùwà ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́.
Kũu thĩinĩ waku nĩ kũrĩ andũ maiganagĩrĩra igenyo, na mendete ũiti wa thakame; na thĩinĩ waku nĩ kũrĩ andũ marĩĩaga irio mahooero ma irĩma-igũrũ, na mageeka ciĩko cia ũũra-thoni.
10 Nínú rẹ ní àwọn ti kò bu ọlá fún àwọn àkéte baba wọn; nínú rẹ ni àwọn tí o ń bá àwọn obìnrin lò nígbà tí wọ́n ń ṣe àkókò lọ́wọ́, ní àsìkò tí a ka wọn sì aláìmọ́.
Nĩ kũrĩ andũ thĩinĩ waku mataheaga ũrĩrĩ wa maithe mao gĩtĩĩo; na thĩinĩ waku nĩ kũrĩ andũ mathũkagia atumia nĩ ũndũ wa gũthiĩ nao mahinda-inĩ mao ma mweri, ihinda-inĩ rĩrĩa marĩ na thaahu.
11 Nínú rẹ ọkùnrin kan ti dá ẹ̀ṣẹ̀ ìríra pẹ̀lú aya aládùúgbò rẹ̀, òmíràn bá ìyàwó ọmọ rẹ̀ jẹ́, òmíràn sì bá arábìnrin rẹ̀ lòpọ̀ èyí tí í ṣe ọbàkan rẹ̀.
Kũu thĩinĩ waku nĩ kũrĩ mũndũ wĩkaga maũndũ marĩ magigi na mũtumia wa mũndũ ũrĩa ũngĩ, nake ũngĩ ndangĩconoka agĩthũkia mũtumia wa mũriũ, ũngĩ nake agathũkagia mwarĩ wa nyina, o ũcio mwarĩ wa ithe.
12 Nínú rẹ àwọn ènìyàn gba àbẹ̀tẹ́lẹ̀ láti tàjẹ̀ sílẹ̀; ìwọ gba èlé ìlọ́po láti mú aláìṣòótọ́ jèrè láti ara aládùúgbò rẹ nípa ìrẹ́jẹ. Ìwọ sì ti gbàgbé èmi; ni Olúwa Olódùmarè wí.
Andũ maamũkagĩra mahaki marĩ thĩinĩ waku nĩguo maite thakame; wee ũrĩ mũrĩa-ngʼũũrũ, na nĩwamũkagĩra uumithio mũkĩru, na ũkoona uumithio ũtarĩ kĩhooto kuuma kũrĩ andũ arĩa angĩ na njĩra ya ũhahanyi. Wee nĩũriganĩirwo nĩ niĩ, ũguo nĩguo Mwathani Jehova ekuuga.
13 “‘Èmi yóò kúkú pàtẹ́wọ́ lórí èrè àìmọ̀ tí ìwọ ti jẹ, àti lórí ẹ̀jẹ̀ tí ìwọ ti ta sílẹ̀ ní àárín yín.
“‘Ti-itherũ nĩngahũũra hĩ nĩ ũndũ wa uumithio ũcio wonete ũtarĩ wa kĩhooto, na nĩ ũndũ wa thakame ĩrĩa ũitithĩtie kũu thĩinĩ waku.
14 Ọkàn rẹ le gbà á, tàbí ọwọ́ rẹ lè le, ní ọjọ́ tí èmi yóò bá ọ ṣé? Èmi Olúwa ti sọ̀rọ̀, Èmi yóò sì ṣe é.
Mũthenya ũrĩa ngaakũherithia-rĩ ũmĩrĩru waku nĩũgetiiria, kana moko maku magĩe na hinya? Niĩ Jehova nĩ niĩ njarĩtie ũhoro ũcio, na nĩ niĩ ngaawĩka.
15 Èmi yóò tú yin ká ní àárín àwọn orílẹ̀-èdè, èmi yóò fọ́n ọ ká sí àwọn ìlú; èmi yóò sì fi òpin sí àìmọ́ rẹ.
Nĩngakũharaganĩria ndũrĩrĩ-inĩ, na ngũhurunjĩre mabũrũri-inĩ; na nĩngakinyia thaahu waku mũthia.
16 Nígbà tí a ó bà ọ́ jẹ́ lójú àwọn orílẹ̀-èdè, ìwọ yóò mọ̀ pé, Èmi ni Olúwa.’”
Hĩndĩ ĩrĩa wee ũgaakorwo ũthaahĩte maitho-inĩ ma ndũrĩrĩ, nĩũkamenya atĩ niĩ nĩ niĩ Jehova.’”
17 Nígbà náà ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá:
Ningĩ kiugo kĩa Jehova gĩkĩnginyĩrĩra, ngĩĩrwo atĩrĩ:
18 “Ọmọ ènìyàn, ilé Israẹli ti di ìdàrọ́ sí mi; gbogbo wọn jẹ́ bàbà, idẹ, irin àti òjé ti a fi sínú iná ìléru. Wọn jẹ́ ìdàrọ́ ti fàdákà.
“Mũrũ wa mũndũ, harĩ niĩ-rĩ, andũ a nyũmba ĩno ya Isiraeli matuĩkĩte o ta gĩko kĩrĩa gĩtigaraga rĩrĩa cuuma ĩratherio na mwaki wa ũturi; acio othe matuĩkĩte o ta gĩcango, na ibati, na kĩgera, o na ngocorai marĩ mwaki-inĩ wa ũturi. O no ta gĩko kĩrĩa gĩtigaraga rĩrĩa betha ĩratherio na mwaki wa ũturi.
19 Nítorí náà èyí yìí ni ohun ti Olúwa Olódùmarè wí: ‘Nítorí tí ìwọ ti di ìdàrọ́, èmi yóò kó yín jọ sí Jerusalẹmu.
Nĩ ũndũ ũcio Mwathani Jehova ekuuga atĩrĩ: ‘Tondũ inyuothe nĩmũtuĩkĩte gĩko kĩrĩa gĩtigaraga rĩrĩa cuuma ĩratherio na mwaki wa ũturi, nĩngamũcookanĩrĩria kũu Jerusalemu.
20 Gẹ́gẹ́ bí ènìyàn ṣe ń kó fàdákà, bàbà, irin, òjé àti idẹ jọ sínú iná ìléru láti fi iná yọ́ ọ, bẹ́ẹ̀ ni èmi yóò kó ọ jọ ní ìbínú àti ìrunú mi, èmi yóò sì fi ọ sì àárín ìlú, èmi yóò sì yọ́ ọ. Níbẹ̀ ní ìwọ yóò sì ti yọ́.
O ta ũrĩa andũ macookanagĩrĩria betha, na gĩcango, na kĩgera, na ngocorai, o na ibati icua-inĩ rĩa mwaki nĩguo itwekio na mwaki mũhiũ-rĩ, ũguo nĩguo o na niĩ ngaamũcookanĩrĩria ndĩ na marakara na mangʼũrĩ, na ndĩmũikie kũu thĩinĩ wa itũũra inene ndĩmũtwekerie kuo.
21 Èmi yóò kó yín jọ, èmi o sì fín iná ìbínú mi si yin lára, ẹ o si di yíyọ́ láàrín rẹ̀.
Nĩngamũcookanĩrĩria na ndĩmũhurutĩre na mangʼũrĩ makwa mahiũ, na inyuĩ nĩmũgatwekerio o kũu thĩinĩ warĩo.
22 Bí a ti ń yọ́ fàdákà nínú iná ìléru bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ ní ìwọ yóò ṣe yọ́ nínú rẹ̀, ìwọ yóò sì mọ̀ wí pé, Èmi Olúwa ti tú ìbínú mi sórí rẹ.’”
O ta ũrĩa betha ĩtwekagĩrio icua-inĩ rĩa mwaki, ũguo noguo o na inyuĩ mũgaatwekerio kũu thĩinĩ warĩo, na inyuĩ nĩmũkamenya atĩ niĩ Jehova nĩ niĩ ndĩmũitĩrĩirie mangʼũrĩ makwa.’”
23 Lẹ́ẹ̀kan sí i ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá wí pé,
O rĩngĩ kiugo kĩa Jehova nĩkĩanginyĩrĩire, ngĩĩrwo atĩrĩ:
24 “Ọmọ ènìyàn, sọ fún ilẹ̀ náà, ‘Ìwọ ní ilẹ̀ tí kò gbá mọ́, ti kò sì rọ òjò tàbí ìrì ní àkókò ìbínú.’
“Mũrũ wa mũndũ, ĩra bũrũri ũcio atĩrĩ, ‘Wee-rĩ, ũrĩ bũrũri ũkoretwo wagĩte mbura kana rũthuthuũ, mũthenya ũrĩa wa mangʼũrĩ.’
25 Ìdìtẹ̀ sì wà láàrín àwọn ọmọ-aládé inú rẹ̀, tó dàbí bíbú kìnnìún tó ń fà ẹran ya, wọ́n ń ba àwọn ènìyàn jẹ́, wọ́n ń kó ìṣúra àti àwọn ohun iyebíye wọ́n sì ń sọ púpọ̀ di opó nínú rẹ̀.
Nĩ kũrĩ na ndundu ya gũũkanĩrĩra ya anene akuo marĩ thĩinĩ waguo, nao matariĩ ta mũrũũthi ũkũrarama ũgĩtambuura kĩrĩa ũnyiitĩte; marĩĩaga andũ, na magakuua mĩthithũ na indo cia goro, na magatũma kũgĩe na atumia aingĩ a ndigwa thĩinĩ waguo.
26 Àwọn àlùfáà rẹ̀ ti rú òfin mi, wọn si ti sọ ohun mímọ́ mi di àìlọ́wọ̀: wọn kò fi ìyàtọ̀ sáàrín ohun mímọ́ àti àìlọ́wọ̀, bẹ́ẹ̀ ni wọn kò fi ìyàtọ̀ hàn láàrín ohun àìmọ́, àti mímọ́, wọn sì ti fi ojú wọn pamọ́ kúrò ní ọjọ́ ìsinmi mi, mó sì dí ẹni àìlọ́wọ̀ láàrín wọn.
Athĩnjĩri-Ngai akuo mahũthagĩra hinya makiuna watho wakwa, na magathaahia indo ciakwa iria nyamũre; matikũũranaga indo iria nyamũre na iria itarĩ nyamũre; marutanaga atĩ gũtirĩ ngũũrani ya indo irĩ thaahu na iria itarĩ thaahu; na mahingaga maitho matikamenyerere Thabatũ ciakwa, nĩguo ngarumagwo gatagatĩ-inĩ kao.
27 Àwọn ọmọ-aládé àárín rẹ̀ dàbí ìkookò ti ń ṣọdẹ, láti tàjẹ̀ sílẹ̀, láti pa ọkàn run, láti jèrè àìṣòótọ́.
Anene akuo arĩa marĩ kuo matariĩ ta njũũi igĩtambuura kĩrĩa inyiitĩte; maitaga thakame na makooraga andũ, nĩguo megwatĩre uumithio ũrĩa ũtagĩrĩire.
28 Àti àwọn wòlíì rẹ́ ti ṣẹ̀tàn sí wọn, wọn ń rì ìran asán, wọn sì ń fọ àfọ̀ṣẹ èké sí wọn, wí pé, ‘Báyìí ní Olúwa Olódùmarè wí,’ nígbà tí ó ṣépè Olúwa kò sọ̀rọ̀.
Anabii akuo mamahakagĩra ciĩko icio coka mwerũ, na njĩra ya kũmoonera cioneki cia maheeni, na ũragũri wa maheeni. Moigaga atĩrĩ, ‘Mwathani Jehova ekuuga ũũ’, o rĩrĩa Jehova atarĩ ũndũ oigĩte.
29 Àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà, tí lo ìwà ìninilára, wọn sì já olè, wọn sì ni àwọn tálákà àti aláìní lára; nítòótọ́, wọn tí ní àlejò lára láìnídìí. Kò sì ṣí ìdájọ́ òdodo.
Andũ a bũrũri ũcio mahũthagĩra ũhahanyi na ũtunyani; mahinyagĩrĩria athĩĩni na abatari, na makanyariira andũ a kũngĩ, makamaagithia kĩhooto.
30 “Èmi si wá ẹnìkan láàrín wọn, tí ìbá tún odi náà mọ́, tí ìbá dúró ní ibi tí ó ya náà níwájú mi fún ilẹ̀ náà, kí èmi má bá à parun: ṣùgbọ́n èmi kò rí ẹnìkan.
“Ndaacaririe mũndũ thĩinĩ wao ũngĩaka rũthingo na arũgame mbere yakwa mwanya-inĩ, agitĩre bũrũri ũcio, nĩguo ndikaũniine o kũũniina, no ndiigana kuona o na ũmwe.
31 Nítorí náà ni mo ṣe da ìbínú mi sí wọn lórí, mo ti fi iná ìbínú mi run wọn, mo si ti fi ọ̀nà wọn gbẹ̀san lórí ara wọn, ní Olúwa Olódùmarè wí.”
Nĩ ũndũ ũcio nĩngamaitĩrĩria mangʼũrĩ makwa, na ndĩmaniine na marakara makwa mahiũ, na ndĩmacookererie maũndũ marĩa mothe mekĩte, ũguo nĩguo Mwathani Jehova ekuuga.”

< Ezekiel 22 >