< Ezekiel 22 >
Hothloilah, BAWIPA e lawk hah kai koe a pha teh,
2 “Ọmọ ènìyàn ǹjẹ́ ìwọ yóò ha ṣe ìdájọ́ rẹ̀? Ǹjẹ́ ìwọ ha ṣe ìdájọ́ ìlú atàjẹ̀sílẹ̀? Tó bá rí bẹ́ẹ̀ dojúkọ wọn pẹ̀lú gbogbo ìwà ìríra wọn.
nang tami capa, thi ka Palawng e khopui hah lawk na ceng hah na maw, Bokheiyah panuet a thonae naw hah panuek sak.
3 Kí ó sì wí pé, ‘Èyí yìí ní ohun tí Olúwa Olódùmarè wí: Ìwọ ìlú ńlá tí ó mú ìparun wá sórí ara rẹ nípa títàjẹ̀sílẹ̀ ní àárín rẹ, tí ó sì ba ara rẹ̀ jẹ́ nípa ṣíṣe àwọn ère.
Ahnimouh koe Bawipa Jehovah ni hettelah a dei. Amae tueng roeroe navah thipalawngnae khopui atueng a pha nahanelah, amahoima kâkhinsak hanelah meikaphawk hah a sak.
4 Ìwọ ti jẹ̀bi nítorí ẹ̀jẹ̀ tí ìwọ ti ta sílẹ̀, àti pé àwọn ère tí ó ṣe tí bà ọ́ jẹ́. Ìwọ tí mú ọjọ́ rẹ súnmọ́ tòsí, ìparí àwọn ọdún rẹ sì ti dé. Nítorí náà èmi yóò fi ọ ṣe ohun ẹ̀gàn lójú àwọn orílẹ̀-èdè àti ohun ẹ̀sín lójú gbogbo ìlú.
Tami hringnae na thei e lahoi yonpen e lah na o teh meikaphawk na sak e dawkvah na kâkhinsak. Namae na hnin na hnai sak teh, na kum apoutnae meimei a pha toe. Hatdawkvah, miphunnaw na pathoenae hoi ram pueng ni dudam e lah na o sak han.
5 Àwọn tí ó wà ní tòsí àti àwọn tí ó jìnnà sí ọ, yóò fi ọ ṣe ẹlẹ́yà, ìwọ ìlú ẹlẹ́gàn, tí ó kún fún làálàá.
Na tengpam e taminaw hoi lamhla e taminaw ni pathoenae hoi pacekpahleknae hoi ka kawi e patetlah na panuikhai han.
6 “‘Wo bí ọ̀kọ̀ọ̀kan nínú àwọn ọmọbìnrin ọba Israẹli tí ó wà nínú yín ti ń lo agbára rẹ̀ láti tàjẹ̀ sílẹ̀.
Khenhaw! Isarel ukkungnaw ni nangmouh thi Palawng hanelah a thaonae rip a hno awh.
7 Nínú rẹ wọn ti hùwà sí baba àti ìyá pẹ̀lú ìfojú tínrín; nínú rẹ wọn ti ni àwọn àlejò lára, wọn sì hùwàkiwà sí aláìní baba àti opó.
Nangmouh thung manu na pa hah a dudam awh teh, nangmae rahak alouke miphun khok hoi a coungroe awh teh, nangmouh dawk e nara hoi lahmai hah banglahai noutna awh hoeh.
8 Ìwọ tí kọ àwọn ohun mímọ́ mi sílẹ̀, ìwọ sì ti lo ọjọ́ ìsinmi mi ní ìlòkulò.
Nang ni kaie thoungnae naw banglahai noutna hoeh e lah na sak toe. Kaie sabbath hninnaw na tapoe toe.
9 Nínú rẹ ni àwọn ayannijẹ ènìyàn pinnu láti tàjẹ̀ sílẹ̀; nínú rẹ ní àwọn tí ó ń jẹun ní orí òkè ojúbọ òrìṣà, wọn sì hùwà ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́.
Namamouh thung e tami thipalawng han na ngai teh, thuengnae moi, tami tangawn ni a ca awh, hno kathout ka sak e ao awh.
10 Nínú rẹ ní àwọn ti kò bu ọlá fún àwọn àkéte baba wọn; nínú rẹ ni àwọn tí o ń bá àwọn obìnrin lò nígbà tí wọ́n ń ṣe àkókò lọ́wọ́, ní àsìkò tí a ka wọn sì aláìmọ́.
Nangmouh thung dawk a na pa e yu hah caicinae na ramuk awh hoeh. Kampheng lahun e napui hai a yonkhai awh toe.
11 Nínú rẹ ọkùnrin kan ti dá ẹ̀ṣẹ̀ ìríra pẹ̀lú aya aládùúgbò rẹ̀, òmíràn bá ìyàwó ọmọ rẹ̀ jẹ́, òmíràn sì bá arábìnrin rẹ̀ lòpọ̀ èyí tí í ṣe ọbàkan rẹ̀.
Nangmouh thung dawk tami tangawn ni amae imri yu koe panuettho e hno a sak awh toe, a langa a kamhnawngkhai awh toe, tangawn ni a tawncanu, a na pa e canu hah a pacekpahlek awh.
12 Nínú rẹ àwọn ènìyàn gba àbẹ̀tẹ́lẹ̀ láti tàjẹ̀ sílẹ̀; ìwọ gba èlé ìlọ́po láti mú aláìṣòótọ́ jèrè láti ara aládùúgbò rẹ nípa ìrẹ́jẹ. Ìwọ sì ti gbàgbé èmi; ni Olúwa Olódùmarè wí.
Nangmouh thung dawk tami theinae han lah tadawnghno hai na la awh, apung na ca teh, tangka na cawi awh, imri e hnopai na lawp awh.
13 “‘Èmi yóò kúkú pàtẹ́wọ́ lórí èrè àìmọ̀ tí ìwọ ti jẹ, àti lórí ẹ̀jẹ̀ tí ìwọ ti ta sílẹ̀ ní àárín yín.
Hatdawkvah, nama ni na pâkhueng e hnopai namamouh thung dawk thi na Palawng e kecu dawk kai ni kut ka tambei sin han.
14 Ọkàn rẹ le gbà á, tàbí ọwọ́ rẹ lè le, ní ọjọ́ tí èmi yóò bá ọ ṣé? Èmi Olúwa ti sọ̀rọ̀, Èmi yóò sì ṣe é.
Kai ni nang lawk na ceng toteh, na lungthin na cak sak thai han na ou. Na kut hai a tha ao thai han na ou. Kai BAWIPA ni ka dei tangcoung e patetlah ka sak han.
15 Èmi yóò tú yin ká ní àárín àwọn orílẹ̀-èdè, èmi yóò fọ́n ọ ká sí àwọn ìlú; èmi yóò sì fi òpin sí àìmọ́ rẹ.
Nang hai ram miphun tangkuem koevah, na kâkayei sak han. Hateiteh, na khinnae hah be kahma sak han.
16 Nígbà tí a ó bà ọ́ jẹ́ lójú àwọn orílẹ̀-èdè, ìwọ yóò mọ̀ pé, Èmi ni Olúwa.’”
Miphunnaw e hmaitung vah mahoima na kâkhinsak. BAWIPA lah ka o tie na panue han ati tet pouh telah ati.
17 Nígbà náà ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá:
BAWIPA e lawk kai koe a pha teh,
18 “Ọmọ ènìyàn, ilé Israẹli ti di ìdàrọ́ sí mi; gbogbo wọn jẹ́ bàbà, idẹ, irin àti òjé ti a fi sínú iná ìléru. Wọn jẹ́ ìdàrọ́ ti fàdákà.
tami capa Isarel imthung hah kai hanelah sumei lah doeh ao. Ahnimanaw teh sôlêi e, tahmanghmai dawk phum e, rahum paling, rahum pangaw, sum hoi ngunei patetlah doeh ao awh.
19 Nítorí náà èyí yìí ni ohun ti Olúwa Olódùmarè wí: ‘Nítorí tí ìwọ ti di ìdàrọ́, èmi yóò kó yín jọ sí Jerusalẹmu.
Hatdawkvah Bawipa Jehovah ni hettelah a dei. Ei rumram lah na o awh dawkvah, khenhaw! Jerusalem kho lungui na pâkhueng awh.
20 Gẹ́gẹ́ bí ènìyàn ṣe ń kó fàdákà, bàbà, irin, òjé àti idẹ jọ sínú iná ìléru láti fi iná yọ́ ọ, bẹ́ẹ̀ ni èmi yóò kó ọ jọ ní ìbínú àti ìrunú mi, èmi yóò sì fi ọ sì àárín ìlú, èmi yóò sì yọ́ ọ. Níbẹ̀ ní ìwọ yóò sì ti yọ́.
Ngun, rahum paling, rahum pangaw, sum, konlawk naw hmai patawi sin teh a tui lah kamyawt hanelah, thawngnae dawk khuk papawp e patetlah kai teh ka lung puenghoi a khuek teh, nangmouh teh kho lungui vah na pâkhueng awh vaiteh, atui lah na kamyawt sak han.
21 Èmi yóò kó yín jọ, èmi o sì fín iná ìbínú mi si yin lára, ẹ o si di yíyọ́ láàrín rẹ̀.
Atangcalah na pâkhueng awh vaiteh, kaie ka lungkhueknae hmai, ka patawi vaiteh, nangmouh teh kho thung atui lah na kamyawt awh han.
22 Bí a ti ń yọ́ fàdákà nínú iná ìléru bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ ní ìwọ yóò ṣe yọ́ nínú rẹ̀, ìwọ yóò sì mọ̀ wí pé, Èmi Olúwa ti tú ìbínú mi sórí rẹ.’”
Ngun thawngnae dawkvah atui lah kamyawt e patetlah nangmanaw teh kho thung vah atui lah na kamyawt awh vaiteh, kai BAWIPA ni nangmae lathueng vah, kaie ka lungkhueknae ka awi toe tie hah na panue awh han telah ati.
23 Lẹ́ẹ̀kan sí i ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá wí pé,
BAWIPA e lawk kai koe a pha teh,
24 “Ọmọ ènìyàn, sọ fún ilẹ̀ náà, ‘Ìwọ ní ilẹ̀ tí kò gbá mọ́, ti kò sì rọ òjò tàbí ìrì ní àkókò ìbínú.’
tami capa ahni koe dei pouh nang teh, lungkhueknae ahni dawk kho ka rak hoeh e, khotui hah ka dawp hoeh e ram lah ao.
25 Ìdìtẹ̀ sì wà láàrín àwọn ọmọ-aládé inú rẹ̀, tó dàbí bíbú kìnnìún tó ń fà ẹran ya, wọ́n ń ba àwọn ènìyàn jẹ́, wọ́n ń kó ìṣúra àti àwọn ohun iyebíye wọ́n sì ń sọ púpọ̀ di opó nínú rẹ̀.
Hote ram dawkvah, profetnaw teh a kâyouk awh toe. Ka huk ni teh moi ka kei e sendek patetlah taminaw a ca awh. Hno kuemnae hoi aphu kaawm e hnopainaw a lawp awh toe. Khothung vah lahmainaw moikapap lah ao sak awh.
26 Àwọn àlùfáà rẹ̀ ti rú òfin mi, wọn si ti sọ ohun mímọ́ mi di àìlọ́wọ̀: wọn kò fi ìyàtọ̀ sáàrín ohun mímọ́ àti àìlọ́wọ̀, bẹ́ẹ̀ ni wọn kò fi ìyàtọ̀ hàn láàrín ohun àìmọ́, àti mímọ́, wọn sì ti fi ojú wọn pamọ́ kúrò ní ọjọ́ ìsinmi mi, mó sì dí ẹni àìlọ́wọ̀ láàrín wọn.
Ahnimae vaihmanaw ni hai kaie kâlawk a ek awh teh, kaie a thoungnae hmuen hai a khinsak awh. Kathounge hoi kathounghoehe hoi kapek awh hoeh. Kathounge hoi kathounghoehe mak kâkalawtsak awh, kaie sabbath hnin hai a kâpahnim sak awh.
27 Àwọn ọmọ-aládé àárín rẹ̀ dàbí ìkookò ti ń ṣọdẹ, láti tàjẹ̀ sílẹ̀, láti pa ọkàn run, láti jèrè àìṣòótọ́.
Kahrawikungnaw ni hai moi ka kei e Asuinaw patetlah ram thung ao awh teh, kamsoumhoehe apung a tawng awh teh, tami hringnae a thei awh.
28 Àti àwọn wòlíì rẹ́ ti ṣẹ̀tàn sí wọn, wọn ń rì ìran asán, wọn sì ń fọ àfọ̀ṣẹ èké sí wọn, wí pé, ‘Báyìí ní Olúwa Olódùmarè wí,’ nígbà tí ó ṣépè Olúwa kò sọ̀rọ̀.
Ahnimae profetnaw ni thungpangaw a hluk awh teh, kaphawk e kamnuenae hah a hmu awh. Laithoe lahoi cungpam a rayu pouh awh. BAWIPA ni banghai a dei hoeh nakunghai, Bawipa Jehovah ni hettelah a dei, telah ouk ati awh.
29 Àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà, tí lo ìwà ìninilára, wọn sì já olè, wọn sì ni àwọn tálákà àti aláìní lára; nítòótọ́, wọn tí ní àlejò lára láìnídìí. Kò sì ṣí ìdájọ́ òdodo.
Khocanaw hai rektapnae tahloi hoi a tuk awh, ka roedengnaw hah pacekpahleknae Jentelnaw hai kahawihoehe lahoi a pacekpahlek awh.
30 “Èmi si wá ẹnìkan láàrín wọn, tí ìbá tún odi náà mọ́, tí ìbá dúró ní ibi tí ó ya náà níwájú mi fún ilẹ̀ náà, kí èmi má bá à parun: ṣùgbọ́n èmi kò rí ẹnìkan.
Ram hah ka raphoe hoeh nahan, rapan ka sak hane hoi ram e a yueng lah kai han e ka kangdout hanelah ahnimouh koe ka tawng, hatei ka hmawt hoeh.
31 Nítorí náà ni mo ṣe da ìbínú mi sí wọn lórí, mo ti fi iná ìbínú mi run wọn, mo si ti fi ọ̀nà wọn gbẹ̀san lórí ara wọn, ní Olúwa Olódùmarè wí.”
Hatdawkvah, ka lungkhueknae teh ahnimae lathueng ka rabawk teh, ka lungkhueknae hmai hoi ka sawi. A hringnae hoi kamcu lah ahnimae lathueng ka pha sak e doeh telah Bawipa Jehovah ni a dei, tet pouh telah ati.