< Ezekiel 21 >

1 Ọ̀rọ̀ Olúwa tọ mi wá:
Kiugo kĩa Jehova nĩkĩanginyĩrĩire, ngĩĩrwo atĩrĩ:
2 “Ọmọ ènìyàn, kọ ojú rẹ sí ìhà Jerusalẹmu, kí o sì wàásù lòdì sí ibi mímọ́. Sọ àsọtẹ́lẹ̀ sí ilẹ̀ Israẹli.
“Mũrũ wa mũndũ, roria ũthiũ waku Jerusalemu, na ũhunjie ũhoro wa gũũkĩrĩrwo kwa handũ-harĩa-haamũre. Ratha ũhoro wa gũũkĩrĩrwo kwa bũrũri ũcio wa Isiraeli,
3 Kí ó sì sọ fún un pe, ‘Èyí yìí ni Olúwa wí, Èmi lòdì sí ọ. Èmi yóò fa idà mi yọ kúrò nínú àkọ̀ rẹ̀, Èmi yóò sì ké olódodo àti ènìyàn búburú kúrò ni àárín yín.
ũwĩre atĩrĩ, ‘Jehova ekuuga ũũ: Nĩngũgũũkĩrĩra. Nĩngũcomora rũhiũ rwakwa rwa njora kuuma njora-inĩ, na ngwehererie andũ arĩa athingu na arĩa aaganu.
4 Nítorí pé, èmi yóò ké olódodo àti olùṣe búburú kúrò, idà mi yóò jáde láti inú àkọ̀ rẹ̀ lòdì sí gbogbo ènìyàn láti gúúsù títí dé àríwá.
Tondũ nĩngũkwehereria andũ arĩa athingu na arĩa aaganu-rĩ, rũhiũ rwakwa rwa njora nĩrũgacomorerwo mũndũ o wothe kuuma mwena wa gũthini nginya mwena wa gathigathini.
5 Nígbà náà gbogbo ènìyàn yóò mọ̀ pé, Èmi Olúwa ti yọ idà mi kúrò nínú àkọ̀ rẹ̀; kì yóò sì padà sínú rẹ̀ mọ́.’
Hĩndĩ ĩyo, andũ othe nĩmakamenya atĩ niĩ Jehova nĩ niĩ njomorete rũhiũ rwakwa rwa njora kuuma njora-inĩ; rũtigacookio rĩngĩ njora-inĩ.’
6 “Nítorí náà, mí ìmí ẹ̀dùn ìwọ ọmọ ènìyàn! Mí ìmí ẹ̀dùn pẹ̀lú ọkàn ìbànújẹ́ àti ẹ̀dùn ọkàn kíkorò ní iwájú wọn.
“Nĩ ũndũ ũcio, wee mũrũ wa mũndũ caaya! Caaĩra mbere yao, ũrĩ mũthĩĩnĩku ngoro na ũrĩ na kĩeha kĩnene.
7 Bí wọ́n bá sì bi ọ́, wí pé, ‘Kí ni ó dé tí ìwọ fi ń mí ìmí ẹ̀dùn?’ Ìwọ yóò wí pé, ‘Nítorí ìròyìn tí ó ń bẹ. Gbogbo ọkàn ni yóò yọ́, gbogbo ọwọ́ ni yóò sì di aláìlera; gbogbo ọkàn ní yóò dákú, gbogbo eékún ni yóò sì di aláìlera bí omi?’ Ó ń bọ̀! Yóò sì wa sí ìmúṣẹ dandan, ni Olúwa Olódùmarè wí.”
Na rĩrĩa magaakũũria atĩrĩ, ‘Ũracaaya nĩkĩ?’ ũkameera atĩrĩ, ‘Nĩ ũndũ wa ũhoro ũrĩa ũroka. Ngoro o yothe nĩĩkaringĩka, na guoko o guothe kwage hinya; roho o wothe nĩũkaringĩka na iru o rĩothe nĩrĩkaregera o ta ũrĩa maaĩ mereeraga.’ Ũhoro ũcio nĩũrooka! Ti-itherũ, ũhoro ũcio nĩũgekĩka, ũguo nĩguo Mwathani Jehova ekuuga.”
8 Ọ̀rọ̀ Olúwa si tún tọ̀ mí wá pé:
Nakĩo kiugo kĩa Jehova gĩkĩnginyĩrĩra, ngĩĩrwo atĩrĩ:
9 “Ọmọ ènìyàn, sọtẹ́lẹ̀ wí pé, èyí yìí ní Olúwa wí pé, “‘Idà kan, idà kan, tí a pọ́n, tí a sì dán pẹ̀lú,
“Mũrũ wa mũndũ, ratha ũhoro, uuge atĩrĩ, ‘Mwathani ekuuga ũũ: “‘Harĩ rũhiũ rwa njora, harĩ rũhiũ rwa njora, rũnooretwo rũkohĩga, na rũgathũũo rũkahenia,
10 a pọ́n láti pa ènìyàn púpọ̀, a dán an láti máa kọ mọ̀nà! “‘Àwa o ha máa ṣe àríyá ọ̀gọ ọmọ mi? Idà gán gbogbo irú igi bẹ́ẹ̀.
rũnooretwo rũrĩ rwa kũũragana, na rũgathũũo nĩguo rũhenagie ta rũheni! “‘Anga nĩtũgagĩkenera mũthĩgi wa ũthamaki wa mũrũ wakwa Juda? Rũhiũ rũu rwa njora nĩrũiraga mũthĩgi o wothe ta ũcio.
11 “‘Idà ní a yàn láti pọ́n, kí ó lè ṣe é gbámú; a pọ́n ọn, a sì dán an, ó ṣetán fún ọwọ́ àwọn apani.
“‘Rũhiũ rũu rwa njora rũthuurĩtwo nĩguo rũthũũo, nĩguo rũnyiitagwo na guoko; nĩrũnoore na rũgathũũo, na nĩrũhaarĩirio nĩguo rũneanwo guoko-inĩ kwa mũũragani.
12 Sọkún síta, kí ó sì pohùnréré ẹ̀kún, ọmọ ènìyàn, nítorí yóò wá sórí àwọn ènìyàn mi; yóò wá sórí gbogbo ọmọ-aládé Israẹli ìbẹ̀rù ńlá yóò wá sórí àwọn ènìyàn mi nítorí idà náà; nítorí náà lu oókan àyà rẹ.
Rĩra na ũgirĩke, wee mũrũ wa mũndũ, nĩgũkorwo nĩrũũkĩrĩire andũ akwa, o na rũgookĩrĩra athamaki othe a Isiraeli. Nĩmaneanĩtwo rũhiũ-inĩ rwa njora marĩ hamwe na andũ akwa. Nĩ ũndũ ũcio wĩhũũre gĩthũri.
13 “‘Ìdánwò yóò dé dandan. Tí ọ̀pá aládé Juda èyí tí idà kẹ́gàn, kò bá tẹ̀síwájú mọ́ ń kọ́? Ni Olúwa Olódùmarè wí.’
“‘Ti-itherũ kũgeranio nĩgũgooka. Gũgaagĩikara atĩa angĩkorwo mũthĩgi ũcio wa ũthamaki wa Juda, ũrĩa ũiragwo nĩ rũhiũ rũu rwa njora ndũgathiĩ na mbere? Ũguo nĩguo Mwathani Jehova ekuuga.’
14 “Nítorí náà, ọmọ ènìyàn, sọtẹ́lẹ̀ kí ó sì fi ọwọ́ lu ọwọ́. Jẹ́ kí idà lu ara wọn lẹ́ẹ̀méjì, kódà ní ẹ̀ẹ̀mẹta. Ó jẹ́ idà fún ìpànìyàn idà fún ìpànìyàn lọ́pọ̀lọ́pọ̀, tí yóò sé wọn mọ́ níhìn-ín àti lọ́hùnnún.
“Nĩ ũndũ ũcio, wee mũrũ wa mũndũ-rĩ, ratha ũhoro, na ũhũũre hĩ. Naruo rũhiũ rũu rwa njora ũreke rũringe maita meerĩ, o na nĩrũringe maita matatũ. Nĩ rũhiũ rwa njora rwa kũũragana, nĩ rũhiũ rwa njora rwa kũũragana kũnene, rũramahatĩrĩria na mĩena yothe.
15 Kí ọkàn kí ó lè yọ́ kí àwọn tí ó ṣubú le pọ̀, mo ti gbé idà sí gbogbo bodè fún ìparun. Háà! A mú kí ó kọ bí ìmọ̀nàmọ́ná, a gbá a mú fún ìparun.
Nĩgeetha ngoro iringĩke, nao arĩa magwĩte maingĩhe, nĩnjigĩte rũhiũ rwa njora rwa kũũragana ihingo-inĩ ciao ciothe. Hĩ! Rũthondeketwo rũhenagie ta rũheni, rũnyiitĩtwo nĩguo rũũragane.
16 Ìwọ idà, jà sí ọ̀tún kí o sì jà sí òsì lọ ibikíbi tí ẹnu rẹ bá dojúkọ.
Wee rũhiũ rwa njora, temanga mwena wa ũrĩo, na ningĩ ũtemange mwena wa ũmotho, na ũtemange kũrĩa guothe ũũgĩ waku ũngĩerekerio.
17 Èmi gan an yóò pàtẹ́wọ́ ìbínú mi yóò sì rẹlẹ̀. Èmi Olúwa ti sọ̀rọ̀.”
Niĩ o na niĩ-rĩ, nĩngahũũra hĩ, namo mangʼũrĩ makwa mahũahũe. Nĩ niĩ Jehova njugĩte ũguo.”
18 Ọ̀rọ̀ Olúwa tọ mi wá:
Kiugo kĩa Jehova nĩkĩanginyĩrĩire, ngĩĩrwo atĩrĩ,
19 “Ọmọ ènìyàn la ọ̀nà méjì fún idà ọba Babeli láti gbà, kí méjèèjì bẹ̀rẹ̀ láti ìlú kan náà. Ṣe àmì sí ìkóríta ọ̀nà tí ó lọ sí ìlú náà.
“Mũrũ wa mũndũ, tema njĩra igĩrĩ cia kũgererwo nĩ rũhiũ rwa njora rwa mũthamaki wa Babuloni, cierĩ ciumĩte bũrũri o ũmwe. Haanda rũũri harĩa njĩra yahũkĩire ĩrorete itũũra inene.
20 La ọ̀nà kan fún idà láti wá kọlu Rabba ti àwọn ará Ammoni kí òmíràn kọlu Juda, kí ó sì kọlu Jerusalẹmu ìlú olódi.
Tema njĩra ĩmwe ĩrĩa rũhiũ rũu rwa njora rũkaagerera rũgĩthiĩ gũũkĩrĩra Raba kũu kwa Aamoni, na ĩngĩ ya kũgerwo nĩruo rũgĩthiĩ gũũkĩrĩra Juda hamwe na Jerusalemu kũu kũirigĩre.
21 Nítorí ọba Babeli yóò dúró ni ìyànà ní ojú ọ̀nà, ní ìkóríta, láti máa lo àfọ̀ṣẹ. Yóò fi ọfà di ìbò, yóò béèrè lọ́wọ́ àwọn òrìṣà rẹ̀, òun yóò ṣe àyẹ̀wò ẹ̀dọ̀.
Nĩgũkorwo mũthamaki wa Babuloni akaarũgama maahũkanĩro ma njĩra ĩyo, harĩa njĩra icio cierĩ ciahũkanĩire, nĩguo aragũrie: Akaahũthĩra mĩguĩ agĩcuuka mĩtĩ, na ahooe kĩrĩra harĩ mĩhianano yake, na arorithie ini.
22 Nínú ọwọ́ ọ̀tún rẹ ni ìbò Jerusalẹmu yóò ti wá, ní ibi tí yóò ti gbé afárá kalẹ̀, láti pàṣẹ fún àwọn apànìyàn, láti mú ki wọn hó ìhó ogun láti gbé òòlù dí ẹnu-ọ̀nà ibodè, láti mọ odi, àti láti kọ́ ilé ìṣọ́.
Guoko-inĩ gwake kwa ũrĩo, mũtĩ nĩũkagwĩra Jerusalemu, kũrĩa akaigithia mĩgogo ya kũmomora rũirigo, na arute watho wa kũũraganwo, na kuugĩrĩrio mbugĩrĩrio ya mbaara, nayo mĩgogo ya kũmomora ĩigwo ĩhingĩrĩirie ihingo, na aigithie kĩhumbu, na gwakwo ngathĩ ndaaya cia mbaara cia gũteithia gũtharĩkĩra itũũra.
23 Àfọ̀ṣẹ náà yóò dàbí àmì èké sí àwọn tí ó ti búra ìtẹríba fún un, ṣùgbọ́n òun yóò ran wọn létí ẹbí wọn yóò sì mú wọn lọ sí ìgbèkùn.
Ũndũ ũcio nĩũkoneka ta ũtarĩ wa ma kũrĩ andũ arĩa mehĩtĩte atĩ nĩmarĩmwathĩkagĩra, nowe nĩakamaririkania mahĩtia mao, acooke amanyiite mĩgwate.
24 “Nítorí náà èyí ní ohun tí Olúwa Olódùmarè wí: ‘Nítorí ti ẹ̀yin ti mú ẹ̀bi yín wá sí ìrántí nípa ìṣọ̀tẹ̀ ní gbangba, ní ṣíṣe àfihàn àwọn ẹ̀ṣẹ̀ rẹ nínú gbogbo ohun tí ó ṣe, nítorí tí ẹ̀yin ti ṣe èyí, a yóò mú yín ní ìgbèkùn.
“Nĩ ũndũ ũcio, Mwathani Jehova ekuuga ũũ: ‘Tondũ inyuĩ andũ aya nĩmũtũmĩte mahĩtia manyu maririkanwo nĩ ũndũ wa ũrĩa ũremi wanyu wonekanĩte, ũkaguũria mehia manyu makoneka maũndũ-inĩ mothe marĩa mwĩkaga; nĩ ũndũ nĩmwĩkĩte ũguo-rĩ, nĩmũkanyiitwo mĩgwate.
25 “‘Ìwọ aláìmọ́ àti ẹni búburú ọmọ-aládé Israẹli, ẹni ti ọjọ́ rẹ̀ ti dé, ẹni tí àsìkò ìjìyà rẹ̀ ti dé góńgó,
“‘Wee mũthamaki ũyũ wa Isiraeli, o wee mwaganu na ndũrĩka, mũthenya waku nĩmũkinyu, na ihinda rĩaku rĩa kũherithio rĩgakinya mũthia.
26 èyí yìí ní ohun tí Olúwa Olódùmarè wí, tú ìwérí kúrò kí o sì gbé adé kúrò. Kò ní rí bí ti tẹ́lẹ̀, ẹni ìgbéga ni a yóò sì rẹ̀ sílẹ̀.
Mwathani Jehova ekuuga ũũ: Ruta kĩremba, na weherie tanji. Maũndũ matigacooka gũikara ta ũrĩa maatariĩ: Arĩa anini nĩmagatũũgĩrio, nao arĩa atũũgĩrie nĩmakanyiihio.
27 Ìparun! Ìparun! Èmi yóò ṣé e ni ìparun! Kì yóò padà bọ̀ sípò bí kò ṣe pé tí ó bá wá sí ọ̀dọ̀ ẹni tí ó ní ẹ̀tọ́ láti ni in; òun ni èmi yóò fi fún.’
Nĩ mwanangĩko! Ĩĩ nĩ mwanangĩko! Nĩngarĩanangithia! Rĩtigacookererio nginya hĩndĩ ĩrĩa ũcio mwene rĩo agooka; ũcio nĩwe ngaarĩneana kũrĩ we.’
28 “Àti ìwọ, ọmọ ènìyàn sọtẹ́lẹ̀ kí ó sì wí pé, ‘Èyí yìí ní ohun tí Olúwa Olódùmarè wí nípa àwọn ará Ammoni àti àbùkù wọn: “‘Idà kan idà kan tí á fa yọ fún ìpànìyàn tí a dán láti fi ènìyàn ṣòfò àti láti kọ bí ìmọ̀nàmọ́ná!
“Nawe mũrũ wa mũndũ, ratha ũhoro, uuge atĩrĩ, ‘Ũũ nĩguo Mwathani Jehova ekuuga ũhoro-inĩ ũkoniĩ Aamoni na irumi ciao: “‘Harĩ rũhiũ rwa njora, harĩ rũhiũ rwa njora, rũcomoretwo rũũragane, na rũthũũĩtwo rũrĩ rwa kũniinana, na rwakũhenia ta rũheni!
29 Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé a rí èké nípa yín àti àfọ̀ṣẹ èké nípa yín a yóò gbé e lé àwọn ọrùn ènìyàn búburú ti a ó pa, àwọn tí ọjọ́ wọn ti dé, àwọn tí ọjọ́ ìjìyà wọn ti dé góńgó.
O na gũkorwo nĩ kũrĩ cioneki cia maheeni igũkoniĩ, na ũragũri wa maheeni ũgũkoniĩ-rĩ, nĩrũkaigĩrĩrwo ngingo cia arĩa aaganu, arĩa marĩ a kũũragwo, arĩa mũthenya wao ũkinyĩte, o acio ihinda rĩao rĩa kũherithio rĩkinyĩte mũthia.
30 “‘Dá idà padà sínú àkọ̀ rẹ̀. Níbi tí a gbé ṣẹ̀dá yín, ní ibi tí ẹ̀yin ti ṣẹ̀ wá.
Cookia rũhiũ njora thĩinĩ. Ũrĩ kũu wee wombĩirwo, o kũu bũrũri-inĩ ũcio wa maithe manyu, nĩkuo ngaagũtuĩra ciira.
31 Níbẹ̀ ni èmi yóò ti ṣe ìdájọ́ yín, èmi o sì fi èémí ìbínú gbígbóná mi bá yín jà.
Nĩngagũitĩrĩria mangʼũrĩ makwa, na ngũũkĩrĩre na mĩhũmũ ya marakara makwa mahiũ; nĩngakũneana moko-inĩ ma andũ matarĩ tha, andũ ohĩgĩrĩru na kũniinana.
32 Ẹ̀yin yóò jẹ́ èpò fún iná náà, a yóò ta ẹ̀jẹ̀ yin sórí ilẹ̀ yín, a kì yóò rántí yín mọ́; nítorí Èmi Olúwa ní ó ti wí bẹ́ẹ̀.’”
Wee ũgaatuĩka ngũ cia gwakia mwaki ũcio, nayo thakame yaku ĩgaitĩrwo kũu bũrũri waku, ndũgacooka kũririkanwo; nĩgũkorwo niĩ Jehova nĩ niĩ njarĩtie.’”

< Ezekiel 21 >