< Ezekiel 21 >

1 Ọ̀rọ̀ Olúwa tọ mi wá:
Angraeng ih lok kai khaeah angzoh,
2 “Ọmọ ènìyàn, kọ ojú rẹ sí ìhà Jerusalẹmu, kí o sì wàásù lòdì sí ibi mímọ́. Sọ àsọtẹ́lẹ̀ sí ilẹ̀ Israẹli.
kami capa, Jerusalem bangah anghaeh loe hmuenciim khaeah misa haih lok to thui ah, Israel prae hoi misa angcoenghaih lok to tapong ah;
3 Kí ó sì sọ fún un pe, ‘Èyí yìí ni Olúwa wí, Èmi lòdì sí ọ. Èmi yóò fa idà mi yọ kúrò nínú àkọ̀ rẹ̀, Èmi yóò sì ké olódodo àti ènìyàn búburú kúrò ni àárín yín.
Israel prae khaeah Angraeng Sithaw mah, Khenah, misa ah kang suek han, tabu thung hoi sumsen to ka phongh moe, katoeng doeh, toeng ai doeh, nihcae to ka tamit boih han boeh.
4 Nítorí pé, èmi yóò ké olódodo àti olùṣe búburú kúrò, idà mi yóò jáde láti inú àkọ̀ rẹ̀ lòdì sí gbogbo ènìyàn láti gúúsù títí dé àríwá.
Katoeng maw, katoeng ai maw, ka tamit boih han oh boeh pongah, aloih bang hoi aluek bang ih kaminawk boih misatuk hanah, ka sumsen loe angmah ih tabu thung hoi tacawt tih boeh:
5 Nígbà náà gbogbo ènìyàn yóò mọ̀ pé, Èmi Olúwa ti yọ idà mi kúrò nínú àkọ̀ rẹ̀; kì yóò sì padà sínú rẹ̀ mọ́.’
to naah Kai, Angraeng mah angmah ih tabu thung hoiah sumsen ka phong boeh, tito kami boih mah panoek o tih; to sumsen loe angmah ih tabu thungah pacaeng let mak ai boeh, tiah thuih, tiah thui paeh.
6 “Nítorí náà, mí ìmí ẹ̀dùn ìwọ ọmọ ènìyàn! Mí ìmí ẹ̀dùn pẹ̀lú ọkàn ìbànújẹ́ àti ẹ̀dùn ọkàn kíkorò ní iwájú wọn.
To pongah kami capa, aham ah! Kaeng angkhaeh moe, palung tapok han khoek to nihcae hmaa ah aham ah.
7 Bí wọ́n bá sì bi ọ́, wí pé, ‘Kí ni ó dé tí ìwọ fi ń mí ìmí ẹ̀dùn?’ Ìwọ yóò wí pé, ‘Nítorí ìròyìn tí ó ń bẹ. Gbogbo ọkàn ni yóò yọ́, gbogbo ọwọ́ ni yóò sì di aláìlera; gbogbo ọkàn ní yóò dákú, gbogbo eékún ni yóò sì di aláìlera bí omi?’ Ó ń bọ̀! Yóò sì wa sí ìmúṣẹ dandan, ni Olúwa Olódùmarè wí.”
Nihcae mah tipongah na ham loe? tiah na dueng o nahaeloe, Tamthang angzoh pongah ni ka ham; tamthang angzo naah loe, palungthin boih tui baktiah amzawt ueloe, bannawk boih thazai sut tih, pakhranawk boih thazok o ueloe, khokkhunawk boih tui baktiah naem o tih boeh, tiah thui paeh; khenah, angzo tih boeh, to hmuen loe om tangtang tih, tiah Angraeng Sithaw mah thuih.
8 Ọ̀rọ̀ Olúwa si tún tọ̀ mí wá pé:
Angraeng ih lok kai khaeah angzoh,
9 “Ọmọ ènìyàn, sọtẹ́lẹ̀ wí pé, èyí yìí ní Olúwa wí pé, “‘Idà kan, idà kan, tí a pọ́n, tí a sì dán pẹ̀lú,
kami capa, Angraeng mah hae tiah thuih, tiah taphong han ih lok loe, Sumsen maeto, sumsen maeto loe tak het moe, hmawt het boeh:
10 a pọ́n láti pa ènìyàn púpọ̀, a dán an láti máa kọ mọ̀nà! “‘Àwa o ha máa ṣe àríyá ọ̀gọ ọmọ mi? Idà gán gbogbo irú igi bẹ́ẹ̀.
sumsen loe kami hum hanah tak het boeh, ni aengh baktiah angpha hanah hmawt suidik boeh; aicae loe ka capa ih cunghet pongah anghoe han oh maw? Thing rumram hoi sak ih cunghet loe sumsen mah patoek.
11 “‘Idà ní a yàn láti pọ́n, kí ó lè ṣe é gbámú; a pọ́n ọn, a sì dán an, ó ṣetán fún ọwọ́ àwọn apani.
Sumsen loe hmawt suidik moe, patoh han ih ni a paek; kami hum thaih khaeah paek hanah, to sumsen loe tak het boeh moe, hmawt suidik boeh.
12 Sọkún síta, kí ó sì pohùnréré ẹ̀kún, ọmọ ènìyàn, nítorí yóò wá sórí àwọn ènìyàn mi; yóò wá sórí gbogbo ọmọ-aládé Israẹli ìbẹ̀rù ńlá yóò wá sórí àwọn ènìyàn mi nítorí idà náà; nítorí náà lu oókan àyà rẹ.
Kami capa, qah ah loe hang ah, to hmuen loe kai ih kaminawk nuiah pha ueloe, Israel angraengnawk nuiah om tih; to baktih zitthok hmuennawk hoi sumsen loe kai ih kaminawk nuiah krah tih, to pongah na phaih to atum ah.
13 “‘Ìdánwò yóò dé dandan. Tí ọ̀pá aládé Juda èyí tí idà kẹ́gàn, kò bá tẹ̀síwájú mọ́ ń kọ́? Ni Olúwa Olódùmarè wí.’
To hmuen loe kaimah ih kaminawk tanoekhaih ah oh, sumsen mah cunghet to patoek nahaeloe kawbangmaw pakaa thai tih? Cunghet loe om mak ai boeh, tiah Angraeng Sithaw mah thuih.
14 “Nítorí náà, ọmọ ènìyàn, sọtẹ́lẹ̀ kí ó sì fi ọwọ́ lu ọwọ́. Jẹ́ kí idà lu ara wọn lẹ́ẹ̀méjì, kódà ní ẹ̀ẹ̀mẹta. Ó jẹ́ idà fún ìpànìyàn idà fún ìpànìyàn lọ́pọ̀lọ́pọ̀, tí yóò sé wọn mọ́ níhìn-ín àti lọ́hùnnún.
To pongah kami capa, lok to taphong ah loe, ban tabaeng ah, vai hnetto, vai thumto sumsen alaekhaih to om tih, to sumsen loe kami humhaih sumsen, kami pop parai humhaih sumsen kalen ah oh moe, nihcae ahnuk ahma humhaih sumsen ah oh.
15 Kí ọkàn kí ó lè yọ́ kí àwọn tí ó ṣubú le pọ̀, mo ti gbé idà sí gbogbo bodè fún ìparun. Háà! A mú kí ó kọ bí ìmọ̀nàmọ́ná, a gbá a mú fún ìparun.
Nihcae palung boeng o moe, kadueh kami pop aep hanah, nihcae ih khongkhanawk boih ah sumsen to ka suek boeh; Aw! Sumsen loe ni aengh baktiah ampha moe, kami hum hanah hmawt suidik boeh.
16 Ìwọ idà, jà sí ọ̀tún kí o sì jà sí òsì lọ ibikíbi tí ẹnu rẹ bá dojúkọ.
Aw sumsen caeh ah loe, banqoi bantang alaek ah, sumsen haa angqoihaih ahnuk ahma bang boih ah takroek ah.
17 Èmi gan an yóò pàtẹ́wọ́ ìbínú mi yóò sì rẹlẹ̀. Èmi Olúwa ti sọ̀rọ̀.”
Kai doeh ban tabaeng moe, palungphuihaih ka dipsak han boeh, tiah Kai, Angraeng mah thuih boeh.
18 Ọ̀rọ̀ Olúwa tọ mi wá:
Angraeng ih lok kai khaeah angzoh,
19 “Ọmọ ènìyàn la ọ̀nà méjì fún idà ọba Babeli láti gbà, kí méjèèjì bẹ̀rẹ̀ láti ìlú kan náà. Ṣe àmì sí ìkóríta ọ̀nà tí ó lọ sí ìlú náà.
kami capa, Babylon siangpahrang sumsen hoi angzohhaih loklam hnetto angmathaih to sah ah; to loklam loe kanghmong prae maeto thung hoiah tacawt tih; toe vangpui bang caehhaih lamphi ah, angmathaih to sah ah.
20 La ọ̀nà kan fún idà láti wá kọlu Rabba ti àwọn ará Ammoni kí òmíràn kọlu Juda, kí ó sì kọlu Jerusalẹmu ìlú olódi.
Loklam hnetto ampraekhaih ahmuen ah angmathaih kamnoek ah sah ah: loklam maeto loe Ammon prae vangpui, Rabah ah caehhaih loklam ah oh moe, kalah loklam maeto bae loe Judah prae, misa buephaih kacakah sak ih Jerusalem caehhaih loklam ah oh.
21 Nítorí ọba Babeli yóò dúró ni ìyànà ní ojú ọ̀nà, ní ìkóríta, láti máa lo àfọ̀ṣẹ. Yóò fi ọfà di ìbò, yóò béèrè lọ́wọ́ àwọn òrìṣà rẹ̀, òun yóò ṣe àyẹ̀wò ẹ̀dọ̀.
Babylon siangpahrang loe loklam hnetto ampraekhaih lamphi phak naah, to ah angdoet; palaa hoiah taham kasae kahoih to a khet moe, krangnawk khaeah lok a dueng, angbawnhaih moi pathin to a khet.
22 Nínú ọwọ́ ọ̀tún rẹ ni ìbò Jerusalẹmu yóò ti wá, ní ibi tí yóò ti gbé afárá kalẹ̀, láti pàṣẹ fún àwọn apànìyàn, láti mú ki wọn hó ìhó ogun láti gbé òòlù dí ẹnu-ọ̀nà ibodè, láti mọ odi, àti láti kọ́ ilé ìṣọ́.
Misa buephaih im to a sak, misa buephaih to sak moe, misa qumqaihaih long khaw to takaeh hanah, a bantang ban hoiah Jerusalem hanah taham khethaih phoisa to a vah.
23 Àfọ̀ṣẹ náà yóò dàbí àmì èké sí àwọn tí ó ti búra ìtẹríba fún un, ṣùgbọ́n òun yóò ran wọn létí ẹbí wọn yóò sì mú wọn lọ sí ìgbèkùn.
Toe anih khaeah lokkamhaih sah kaminawk loe taham khethaih to tidoeh avang ai hmuen ah poek o tih; toe siangpahrang mah loe to kaminawk to naeh thai hanah nihcae sakpazaehaih to pakrong tih.
24 “Nítorí náà èyí ní ohun tí Olúwa Olódùmarè wí: ‘Nítorí ti ẹ̀yin ti mú ẹ̀bi yín wá sí ìrántí nípa ìṣọ̀tẹ̀ ní gbangba, ní ṣíṣe àfihàn àwọn ẹ̀ṣẹ̀ rẹ nínú gbogbo ohun tí ó ṣe, nítorí tí ẹ̀yin ti ṣe èyí, a yóò mú yín ní ìgbèkùn.
To pongah Angraeng Sithaw mah hae tiah thuih: na sakpazae o ih hmuennawk to panoek hanah na sak o, to pongah na sakpazae o ih hmuennawk to na panoek o boeh; to tiah na sak o ih hmuennawk hoi na zae o ih hmuennawk loe amtueng boih boeh pongah, siangpahrang ban ah nam timh o tih, tiah ka thuih, tiah thuih pae han ang naa.
25 “‘Ìwọ aláìmọ́ àti ẹni búburú ọmọ-aládé Israẹli, ẹni ti ọjọ́ rẹ̀ ti dé, ẹni tí àsìkò ìjìyà rẹ̀ ti dé góńgó,
Aw nang, panuet thok Israel siangpahrang, nang ih ani loe phak boeh, zaehaih pongah boenghaih to phak boeh.
26 èyí yìí ní ohun tí Olúwa Olódùmarè wí, tú ìwérí kúrò kí o sì gbé adé kúrò. Kò ní rí bí ti tẹ́lẹ̀, ẹni ìgbéga ni a yóò sì rẹ̀ sílẹ̀.
Lumuek to khring ah loe, sui lumuek to angkhring ah; hae hmuen loe amkhrai boih boeh, atlim ah kaom kami to tapom tahang ueloe, tapom tahang ih kami to atlim ah pakhrak tathukhaih om tih, tiah Angraeng Sithaw mah thuih.
27 Ìparun! Ìparun! Èmi yóò ṣé e ni ìparun! Kì yóò padà bọ̀ sípò bí kò ṣe pé tí ó bá wá sí ọ̀dọ̀ ẹni tí ó ní ẹ̀tọ́ láti ni in; òun ni èmi yóò fi fún.’
Tawnkung angzo ai karoek to kam rosak han, kam rosak han! Tawnkung angzoh naah, Anih khaeah ka paek han, tiah a thuih.
28 “Àti ìwọ, ọmọ ènìyàn sọtẹ́lẹ̀ kí ó sì wí pé, ‘Èyí yìí ní ohun tí Olúwa Olódùmarè wí nípa àwọn ará Ammoni àti àbùkù wọn: “‘Idà kan idà kan tí á fa yọ fún ìpànìyàn tí a dán láti fi ènìyàn ṣòfò àti láti kọ bí ìmọ̀nàmọ́ná!
Nang, kami capa, Ammon kaminawk hoi nihcae sethaih kawng pongah Angraeng Sithaw mah, Sumsen, sumsen to aphong boeh; Kami takroek hanah hmawt het boeh moe, kami hum hanah ni aengh baktiah kampha ah hmawt suidik boeh:
29 Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé a rí èké nípa yín àti àfọ̀ṣẹ èké nípa yín a yóò gbé e lé àwọn ọrùn ènìyàn búburú ti a ó pa, àwọn tí ọjọ́ wọn ti dé, àwọn tí ọjọ́ ìjìyà wọn ti dé góńgó.
nangcae Ammon kaminawk loe tidoeh avang ai hmuen to na khet o moe, nangcae khaeah thuih ih lok amlaihaih to na tang o. To pongah hum han kaom kasae kami ih tahnong ah sumsen to koeng tih boeh, anih humhaih atue loe phak boeh, a zae o haih pongah nihcae boenghaih atue to phak boeh.
30 “‘Dá idà padà sínú àkọ̀ rẹ̀. Níbi tí a gbé ṣẹ̀dá yín, ní ibi tí ẹ̀yin ti ṣẹ̀ wá.
Sumsen to tabu thungah ka pacaeng let han maw? Nang kang sakhaih ahmuen, na tapenhaih ahmuen ah, lok kang caek han, tiah thuih, tiah thui paeh, tiah ang naa.
31 Níbẹ̀ ni èmi yóò ti ṣe ìdájọ́ yín, èmi o sì fi èémí ìbínú gbígbóná mi bá yín jà.
Na nuiah palung ka phuihaih ka kraih moe, palung ka phuihaih hmai hoiah kang uengh thuih pacoengah, kami hum thaih, tahmenhaih tawn ai kaminawk ban ah kang paek han.
32 Ẹ̀yin yóò jẹ́ èpò fún iná náà, a yóò ta ẹ̀jẹ̀ yin sórí ilẹ̀ yín, a kì yóò rántí yín mọ́; nítorí Èmi Olúwa ní ó ti wí bẹ́ẹ̀.’”
Nang loe hmaitik koi thing ah na om ueloe, prae thungah na thii to long tih; mi mah doeh nang to panoek mak ai boeh, tiah Kai, Angraeng mah thuih boeh, tiah ang naa.

< Ezekiel 21 >