< Ezekiel 21 >
Hina Gode da nama amane sia: i,
2 “Ọmọ ènìyàn, kọ ojú rẹ sí ìhà Jerusalẹmu, kí o sì wàásù lòdì sí ibi mímọ́. Sọ àsọtẹ́lẹ̀ sí ilẹ̀ Israẹli.
“Dunu egefe! Di Yelusaleme fi ilima mimogoa fofada: ma! Sogebi amoga dunu ilia ogogosu ‘gode’ ilima nodone sia: ne gadosa, amoma mimogoa fofada: ma. Isala: ili sogega sisane amane sia: ma,
3 Kí ó sì sọ fún un pe, ‘Èyí yìí ni Olúwa wí, Èmi lòdì sí ọ. Èmi yóò fa idà mi yọ kúrò nínú àkọ̀ rẹ̀, Èmi yóò sì ké olódodo àti ènìyàn búburú kúrò ni àárín yín.
‘Na, Hina Gode, da dilima amane sia: sa, Na da dilima ha lai dunu esala. Na da Na gegesu gobihei duga: le gadole, dili huluane, noga: i amola wadela: i defele medole legemu.
4 Nítorí pé, èmi yóò ké olódodo àti olùṣe búburú kúrò, idà mi yóò jáde láti inú àkọ̀ rẹ̀ lòdì sí gbogbo ènìyàn láti gúúsù títí dé àríwá.
Na da dunu huluanedafa, ga (north) asili ga (south) esalebe, ilima Na gegesu gobiheiga gegemu.
5 Nígbà náà gbogbo ènìyàn yóò mọ̀ pé, Èmi Olúwa ti yọ idà mi kúrò nínú àkọ̀ rẹ̀; kì yóò sì padà sínú rẹ̀ mọ́.’
Dunu huluane da Na, Hina Gode, Na da Na gegesu gobihei amo duga: le gadole, bu hame salimu, amo ilia dawa: mu.
6 “Nítorí náà, mí ìmí ẹ̀dùn ìwọ ọmọ ènìyàn! Mí ìmí ẹ̀dùn pẹ̀lú ọkàn ìbànújẹ́ àti ẹ̀dùn ọkàn kíkorò ní iwájú wọn.
Dunu egefe! Dia se baligili nababe dunu defele, gogonomoma. Gogolo nabi dunu defele, dunu huluane ba: ma: ne, gogonomoma.
7 Bí wọ́n bá sì bi ọ́, wí pé, ‘Kí ni ó dé tí ìwọ fi ń mí ìmí ẹ̀dùn?’ Ìwọ yóò wí pé, ‘Nítorí ìròyìn tí ó ń bẹ. Gbogbo ọkàn ni yóò yọ́, gbogbo ọwọ́ ni yóò sì di aláìlera; gbogbo ọkàn ní yóò dákú, gbogbo eékún ni yóò sì di aláìlera bí omi?’ Ó ń bọ̀! Yóò sì wa sí ìmúṣẹ dandan, ni Olúwa Olódùmarè wí.”
Ilia da dia gogonomosu bai dima adole ba: sea, ilima se iasu bagade da misunuba: le, di da gogonomosa sia: ma. Amo se nabasu da doaga: sea, ilia da bagade beda: mu, ilia lobo da gadaiamu, ilia da nimi hame ba: mu, amola ilia muguni da yagugumu. Eso da doaga: i dagoi,” Ouligisudafa Hina Gode da sia: i dagoi.
8 Ọ̀rọ̀ Olúwa si tún tọ̀ mí wá pé:
Hina Gode da nama amane sia: i,
9 “Ọmọ ènìyàn, sọtẹ́lẹ̀ wí pé, èyí yìí ní Olúwa wí pé, “‘Idà kan, idà kan, tí a pọ́n, tí a sì dán pẹ̀lú,
“Dunu egefe! Ba: la: loma! Na, Hina Gode, Na sia: be amo dunuma adosisima, ‘Gegesu gobihei mei amola ela: mei diala.
10 a pọ́n láti pa ènìyàn púpọ̀, a dán an láti máa kọ mọ̀nà! “‘Àwa o ha máa ṣe àríyá ọ̀gọ ọmọ mi? Idà gán gbogbo irú igi bẹ́ẹ̀.
Gobihei da fane legemusa: debele mei. Amola ha: ha: na agoane ela: mene gala: ma: ne ela: mei. Na fi dunu da sisasu amola se iasu ea olelei, amo huluane hame nababeba: le, nodosu hamomu da hamedei.
11 “‘Idà ní a yàn láti pọ́n, kí ó lè ṣe é gbámú; a pọ́n ọn, a sì dán an, ó ṣetán fún ọwọ́ àwọn apani.
Gobihei da giga: ne ela: mene gaguli lamusa: momagele legei dagoi diala. Amalu debele, giga: ne, medole legesu dunu ilia lobo da: iya ligisima: ne, momagei diala.
12 Sọkún síta, kí ó sì pohùnréré ẹ̀kún, ọmọ ènìyàn, nítorí yóò wá sórí àwọn ènìyàn mi; yóò wá sórí gbogbo ọmọ-aládé Israẹli ìbẹ̀rù ńlá yóò wá sórí àwọn ènìyàn mi nítorí idà náà; nítorí náà lu oókan àyà rẹ.
Dunu egefe! Gogolole ha: gi dima! Amo gobihei da Na dunu amola Isala: ili ouligisu dunu huluane, ili medole legema: ne diala. Ili amola Na dunu huluane eno amola da gilisili medole legei dagoi ba: mu. Di da heawini se bagade nababeba: le, dia bida: gia lulufugima.
13 “‘Ìdánwò yóò dé dandan. Tí ọ̀pá aládé Juda èyí tí idà kẹ́gàn, kò bá tẹ̀síwájú mọ́ ń kọ́? Ni Olúwa Olódùmarè wí.’
Na da Na dunuma adoba: sa. Amola ilia da sinidigimu higasea, amo sia: i liligi huluane da ilima doaga: mu.
14 “Nítorí náà, ọmọ ènìyàn, sọtẹ́lẹ̀ kí ó sì fi ọwọ́ lu ọwọ́. Jẹ́ kí idà lu ara wọn lẹ́ẹ̀méjì, kódà ní ẹ̀ẹ̀mẹta. Ó jẹ́ idà fún ìpànìyàn idà fún ìpànìyàn lọ́pọ̀lọ́pọ̀, tí yóò sé wọn mọ́ níhìn-ín àti lọ́hùnnún.
Dunu egefe! Na gasa bagade sia: Yelusaleme fi ilima adosima! Dia lobo fama! Amasea, gegesu gobihei sedade da eno fane, eno fane, fananumu. Amo gegesu gobihei da medole legema: ne, amola dunu beda: gia: ma: ne hamosu dawa:
15 Kí ọkàn kí ó lè yọ́ kí àwọn tí ó ṣubú le pọ̀, mo ti gbé idà sí gbogbo bodè fún ìparun. Háà! A mú kí ó kọ bí ìmọ̀nàmọ́ná, a gbá a mú fún ìparun.
Amo gegesu gobihei ea hamobeba: le, Na fi dunu da beda: igia: sa amola dafasa. Na da gobihei amo da ha: ha: na agoane gagala: sa, amola medole legemusa: momagei dagoi, amoga ilia moilai amoma magagisa.
16 Ìwọ idà, jà sí ọ̀tún kí o sì jà sí òsì lọ ibikíbi tí ẹnu rẹ bá dojúkọ.
Gobihei mei! Di da dia lobodafadili, amola fofadidili ele galu damuma! Di da habodili delegisia, amo defele damuma.
17 Èmi gan an yóò pàtẹ́wọ́ ìbínú mi yóò sì rẹlẹ̀. Èmi Olúwa ti sọ̀rọ̀.”
Na da Na lobo famu, amasea Na ougi da gumi ba: mu. Na, Hina Gode da sia: i dagoi.”
Hina Gode da nama amane sia: i,
19 “Ọmọ ènìyàn la ọ̀nà méjì fún idà ọba Babeli láti gbà, kí méjèèjì bẹ̀rẹ̀ láti ìlú kan náà. Ṣe àmì sí ìkóríta ọ̀nà tí ó lọ sí ìlú náà.
“Dunu egefe! Ba: bilone hina bagade dunu da ea gobihei gaguli misa: ne, logo aduna ilegema. Ela da soge afadafa amoga hemomu. Logo da sagulufai galea, amogai dawa: digisu ifa bugima.
20 La ọ̀nà kan fún idà láti wá kọlu Rabba ti àwọn ará Ammoni kí òmíràn kọlu Juda, kí ó sì kọlu Jerusalẹmu ìlú olódi.
Logo afae da Ba: bilone hina bagade dunu amoma A: mounaide moilai bai bagade La: ba amoga ahoasu logo olelemu, amola eno da Yuda fi ilia moilai bai bagade Yelusaleme gasa bagade gagili sali, amoga ahoasu olelemu.
21 Nítorí ọba Babeli yóò dúró ni ìyànà ní ojú ọ̀nà, ní ìkóríta, láti máa lo àfọ̀ṣẹ. Yóò fi ọfà di ìbò, yóò béèrè lọ́wọ́ àwọn òrìṣà rẹ̀, òun yóò ṣe àyẹ̀wò ẹ̀dọ̀.
Ba: bilone hina bagade dunu da logo sagulufaia, dawa: digima: ne ifala dafulili lela. E da ea logo masunu dawa: ma: ne, ea dadi fofoga: sa. E da ea ogogosu loboga hamoi ‘gode’ ilima adole ba: sa. E da gobele salasu ohe ea habe abedesa.
22 Nínú ọwọ́ ọ̀tún rẹ ni ìbò Jerusalẹmu yóò ti wá, ní ibi tí yóò ti gbé afárá kalẹ̀, láti pàṣẹ fún àwọn apànìyàn, láti mú ki wọn hó ìhó ogun láti gbé òòlù dí ẹnu-ọ̀nà ibodè, láti mọ odi, àti láti kọ́ ilé ìṣọ́.
Waha! Ea lobodafa da sou amoga ‘Yelusaleme’ dedei, amo gagui dialebe ba: sa. Amo da ema agoane olelesa. E da Yelusaleme amoga asili, ifa damui dou sosu amoga logo ga: su muguluma: ne, amola gegemusa: gini bulalisu, amola osobo gasa: gala: su, amola gegesu adobo dogosu, hamoma: ne olelesa.
23 Àfọ̀ṣẹ náà yóò dàbí àmì èké sí àwọn tí ó ti búra ìtẹríba fún un, ṣùgbọ́n òun yóò ran wọn létí ẹbí wọn yóò sì mú wọn lọ sí ìgbèkùn.
Yelusaleme fi dunu da musa: Ba: bilone hina bagade ema gousa: su ilegeiba: le, e da Yelusaleme amoma doagala: mu sia: , amo ilia da ogogosuyale dawa: mu. Be amo ba: la: lusu da ilia wadela: i hou hamoi ili dawa: digima: ne, amola ilia huluane da enoga doagala: le fedei dagoi ba: mu, amo olelema: ne misi.
24 “Nítorí náà èyí ní ohun tí Olúwa Olódùmarè wí: ‘Nítorí ti ẹ̀yin ti mú ẹ̀bi yín wá sí ìrántí nípa ìṣọ̀tẹ̀ ní gbangba, ní ṣíṣe àfihàn àwọn ẹ̀ṣẹ̀ rẹ nínú gbogbo ohun tí ó ṣe, nítorí tí ẹ̀yin ti ṣe èyí, a yóò mú yín ní ìgbèkùn.
Na, Ouligisudafa Hina Gode, da amane sia: sa, ‘Dilia wadela: i hou musa: wamolegei dialu, wali dunu huluane ba: ma: ne odagia ba: sa. Dilia hamobe huluane da dilia wadela: i hou olelesa. Dilia dafawanedafa wadela: idafa hamoiba: le, Na da dilima fofada: ne, se iasu imunu gala. Na da dilia ha lai dunuma dili iagamu.
25 “‘Ìwọ aláìmọ́ àti ẹni búburú ọmọ-aládé Israẹli, ẹni ti ọjọ́ rẹ̀ ti dé, ẹni tí àsìkò ìjìyà rẹ̀ ti dé góńgó,
Di, wadela: idafa, hadigi hame, Isala: ili hina bagade dunu! Na da dima bogoma: ne se bidi imunu.
26 èyí yìí ní ohun tí Olúwa Olódùmarè wí, tú ìwérí kúrò kí o sì gbé adé kúrò. Kò ní rí bí ti tẹ́lẹ̀, ẹni ìgbéga ni a yóò sì rẹ̀ sílẹ̀.
Na, Ouligisudafa Hina Gode, da sia: i dagoi. Dia gouliga hamoi habuga, amola abulaga hamoi habuga, gisa: le fasima. Waha hou da afadenene, musa: agoane bu hame ba: mu. Na da hame gagui dunu, ilia soge gasawane ouligima: ne, gaguia gadomu. Na da wali gasa fi ouligisu dunu amo fadegale fasili, ilia da gudu sa: i dagoi ba: mu.
27 Ìparun! Ìparun! Èmi yóò ṣé e ni ìparun! Kì yóò padà bọ̀ sípò bí kò ṣe pé tí ó bá wá sí ọ̀dọ̀ ẹni tí ó ní ẹ̀tọ́ láti ni in; òun ni èmi yóò fi fún.’
Gugunufinisisu! Dafawane! Yelusaleme da wadela: lesi dagoi ba: mu! Na da amo wadela: lesimu. Be dunu amo Na da e Yelusaleme fi ilima se ima: ne ilegei, amo da doaga: sea fawane amo hou ba: mu. Amasea, Na da Yelusaleme ema iagamu.
28 “Àti ìwọ, ọmọ ènìyàn sọtẹ́lẹ̀ kí ó sì wí pé, ‘Èyí yìí ní ohun tí Olúwa Olódùmarè wí nípa àwọn ará Ammoni àti àbùkù wọn: “‘Idà kan idà kan tí á fa yọ fún ìpànìyàn tí a dán láti fi ènìyàn ṣòfò àti láti kọ bí ìmọ̀nàmọ́ná!
“Dunu egefe! Ba: la: loma! Di, A:mounaide dunu (amo da Na fi Isala: ili dunuma gadesa) ilima Na gasa bagade sia: adosima. Amane sia: ma, ‘Gegesu gobihei bagade da dili wadela: lesimusa: momagei diala. E da medole legemusa: , amola ha: ha: na agoane nene gagala: musa: , ela: mei diala.
29 Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé a rí èké nípa yín àti àfọ̀ṣẹ èké nípa yín a yóò gbé e lé àwọn ọrùn ènìyàn búburú ti a ó pa, àwọn tí ọjọ́ wọn ti dé, àwọn tí ọjọ́ ìjìyà wọn ti dé góńgó.
Esala ba: su dilia ba: lala, amo da ogogosa. Amola dia ba: la: lusu da ogogosa. Dilia da wadela: idafa, amola dilia wadela: mu eso da mana. Fedege agoane, gegesu gobihei bagade da dilia galogoa hedofamu.
30 “‘Dá idà padà sínú àkọ̀ rẹ̀. Níbi tí a gbé ṣẹ̀dá yín, ní ibi tí ẹ̀yin ti ṣẹ̀ wá.
Bu mae gegema: ne, dilia gegesu gobihei hina: salasuga sanasima. Na da dilia hahamoi soge amola dilia lalelegei soge amoga dilima fofada: mu.
31 Níbẹ̀ ni èmi yóò ti ṣe ìdájọ́ yín, èmi o sì fi èémí ìbínú gbígbóná mi bá yín jà.
Na da lalu agoane, Na ougi se bidi imunu, amola dilia da amo se nabimu. Amola Na da dili sa: digini fasu dawa: dunu, amo dili wadela: lesima: ne iagamu.
32 Ẹ̀yin yóò jẹ́ èpò fún iná náà, a yóò ta ẹ̀jẹ̀ yin sórí ilẹ̀ yín, a kì yóò rántí yín mọ́; nítorí Èmi Olúwa ní ó ti wí bẹ́ẹ̀.’”
Dilia da laluga gugunufinisi dagoi ba: mu. Dilia sogedafa amo ganodini, eno dunu da dili medole legemu. Amola, dunu enoga dili bu hame dawa: lumu. Bai Na, Hina Gode da sia: i dagoi.’”