< Ezekiel 20 >

1 Ní ọjọ́ kẹwàá, oṣù karùn-ún ọdún keje, ní díẹ̀ nínú àwọn àgbàgbà Israẹli wá wádìí lọ́wọ́ Olúwa, wọn jókòó níwájú mi.
Ug nahitabo sa ikapito ka tuig, sa ikalima ka bulan, sa ikanapulo ka adlaw sa bulan, nga dihay pipila sa mga anciano sa Israel nga ming-abut aron sa pagpakisayud mahitungod kang Jehova, ug minglingkod sa akong atubangan.
2 Nígbà náà ni ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá wí pé,
Ug ang pulong ni Jehova midangat kanako, nga nagaingon:
3 “Ọmọ ènìyàn, sọ fún àwọn àgbàgbà Israẹli, kì ó sì wí fún wọn pé, ‘Báyìí ní Olúwa Olódùmarè wí, ṣe ki ẹ lè wádìí lọ́dọ̀ mi ni ẹ ṣe wá? Bí mo ti wà láààyè, ní Olúwa Olódùmarè wí, Èmi kì yóò gbà kí ẹ wádìí lọ́dọ̀ mi.’
Anak sa tawo, sumulti ka sa mga anciano sa Israel, ug umingon ka kanila: Mao kini ang giingon sa Ginoong Jehova: Mianhi ba kamo sa pagpakigsayud mahitungod kanako? Ingon nga ako buhi, nagaingon ang Ginoong Jehova, ako dili buot nga pakisayran ninyo.
4 “Ìwọ fẹ́ dájọ́ wọn bí? Ìwọ fẹ́ dájọ́ wọn bí ọmọ ènìyàn? Nítorí náà fi gbogbo ìwà ìríra baba wọn kò wọ́n lójú,
Hukman mo ba sila, anak sa tawo, hukman mo ba sila? pahibaloon mo sila sa mga dulumtanan sa ilang mga amahan;
5 kí ó sì sọ fún wọn pé, ‘Báyìí ní Olúwa Olódùmarè wí, ní ọjọ́ tí mo yàn Israẹli, mo gbé ọwọ́ mi sókè nínú ìbúra sí àwọn ọmọ ilé Jakọbu, mo sì fi ara mi hàn wọn ní Ejibiti, mo gbé ọwọ́ mi sókè nínú ẹ̀jẹ́ wí pé, “Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín.”
Ug umingon ka kanila: Mao kini ang giingon sa Ginoong Jehova: Sa adlaw sa akong pagpili sa Israel, ug sa nanumpa ako sa kaliwat sa balay ni Jacob, ug sa nagpaila ako sa akong kaugalingon kanila didto sa yuta sa Eqipto, sa diha nga nanumpa ako kanila, nga nagaingon: Ako mao si Jehova nga inyong Dios;
6 Ní ọjọ́ náà mo lọ búra fún wọn pé, èmi yóò mú wọn jáde kúrò ni ilẹ̀ Ejibiti lọ sí ilẹ̀ ti mo ti wá sílẹ̀ fún wọn, ilẹ̀ tí ó ń sàn fún wàrà àti oyin, ilẹ̀ tí ó lẹ́wà jùlọ láàrín àwọn ilẹ̀ yòókù.
Niadtong adlawa ako nanumpa kanila, sa pagdala kanila sa gawas gikan sa yuta sa Eqipto ngadto sa usa ka yuta nga akong nasusi alang kanila, yuta nga nagapaagay sa gatas ug dugos, nga maoy himaya sa tanang mga yuta.
7 Mo sì wí fún wọn pé, “Kí olúkúlùkù nínú yín gbé ìríra ojú rẹ̀ kúrò, kí ẹ sì má bá sọ ara yín di àìmọ́ pẹ̀lú àwọn òrìṣà Ejibiti, èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín.”
Ug miingon ako kanila: Isalibay ninyo sa tagsatagsa ka tawo ang mga dulumtanan sa inyong mga mata, ug ayaw ninyo paghugawi ang inyong kaugalingon uban sa mga dios-dios sa Egipto; ako mao si Jehova nga inyong Dios.
8 “‘Ṣùgbọ́n wọn ṣọ̀tẹ̀ sí mi wọn kò sì gbọ́rọ̀, wọn kò gbé àwòrán ìríra tí wọ́n dojúkọ kúrò níwájú wọn bẹ́ẹ̀ ni wọn kò si kọ̀ àwọn òrìṣà Ejibiti sílẹ̀, torí náà mo sọ pé èmi yóò tú ìbínú gbígbóná mi lé wọn lórí, èmi yóò sì jẹ́ kí ìbínú mi sẹ̀ lórí wọn ní ilẹ̀ Ejibiti.
Apan sila mingsukol batok kanako, ug wala mamati kanako; ang tagtatagsa kanila wala magsalibay sa mga dulumtanan sa ilang mga mata, ni mingbiya sila sa mga dios-dios sa Egipto. Unya ako miingon, ibubo ko ang akong kaligutgut diha sa ibabaw nila, aron sa pagtibawas sa akong kasuko batok kanila sa taliwala sa yuta sa Egipto.
9 Ṣùgbọ́n nítorí orúkọ mi, mo ṣe ohun tí kò ní jẹ́ kí orúkọ mi bàjẹ́ lójú àwọn orílẹ̀-èdè tí wọn ń gbé láàrín wọn, lójú àwọn ẹni tí mo ti fi ara hàn fún ara Israẹli nípa mímú wọn jáde ní ilẹ̀ Ejibiti.
Apan gibuhat ko ang angay alang sa akong ngalan, aron kini dili panamastamasan sa atubangan sa mga nasud, diin sila anaa sa taliwala, sa kang kansang pagtan-aw gipaila ko kanila ang akong kaugalingon pinaagi sa pagdala kanila sa gawas sa yuta sa Egipto.
10 Nítorí náà, mo mú wọn jáde ní ilẹ̀ Ejibiti mo sì mú wọn wá sínú aginjù.
Busa ako silang gipagula gikan sa yuta sa Egipto, ug gihatud ko sila ngadto sa kamingawan.
11 Mo sì fún wọn ni òfin mi, mo sì fi àwọn òfin mi hàn wọ́n; nítorí pé ẹni tó bá ṣe wọ́n yóò yè nípa wọn.
Ug gihatag ko kanila ang akong kabalaoran, ug gipakita kanila ang akong mga tulomanon, nga kong tumanon sa tawo, siya mabuhi diha kanila.
12 Bẹ́ẹ̀ ni mo fún wọn ní ọjọ́ ìsinmi gẹ́gẹ́ bí àmì láàrín àwọn àti èmi, kí wọn lè mọ̀ pé èmi ni Olúwa tó sọ wọn di mímọ́.
Labut pa usab gihatag ko kanila ang akong mga adlawng igpapahulay, aron mahimong usa ka timaan sa taliwala kanako ug kanila, aron sila makaila nga ako mao si Jehova nga ngabalaan kanila.
13 “‘Síbẹ̀; ilé Israẹli ṣọ̀tẹ̀ sí mí nínú aginjù. Wọn kò tẹ̀lé àṣẹ mi, wọn sì kọ àwọn òfin mi sílẹ̀ bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ẹni tó bá pa á mọ́ yóò yè nínú rẹ̀. Wọn sì sọ ọjọ́ ìsinmi mi di aláìmọ́ lọ́pọ̀lọ́pọ̀. Nítorí náà, mo sọ pé èmi yóò tú ìbínú gbígbóná mi sórí wọn, èmi yóò sì pa wọ́n run nínú aginjù.
Apan ang balay sa Israel misukol batok kanako didto sa kamingawan: sila wala maglakaw sa akong kabalaoran, ug gisalikway nila ang akong mga tulomanon, nga kong bantayan kini sa tawo, siya mabuhi diha kanila; ug ang akong mga adlawng igpapahulay ilang gipasipalahan sa hilabihan gayud. Unya ako miingon nga ibubo ko ang akong kaligutgut diha sa ibabaw nila didto sa kamingawan, aron sa pag-ut-ut kanila.
14 Ṣùgbọ́n nítorí orúkọ mi, mo ṣe ohun tí kò ní mú kí orúkọ mi bàjẹ́ lójú àwọn orílẹ̀-èdè tí mo kó wọn jáde.
Apan gibuhat ko ang angay alang sa akong ngalan, aron kini dili pasipalahan sa atubangan sa mga nasud, sa kang kansang pagtan-aw sila gipagula ko.
15 Nítorí náà, mo tún gbọ́wọ́ mi sókè ní ìbúra fún wọn nínú aginjù pé, èmi kì yóò mú wọn dé ilẹ̀ tí mo fi fún wọn—ilẹ̀ tí ó ń sàn fún wàrà àti oyin, ilẹ̀ tí ó lẹ́wà jùlọ láàrín àwọn ilẹ̀ yòókù.
Labut pa usab gipanumpa ko kanila didto sa kamingawan, nga sila dili ko unta dad-on ngadto sa yuta nga gihatag ko kanila, yuta nga nagapaagay sa gatas ug dugos, nga maoy himaya sa tanang mga yuta;
16 Nítorí pé, wọn kọ òfin mi sílẹ̀, wọn kò sì tẹ̀lé àṣẹ mi, wọn sọ ọjọ́ ìsinmi mi dí aláìmọ́. Nítorí pé tọkàntọkàn ni wọn ń tẹ̀lé òrìṣà wọn.
Tungod kay gisalikway nila ang akong mga tulomanon, ug sila wala maglakaw sa akong kabalaoran, ug nanagpasipala sa akong mga adlawng igpapahulay: kay ang ilang kasingkasing nanagsunod sa ilang mga dios-dios.
17 Síbẹ̀síbẹ̀ mo wò wọ́n pẹ̀lú àánú, ń kò sì pa wọ́n run tàbí kí òpin dé bá wọn nínú aginjù.
Bisan pa niana gipagawas sila sa akong mata, ug sila wala ko laglaga, ni itibawason ko sila didto sa kamingawan.
18 Ṣùgbọ́n mo sọ fún àwọn ọmọ wọn nínú aginjù pé, “Ẹ má ṣe rìn ní ìlànà àwọn baba yín, ẹ má ṣe pa òfin wọn mọ́, ẹ má ṣe bá ara yín jẹ́ pẹ̀lú òrìṣà wọn.
Ug ako miingon sa ilang mga anak didto sa kamingawan: Ayaw kamo paglakaw sa kabalaoran sa inyong mga amahan, ni magtuman kamo sa ilang mga tulomanon, ni maghugaw kamo sa inyong kaugalingon sa ilang mga dios-dios.
19 Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín, ẹ tẹ̀lé àṣẹ mi, kí ó sì pa òfin mi mọ́.
Ako mao si Jehova nga inyong Dios: managlakaw kamo sa akong kabalaoran ug bantayan ninyo ang akong tulomanon ug tumana sila;
20 Ẹ ya ọjọ́ ìsinmi mi sí mímọ́ kí ó lè jẹ́ àmì láàrín wa, ki ẹ lè mọ̀ pé èmi ní Olúwa Ọlọ́run yín.”
Ug balaana ang akong mga adlawng igpapahuklay; ug sila mahimong usa ka timaan sa taliwala kanako ug kaninyo, aron kamo makaila nga ako mao si Jehova nga inyong Dios.
21 “‘Ṣùgbọ́n àwọn ọmọ náà ṣọ̀tẹ̀ sí mi. Wọn kò tẹ̀lé àṣẹ mi, wọn kò sì pa òfin mi mọ́ bí o tilẹ̀ jẹ́ pé ẹni tó bá tẹ̀lé àwọn òfin yìí, yóò yè nínú rẹ̀, wọ́n sì tún sọ ọjọ́ ìsinmi mi di aláìmọ́. Nítorí náà, mo sọ pé èmi yóò tú ìbínú mi lórí wọn, Èmi yóò sì mú kí ìbínú gbígbóná mi wá sórí wọn ni aginjù.
Apan, ang mga anak mingsukol batok kanako; sila wala maglakaw sa akong kabalaoran, ni magbantay sa akong mga tulomanon sa pagtuman kanila, nga kong sila tumanon sa tawo, siya mabuhi diha kanila; gipasipalahan nila ang akong mga adlawng igpapahulay. Unya ako miingon nga ibubo ko ang akong kaligutgut diha sa ibabaw nila aron sa pagtibawas sa akong kasuko batok kanila didto sa kamingawan.
22 Síbẹ̀síbẹ̀ mo dáwọ́ dúró, nítorí orúkọ mi, mo sì ṣe ohun tí kò ní ba orúkọ mi jẹ́ lójú àwọn orílẹ̀-èdè ti mo kó wọn jáde lójú wọn.
Bisan pa niana ako nagpalikay sa akong kamot, ug gibuhat ko ang angay alang sa akong ngalan aron kini dili pasipalahan diha sa atubangan sa mga nasud, sa kang kansang pagtan-aw gipagula ko sila.
23 Bẹ́ẹ̀ ni pẹ̀lú ọwọ́ ti mo gbé sókè sí wọn, mo búra fún wọn nínú aginjù pé èmi yóò tú wọn ka sì àárín àwọn orílẹ̀-èdè, èmi yóò sì fọ́n wọn káàkiri ilẹ̀ gbogbo,
Labut pa ako nanumpa kanila didto sa kamingawan, nga patlaagon ko sila sa taliwala sa mga nasud, ug patibulaagon ko sila latas sa mga nasud;
24 nítorí pé wọn kò pa òfin mi mọ́, wọn sì tún kọ àṣẹ mi sílẹ̀, wọn tún sọ ọjọ́ ìsinmi mi di aláìmọ́. Ojú wọn sì wà ní ara òrìṣà baba wọn.
Tungod kay wala sila magtuman sa akong mga tulomanon, kondili nanagsalikway sa akong kabalaoran, ug nanagpasipala sa akong mga adlawng igpapahulay, ug ang ilang mga mata nanagnunot sa mga dios-dios sa ilang mga amahan.
25 Èmi náà sì fi wọn fún ìlànà tí kò dára àti òfin tí wọn kò le e yè nípa rẹ̀;
Labut pa usab kanila gihatag ko nga silot ang kabalaoran nga dili maayo, ug mga tulomanon diin sila dili mabuhi;
26 mo jẹ́ kí ó sọ wọn di aláìmọ́ nípa ẹ̀bùn nípa fífi àkọ́bí ọmọ wọn rú ẹbọ sísun, àkọ́bí wọn la iná kọjá, kí èmi sọ wọ́n di ahoro, kí wọn le mọ̀ pé èmi ni Olúwa.’
Ug sila gipahugawan ko sa kaugalingon nilang mga gasa, nga niana ilang gipaagi sa kalayo ang tanan kadto nga ming-abli sa tagoangkan, aron sila wagtangon ko, sa katuyoan nga sila makaila unta nga ako mao si Jehova.
27 “Nítorí náà, Ọmọ ènìyàn, sọ fún ilé Israẹli kí ó sì wí fún wọn pé, ‘Èyí ní ohun ti Olúwa Olódùmarè wí, nínú èyí tí baba yín ti sọ̀rọ̀-òdì sí mi, nípa kíkọ̀ mí sílẹ̀.
Busa, anak sa tawo, sumulti ka sa balay sa Israel, ug umingon ka kanila: Mao kini ang giingon sa Ginoong Jehova: Labut pa niining paagiha ang inyong mga amahan nagpasipala kanako, nga niana sila nakasala batok kanako.
28 Nítorí nígbà tí mo mú wọn dé ilẹ̀ náà, tí mo gbé ọwọ́ mi sókè láti fi í fún wọn, nígbà náà ni wọ́n rí olúkúlùkù òkè gíga, àti gbogbo igi bíbò, wọ́n sì rú ẹbọ wọn níbẹ̀, wọ́n sì gbé ìmúnibínú ọrẹ wọ́n kalẹ̀ níbẹ̀; níbẹ̀ pẹ̀lú ni wọ́n ṣe òórùn dídùn wọn, wọ́n sì ta ohun ọrẹ mímu sílẹ̀ níbẹ̀.
Kay sa diha nga gipasulod ko sila ngadto sa yuta, nga akong gipanumpaan sa paghatag kanila, unya sila nakakita sa tagsatagsa ka hataas nga bungtod, ug sa tanang mga kahoy nga madasok ug sila nanagdulot didto sa ilang mga halad, ug didto gitanyag nila sa pagkamahagiton ang ilang halad; didto usab gibuhat nila ang ilang maamyon nga kahumot, ug didto gibubo ang ilang mga halad-nga-ilimnon.
29 Nígbà náà ni mo wí fún wọn pé, kí ní ibi gíga tí ẹ̀yin lọ yìí?’” (Orúkọ rẹ̀ ni a sì ń pè ní Bama di òní yìí.)
Unya ako miingon kanila: Unsa ba alang kaninyo ang kahulogan sa hataas nga dapit diin kamo moadto? Busa ang ngalan niana ginatawag nga Bama hangtud niining adlawa.
30 “Nítorí náà sọ fún ilé Israẹli pé, ‘Èyí ní ohun tí Olúwa Olódùmarè wí, ṣé o fẹ́ ba ara rẹ jẹ́ bi àwọn baba rẹ ṣe ṣe, tiwọn ń ṣe àgbèrè nípa títẹ̀lé àwọn àwòrán ìríra?
Tungod niini umingon ka sa balay sa Israel: Mao kini ang giingon sa Ginoong Jehova: Gihugawan ba ninyo ang inyong kaugalingon ingon sa batasan sa inyong mga amahan? ug nakighilawas ba kamo sumala sa ilang mga dulumtanan?
31 Nígbà tí ẹ̀yin bá san ọrẹ yìí, ìrúbọ ọmọkùnrin ọmọ yín, tí ẹ mú ọmọ yin la iná kọjá, ẹ̀yin ń tẹ̀síwájú láti ba ara yín jẹ́ pẹ̀lú àwọn òrìṣà yín títí di òní yìí, ẹ̀yin yóò ha jẹ wádìí lọ́dọ̀ mi, ìwọ ilé Israẹli? Bí mo ti wà láààyè, ní Olúwa Olódùmarè wí, Èmi ki yóò jẹ́ kí ẹ wádìí lọ́dọ̀ mi.
Ug sa diha nga nanghatag kamo sa inyong mga gasa, sa diha nga gipaagi ninyo ang inyong mga anak diha sa kalayo, gihugawan ba ninyo ang inyong kaugalingon uban ang tanan ninyong mga dios-dios bisan hangtud ninyo ining adlawa? ug ako pakisayran pa ba diay ninyo, Oh balay sa Israel? Ingon nga ako buhi, nagaingon ang Ginoong Jehova, ako dili gayud pakisayran ninyo:
32 “‘Ẹ̀yin wí pé, “Àwa fẹ́ dàbí àwọn orílẹ̀-èdè yòókù, bí àwọn ènìyàn ayé, tó ń bọ igi àti òkúta.” Ṣùgbọ́n ohun ti ẹ ni lọ́kàn kò ní ṣẹ rárá.
Ug kadtong mosulod sa inyong panumduman dili gayud mahitabo, sa pagkaagi nga kamo mag-ingon: Manig-ingon kita sa mga nasud, sama sa mga panimalay sa kayutaan, sa ilang pag-alagad sa kahoy ug bato.
33 Bí mo ti wà láààyè, ní Olúwa Olódùmarè wí, Èmi yóò jẹ ọba lórí yín pẹ̀lú ọwọ́ agbára tí èmi yóò nà jáde pẹ̀lú ìtújáde ìbínú gbígbóná mi.
Ingon nga ako buhi, nagaingon ang Ginoong Jehova, sa pagkamatuod uban ang kamot nga gamhanan, ug uban ang tinuy-od nga bukton ug uban ang kaligutgut nga binubo, ako magahari sa ibabaw ninyo.
34 Èmi yóò si mú yín jáde kúrò láàrín àwọn ènìyàn, èmi yóò sì ṣà yín jọ láàrín àwọn orílẹ̀-èdè tí a fọ́n yín sí pẹ̀lú ọwọ́ agbára àti apá nínà tí èmi yóò nà jáde àti pẹ̀lú ìtújáde ìbínú gbígbóná ni.
Ug panguhaon ko kamo gikan sa mga katawohan, ug tigumon ko kamo gikan sa mga kayutaan diin kamo gipatibulaag, uban ang kamot nga gamhanan, ug uban ang bukton nga tinuy-od, ug uban ang kaligutgut nga binubo;
35 Èmi yóò si mú yín wá sí aginjù àwọn orílẹ̀-èdè, níbẹ̀ ni ojúkójú ni èmi yóò ṣe ìdájọ́ lé e yín lórí.
Ug kamo dad-on ko ngadto sa kamingawan sa mga katawohan, ug didto hukman ko kamo, sa nawong ug nawong.
36 Bí mo ṣe ṣe ìdájọ́ àwọn baba yín nínú aginjù nílẹ̀ Ejibiti, bẹ́ẹ̀ ni èmi yóò ṣe ìdájọ́ yín ní Olúwa Olódùmarè wí.
Ingon sa paghukom ko sa inyong mga amahan didto sa kamingawan sa yuta sa Eqipto, ingon man pagahukman ko kamo, nagaingon ang Ginoong Jehova.
37 Èmi yóò kíyèsi i yín bí mo ti mú un yín kọjá lábẹ́ ọ̀pá, èmi yóò sì mú yín wá sí abẹ́ ìdè májẹ̀mú.
Ug kamo pasung-on ko ilalum sa akong sungkod, ug dad-on ko kamo ngadto sa higot sa tugon;
38 Èmi yóò si ṣa àwọn ọlọ̀tẹ̀ kúrò láàrín yín, àti àwọn o lù re òfin kọjá, èmi yóò mu wọn jáde kúrò ni ilẹ̀ tiwọn gbé ṣe àtìpó, wọn ki yóò si wọ ilẹ̀ Israẹli. Nígbà náà ní ẹ̀yin yóò mọ̀ pé, èmi ní Olúwa.
Ug paphaon ko gikan sa inyong taliwala ang mga masukihon, ug kadtong nanagpakasala batok kanako; panad-on ko sila ngadto sa gawas gikan sa yuta diin sila magapuyo, apan sila dili makasulod sa yuta sa Israel: ug kamo makaila nga ako mao si Jehova.
39 “‘Ní tí ẹ̀yin, ilé Israẹli, èyí ni ohun tí Olúwa Olódùmarè wí: Kí olúkúlùkù yín lọ máa sìn òrìṣà rẹ̀, ṣùgbọ́n lẹ́yìn èyí, ẹ̀yin yóò gbọ́ tèmi, ẹ̀yin kò sí ní i bá orúkọ mímọ́ mi jẹ́ pẹ̀lú ọrẹ àti àwọn òrìṣà yín mọ́.
Mahatungod kaninyo, Oh balay sa Israel, mao kini ang giingon sa Ginoong Jehova: Lakaw kamo, mag-alagad ang tagsatagsa kaninyo sa iyang mga dios-dios, ug kutob karon hangtud sa katapusan usab kong ugaling kamo dili magpatalinghug kanako; apan ang akong balaan nga ngalan dili na ninyo pasipalahan uban sa inyong mga gasa, ug uban sa inyong mga dios-dios.
40 Nítorí lórí òkè mímọ́ mi, lórí òkè gíga Israẹli, ni Olúwa Olódùmarè wí, níbẹ̀ ni ilẹ̀ náà ní gbogbo ilé Israẹli yóò sìn mí; èmi yóò sì tẹ́wọ́ gba wọ́n níbẹ̀. Níbẹ̀ èmi yóò béèrè ọrẹ àti ẹ̀bùn nínú àkọ́so yín pẹ̀lú gbogbo ẹbọ mímọ́ yín.
Kay sa akong balaan nga bukid, sa hataas nga bukid sa Israel, nagaingon ang Ginoong Jehova, didto ang tibook nga balay sa Israel, silang tanan magaalagad kanako diha sa yuta: didto, dawaton ko sila, ug didto pagakinahanglanon ko ang inyong mga halad, ug ang unang mga bunga sa inyong mga paghalad, uban ang tanan ninyong mga balaan nga butang.
41 Èmi yóò tẹ́wọ́ gbà yín gẹ́gẹ́ bí tùràrí olóòórùn dídùn nígbà tí mo ba mú yín jáde láàrín àwọn orílẹ̀-èdè tí a fọ́n yín ká sí, èmi yóò sì fi ìwà mímọ́ mi hàn láàrín yín lójú àwọn orílẹ̀-èdè.
Dawaton ko kamo ingon nga usa ka maamyon nga kahumot, sa diha nga kuhaon ko kamo gikan sa mga katawohan, ug sa diha nga tigumon ko kamo gikan sa mga kayutaan diin kamo gipatibulaag; ug ako pagabalaanon diha kaninyo sa atubangan sa mga nasud.
42 Nígbà náà ni ẹ o mọ̀ pé èmi ní Olúwa, nígbà tí mo bá mú yín wa sí ilẹ̀ Israẹli; sí ilẹ̀ tí mo gbọ́wọ́ mí sókè nínú ẹ̀jẹ́ láti fún àwọn baba yín.
Ug kamo makaila nga ako mao si Jehova, sa diha nga dad-on ko kamo ngadto sa yuta sa Israel, sulod sa yuta nga gipanumpa ko nga ihatag sa inyong mga amahan.
43 Níbẹ̀ ni ẹ ó wa rántí ìwà àti gbogbo ìṣesí yín, èyí tí ẹ̀yin fi sọ ara yín di aláìmọ́, ẹ̀yin yóò sì kórìíra ara yín fún gbogbo ibi tí ẹ̀yin ti ṣe.
Ug didto mahinumdum kamo sa inyong mga dalan, ug sa tanan ninyong mga buhat, diin kamo naghugaw sa inyong kaugalingon; ug kamo pagalud-on sa inyong kaugalingon diha sa inyong pagtan-aw tungod sa tanang mga kadautan nga inyong nabuhat.
44 Nígbà náà ní ẹ̀yin yóò mọ̀ pé, Èmi ni Olúwa, nígbà tí mo bá hùwà sí yín nítorí orúkọ mi ni, tí ń kò hùwà sí yín gẹ́gẹ́ bí ọ̀nà ibi àti ìwà ìríra yín. Ẹ̀yin ilé Israẹli, ni Olúwa Olódùmarè wí.’”
Ug kamo makaila nga ako mao si Jehova, sa diha nga mabuhat ko na ang angay kaninyo tungod sa akong ngalan, dili sumala sa inyong mga dautang dalan, ni sumala sa inyong mga hiwi nga buhat, Oh kamo nga sa balay sa Israel, nagaingon ang Ginoong Jehova.
45 Ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá:
Ug ang pulong ni Jehova midangat kanako, nga nagaingon:
46 “Ọmọ ènìyàn, dojúkọ ìhà gúúsù; wàásù lòdì sí gúúsù kí ìwọ sì sọtẹ́lẹ̀ sí igbó ilẹ̀ gúúsù.
Anak sa tawo, ipaatubang ang imong nawong paingon sa habagatan, ug ihulog ang imong pulong paingon sa habagatan, ug panagna batok sa kalasangan sa kapatagan sa Habagatan;
47 Sọ fún igbó ìhà gúúsù pé: ‘Gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa. Èyí ní ohun tí Olúwa Olódùmarè wí: Kíyèsi í, èmi yóò dá iná kan nínú rẹ̀, yóò sì jó olúkúlùkù igi tútù nínú rẹ̀, àti olúkúlùkù igi gbígbẹ. Jíjò ọwọ́ iná náà ní kí yóò ṣé é pa, àti gbogbo ojú láti gúúsù dé àríwá ni a ó sun nínú rẹ̀.
Ug umingon ka sa kalasangan sa Habagatan: Pamati sa pulong ni Jehova: Mao kini ang giingon sa Ginoong Jehova: Ania karon, ako magahaling ug kalayo diha kanimo, ug kini magaut-ut sa tanang lunhaw nga kahoy nga anaa kanimo, ug sa tanang laya nga kahoy: ang nagdilaab nga siga dili mapalong, ug ang tanang mga nawong gikan sa habagatan ngadto sa amihanan masunog niana.
48 Gbogbo ènìyàn yóò sì mọ̀ pé, Èmi Olúwa ni ó dá a, a kì yóò sì le è pa á.’”
Ug ang tanang unod makakita nga ako, si Jehova, maoy mihaling niini: kini dili mapalong.
49 Nígbà náà ni mo wí pé, “Háà! Olúwa Olódùmarè! Wọn ń wí fún mi pé, ‘Kì í wa ṣe pé òwe lo ń pa bí?’”
Unya miingon ako: Ah Ginoong Jehova: sila nagaingon tungod kanako: Dili ba siya maoy usa ka magsusulti sa mga sambingay?

< Ezekiel 20 >