< Ezekiel 20 >
1 Ní ọjọ́ kẹwàá, oṣù karùn-ún ọdún keje, ní díẹ̀ nínú àwọn àgbàgbà Israẹli wá wádìí lọ́wọ́ Olúwa, wọn jókòó níwájú mi.
Eso nabu amola oubi bi amola ode fesu ninia mugululi misi esoga ba: i. Isala: ili fi ouligisu dunu mogili da Hina Gode Ea hamomu hanai bai nama adole ba: musa: misini, na midadi bulagi.
2 Nígbà náà ni ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá wí pé,
Amalalu, Hina Gode da nama amane sia: i,
3 “Ọmọ ènìyàn, sọ fún àwọn àgbàgbà Israẹli, kì ó sì wí fún wọn pé, ‘Báyìí ní Olúwa Olódùmarè wí, ṣe ki ẹ lè wádìí lọ́dọ̀ mi ni ẹ ṣe wá? Bí mo ti wà láààyè, ní Olúwa Olódùmarè wí, Èmi kì yóò gbà kí ẹ wádìí lọ́dọ̀ mi.’
“Dunu egefe! Amo dunuma amane sia: ma, ‘Ouligisu Gode da amane sia: sa, Dilia da Na hamomu hanai adole ba: musa: misibala: ? Na da dafawane Ouligisudafa Hina Gode, amola Na da dili Nama adole ba: su logo hedofamu. Na, Ouligisudafa Hina Gode da sia: i dagoi.’
4 “Ìwọ fẹ́ dájọ́ wọn bí? Ìwọ fẹ́ dájọ́ wọn bí ọmọ ènìyàn? Nítorí náà fi gbogbo ìwà ìríra baba wọn kò wọ́n lójú,
Dunu egefe! Di da ilima fofada: ma: bela: ? Defea! Ilima fofada: ma! Ilia eda ilia wadela: i hou hamoi, amo ilia dawa: ma: ne, ilima olelema.
5 kí ó sì sọ fún wọn pé, ‘Báyìí ní Olúwa Olódùmarè wí, ní ọjọ́ tí mo yàn Israẹli, mo gbé ọwọ́ mi sókè nínú ìbúra sí àwọn ọmọ ilé Jakọbu, mo sì fi ara mi hàn wọn ní Ejibiti, mo gbé ọwọ́ mi sókè nínú ẹ̀jẹ́ wí pé, “Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín.”
Ilima amane sia: ma, ‘Ouligisudafa Hina Gode da amane sia: sa, Na da Isala: ili fi ilegeloba, amo esoha Na da Ya: igobe egaga fi Idibidi soge ganodini esalu ilima misini, Na lobo gaguia gadole, amane dafawane sia: i, ‘Na da dilia Hina Godedafa.’
6 Ní ọjọ́ náà mo lọ búra fún wọn pé, èmi yóò mú wọn jáde kúrò ni ilẹ̀ Ejibiti lọ sí ilẹ̀ ti mo ti wá sílẹ̀ fún wọn, ilẹ̀ tí ó ń sàn fún wàrà àti oyin, ilẹ̀ tí ó lẹ́wà jùlọ láàrín àwọn ilẹ̀ yòókù.
Amo esoha Na da ili Idibidi sogega fisili masa: ne asunasili, soge amo Na da ilima ima: ne hogole ba: i (soge ida: iwane fedege agoane bulamagau dodo maga: me amola agime hano bagadedafa galebeba: le, hano agoane a: iahoa) amoga oule masa: ne, dafawanedafa ilegele sia: i.
7 Mo sì wí fún wọn pé, “Kí olúkúlùkù nínú yín gbé ìríra ojú rẹ̀ kúrò, kí ẹ sì má bá sọ ara yín di àìmọ́ pẹ̀lú àwọn òrìṣà Ejibiti, èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín.”
Amola Na da ilima amane sia: i, ‘Dilia afae afae wadela: idafa loboga hamoi ‘gode’ liligi dilia ba: lala, amo galagama. Idibidi loboga hamoi ‘gode’ liligi da dilia hou ledo hamosa: besa: le, amo bu maedafa dawa: ma. Na da dilia Hina Gode esala.’
8 “‘Ṣùgbọ́n wọn ṣọ̀tẹ̀ sí mi wọn kò sì gbọ́rọ̀, wọn kò gbé àwòrán ìríra tí wọ́n dojúkọ kúrò níwájú wọn bẹ́ẹ̀ ni wọn kò si kọ̀ àwọn òrìṣà Ejibiti sílẹ̀, torí náà mo sọ pé èmi yóò tú ìbínú gbígbóná mi lé wọn lórí, èmi yóò sì jẹ́ kí ìbínú mi sẹ̀ lórí wọn ní ilẹ̀ Ejibiti.
Be ilia da Na sia: hame nabi amola Nama odoga: i. Ilia da ilia wadela: idafa loboga hamoi ‘gode’ hame galagai. Amola Idibidi ogogosu ‘gode’ ilima nodone sia: ne gadosu hou hame yolesi. Na da Idibidi sogega, Na ougi hou bagade ilima olelemusa: dawa: i galu.
9 Ṣùgbọ́n nítorí orúkọ mi, mo ṣe ohun tí kò ní jẹ́ kí orúkọ mi bàjẹ́ lójú àwọn orílẹ̀-èdè tí wọn ń gbé láàrín wọn, lójú àwọn ẹni tí mo ti fi ara hàn fún ara Israẹli nípa mímú wọn jáde ní ilẹ̀ Ejibiti.
Be Na da amane hame hamoi. Bai Na Dio wadela: sa: besa: le, hame hamoi. Na da Idibidi dunu ba: ma: ne, Na da Isala: ili dunuma ili Idibidi sogega fisili masa: ne, Na da ili ga oule masa: ne sisia: i dagoi. Amaiba: le, Na da ogogosu dunu ilia dawa: sa: besa: le, ilima ougi se bidi hame i.
10 Nítorí náà, mo mú wọn jáde ní ilẹ̀ Ejibiti mo sì mú wọn wá sínú aginjù.
Amaiba: le, Na da Isala: ili dunu Idibidi sogega fisili masa: ne, ili hafoga: i sogega oule asi.
11 Mo sì fún wọn ni òfin mi, mo sì fi àwọn òfin mi hàn wọ́n; nítorí pé ẹni tó bá ṣe wọ́n yóò yè nípa wọn.
Na hamoma: ne sia: i amola sema da nowa dunu da nabawane hamosa, amoma esalusu iaha. Amo malei amola sema Na da Isala: ili dunuma olelei.
12 Bẹ́ẹ̀ ni mo fún wọn ní ọjọ́ ìsinmi gẹ́gẹ́ bí àmì láàrín àwọn àti èmi, kí wọn lè mọ̀ pé èmi ni Olúwa tó sọ wọn di mímọ́.
Na da Sa: bade eso sema ilima i. Sa: bade eso da Na gousa: su hamoi, amoma dawa: digima: ne olelesu, amola Na da ilia hou bu hadigima: ne hamomu, amo dawa: digima: ne hamoi.
13 “‘Síbẹ̀; ilé Israẹli ṣọ̀tẹ̀ sí mí nínú aginjù. Wọn kò tẹ̀lé àṣẹ mi, wọn sì kọ àwọn òfin mi sílẹ̀ bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ẹni tó bá pa á mọ́ yóò yè nínú rẹ̀. Wọn sì sọ ọjọ́ ìsinmi mi di aláìmọ́ lọ́pọ̀lọ́pọ̀. Nítorí náà, mo sọ pé èmi yóò tú ìbínú gbígbóná mi sórí wọn, èmi yóò sì pa wọ́n run nínú aginjù.
Be ilia da hafoga: i sogea amowane, Nama higale lelesu. Na hamoma: ne sia: i amola Na sema (amo da nowa dunu da nabawane hamosa, ema esalusu iaha) huluane higale fi dagoi. Ilia da Sa: bade eso sema wadela: lesidafa. Na da hafoga: i sogega, ilima ougi bagade se bidi imunusa: , amola ili wadela: lesimusa: momagei galu.
14 Ṣùgbọ́n nítorí orúkọ mi, mo ṣe ohun tí kò ní mú kí orúkọ mi bàjẹ́ lójú àwọn orílẹ̀-èdè tí mo kó wọn jáde.
Be Na da amane hame hamoi. Bai fifi asi gala amo da Na Isala: ili fi Idibidi sogega fisili masa: ne, gadili asunasi, amo ba: i, ilia da Na Dio amoma hame nodosa: besa: le, Na amane hame hamoi.
15 Nítorí náà, mo tún gbọ́wọ́ mi sókè ní ìbúra fún wọn nínú aginjù pé, èmi kì yóò mú wọn dé ilẹ̀ tí mo fi fún wọn—ilẹ̀ tí ó ń sàn fún wàrà àti oyin, ilẹ̀ tí ó lẹ́wà jùlọ láàrín àwọn ilẹ̀ yòókù.
Amo dawa: beba: le, Na da hafoga: i soge ganodini, Na da dilia eda amo soge Na da ilima i dagoi (amo soge da gugui amola nasegagi, baligili noga: idafa) amoga hame oule masunusa: ilegei.
16 Nítorí pé, wọn kọ òfin mi sílẹ̀, wọn kò sì tẹ̀lé àṣẹ mi, wọn sọ ọjọ́ ìsinmi mi dí aláìmọ́. Nítorí pé tọkàntọkàn ni wọn ń tẹ̀lé òrìṣà wọn.
Bai ilia da Na hamoma: ne sia: i hame nabi, amola Na sema fi, amola Sa: bade eso sema wadela: lesi, amola Na fisili, ilia da ogogosu ‘gode’ ilima sia: ne gadomusa: hanai galu.
17 Síbẹ̀síbẹ̀ mo wò wọ́n pẹ̀lú àánú, ń kò sì pa wọ́n run tàbí kí òpin dé bá wọn nínú aginjù.
Be amalalu, Na da ilima bu asigisu. Na da ili hafoga: i sogega medole legemusa: dawa: i bu yolesi.
18 Ṣùgbọ́n mo sọ fún àwọn ọmọ wọn nínú aginjù pé, “Ẹ má ṣe rìn ní ìlànà àwọn baba yín, ẹ má ṣe pa òfin wọn mọ́, ẹ má ṣe bá ara yín jẹ́ pẹ̀lú òrìṣà wọn.
Be amomane, Na da ayeligi amola a: fini ilia gilisisu ganodini sisane amane i, ‘Dilia aowalalia sema hamoi amola ilia hou amoma mae fa: no bobogema. Dilia ledo hamoi ba: sa: besa: le, ilia loboga hamoi ‘gode’ ilima mae nodone sia: ne gadoma.
19 Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín, ẹ tẹ̀lé àṣẹ mi, kí ó sì pa òfin mi mọ́.
Na da dilia Hina Godedafa. Na hamoma: ne sia: i amola Na sema nabawane hamoma.
20 Ẹ ya ọjọ́ ìsinmi mi sí mímọ́ kí ó lè jẹ́ àmì láàrín wa, ki ẹ lè mọ̀ pé èmi ní Olúwa Ọlọ́run yín.”
Sa: bade eso da hadigi eso, amola gousa: su Na dilima hamoi da dawa: digisu ilegesu gala. Amola Na da dilia Hina Godedafa. Amo huluane dilia bu dawa: ma: ne, Sa: bade eso sema noga: le ouligima.
21 “‘Ṣùgbọ́n àwọn ọmọ náà ṣọ̀tẹ̀ sí mi. Wọn kò tẹ̀lé àṣẹ mi, wọn kò sì pa òfin mi mọ́ bí o tilẹ̀ jẹ́ pé ẹni tó bá tẹ̀lé àwọn òfin yìí, yóò yè nínú rẹ̀, wọ́n sì tún sọ ọjọ́ ìsinmi mi di aláìmọ́. Nítorí náà, mo sọ pé èmi yóò tú ìbínú mi lórí wọn, Èmi yóò sì mú kí ìbínú gbígbóná mi wá sórí wọn ni aginjù.
Be amo fifi misi amola da Na higasu. Ilia da Na sema fi amola Na hamoma: ne sia: i (amo da nowa dunu da nabawane hamosea, ema esalusu iaha) amo hame nabi. Ilia da Sa: bade eso sema wadela: lesi. Na da hafoga: i sogega ilima ougi se bidi imunusa: , amola ili huluane medole legemusa: dawa: i galu.
22 Síbẹ̀síbẹ̀ mo dáwọ́ dúró, nítorí orúkọ mi, mo sì ṣe ohun tí kò ní ba orúkọ mi jẹ́ lójú àwọn orílẹ̀-èdè ti mo kó wọn jáde lójú wọn.
Be Na da amane hame hamoi. Bai fifi asi gala amo da Na Isala: ili fi Idibidi sogega fisili masa: ne, gadili asunasi, amo ba: i, ilia da Na Dio amoma hame nodosa: besa: le, Na da amane hame hamoi.
23 Bẹ́ẹ̀ ni pẹ̀lú ọwọ́ ti mo gbé sókè sí wọn, mo búra fún wọn nínú aginjù pé èmi yóò tú wọn ka sì àárín àwọn orílẹ̀-èdè, èmi yóò sì fọ́n wọn káàkiri ilẹ̀ gbogbo,
Amaiba: le, Na da hafoga: i sogega ilima eno ilegei. Na da ili osobo bagade fifi asi gala huluane, amo ganodini afagololesima: ne, dafawane ilegele sia: i.
24 nítorí pé wọn kò pa òfin mi mọ́, wọn sì tún kọ àṣẹ mi sílẹ̀, wọn tún sọ ọjọ́ ìsinmi mi di aláìmọ́. Ojú wọn sì wà ní ara òrìṣà baba wọn.
Ilia da Na sema fiba: le, amola Na hamoma: ne sia: i nabawane hame hamobeba: le, amola Sa: bade eso sema fiba: le, amola ogogosu ‘gode’ (amoma ilia aowalalia da fa: no bobogei) ilima nodone sia: ne gadobeba: le, Na da amane hamoi.
25 Èmi náà sì fi wọn fún ìlànà tí kò dára àti òfin tí wọn kò le e yè nípa rẹ̀;
Amalalu, Na da noga: i hame sema ilima i, amola hamoma: ne sia: i amo da esalusu hame iaha, ilima i.
26 mo jẹ́ kí ó sọ wọn di aláìmọ́ nípa ẹ̀bùn nípa fífi àkọ́bí ọmọ wọn rú ẹbọ sísun, àkọ́bí wọn la iná kọjá, kí èmi sọ wọ́n di ahoro, kí wọn le mọ̀ pé èmi ni Olúwa.’
Ilia da ilila: gobele salasu amoga ledo hamoma: ne, Na da logo doasi. Amola ilia da ilila: magobo mano medole legele, gobele salimusa: , Na da logo doasi. Amo da ilima se ima: ne, amola Na da Hina Godedafa ili dawa: musa: amo olelema: ne, Na da amane hamoi.
27 “Nítorí náà, Ọmọ ènìyàn, sọ fún ilé Israẹli kí ó sì wí fún wọn pé, ‘Èyí ní ohun ti Olúwa Olódùmarè wí, nínú èyí tí baba yín ti sọ̀rọ̀-òdì sí mi, nípa kíkọ̀ mí sílẹ̀.
Wali, dunu egefe! Isala: ili dunuma, Na, Ouligisudafa Hina Gode, Na sia: ilima adosima. Ilia aowalalia da eno agoane Nama gadesu.
28 Nítorí nígbà tí mo mú wọn dé ilẹ̀ náà, tí mo gbé ọwọ́ mi sókè láti fi í fún wọn, nígbà náà ni wọ́n rí olúkúlùkù òkè gíga, àti gbogbo igi bíbò, wọ́n sì rú ẹbọ wọn níbẹ̀, wọ́n sì gbé ìmúnibínú ọrẹ wọ́n kalẹ̀ níbẹ̀; níbẹ̀ pẹ̀lú ni wọ́n ṣe òórùn dídùn wọn, wọ́n sì ta ohun ọrẹ mímu sílẹ̀ níbẹ̀.
Na da soge amo Na da ilima imunusa: ilegei, amoga ili oule misi. Ilia da goumi sedade amola gahe ifa ba: beba: le, huluane amogai gobele salasu hamosu. Ilia da gobele salasu hamobeba: le, amola waini hano ogogosu ‘gode’ ilima imunusa: gaguli misiba: le, Na da ougi bagade ba: i.
29 Nígbà náà ni mo wí fún wọn pé, kí ní ibi gíga tí ẹ̀yin lọ yìí?’” (Orúkọ rẹ̀ ni a sì ń pè ní Bama di òní yìí.)
Na da ilima amane adole ba: i, ‘Amo gadodafa sogebi amoga dili ahoa, ilia bai da adila: ?’ Amaiba: le, ilia da amo sogebi fa: noga ‘Gadodafa Sogebi’ dio sia: sa.
30 “Nítorí náà sọ fún ilé Israẹli pé, ‘Èyí ní ohun tí Olúwa Olódùmarè wí, ṣé o fẹ́ ba ara rẹ jẹ́ bi àwọn baba rẹ ṣe ṣe, tiwọn ń ṣe àgbèrè nípa títẹ̀lé àwọn àwòrán ìríra?
Wali, Isala: ili dunuma, Na, Ouligisudafa Hina Gode, Na sia: be ilima adosima. ‘Dilia abuliba: le, dilia aowalalia ilia wadela: i hou defele, ogogosu ‘gode’ ilima hehenaia fa: no bobogesala: ?
31 Nígbà tí ẹ̀yin bá san ọrẹ yìí, ìrúbọ ọmọkùnrin ọmọ yín, tí ẹ mú ọmọ yin la iná kọjá, ẹ̀yin ń tẹ̀síwájú láti ba ara yín jẹ́ pẹ̀lú àwọn òrìṣà yín títí di òní yìí, ẹ̀yin yóò ha jẹ wádìí lọ́dọ̀ mi, ìwọ ilé Israẹli? Bí mo ti wà láààyè, ní Olúwa Olódùmarè wí, Èmi ki yóò jẹ́ kí ẹ wádìí lọ́dọ̀ mi.
Waha amolawane, dilia da ili defele gobele salasu hamosa. Dilia da dilia mano ogogosu ‘gode’ ilima laluga gobele salabeba: le, dilila: hou ledo hamosa. Abuliba: le dilia Isala: ili dunu da Na hamomu hanai adoleba: la mahabela: ? Na, Ouligisudafa Hina Gode da Fifi Ahoanusu Gode! Amaiba: le, Na da amane dafawane sia: sa. Na da dilia Nama adole ba: su logo hedofamu.
32 “‘Ẹ̀yin wí pé, “Àwa fẹ́ dàbí àwọn orílẹ̀-èdè yòókù, bí àwọn ènìyàn ayé, tó ń bọ igi àti òkúta.” Ṣùgbọ́n ohun ti ẹ ni lọ́kàn kò ní ṣẹ rárá.
Dilia da eno fifi asi gala huluane ilia hou defele hamomusa: hanai gala. Ilia da ifa amola igi amoma nodone sia: ne gadosu hou hamosa. Be Na fi ilia da agoane hamomu da hamedei.
33 Bí mo ti wà láààyè, ní Olúwa Olódùmarè wí, Èmi yóò jẹ ọba lórí yín pẹ̀lú ọwọ́ agbára tí èmi yóò nà jáde pẹ̀lú ìtújáde ìbínú gbígbóná mi.
Na da Ouligisudafa Hina Gode! Amola na da Fifi Ahoanusu Gode esalebeba: le, Na da dafawane dilima sisane iaha. Na da ougiba: le, Na gasa bagade defele, dilima gasa fili ouligimu.
34 Èmi yóò si mú yín jáde kúrò láàrín àwọn ènìyàn, èmi yóò sì ṣà yín jọ láàrín àwọn orílẹ̀-èdè tí a fọ́n yín sí pẹ̀lú ọwọ́ agbára àti apá nínà tí èmi yóò nà jáde àti pẹ̀lú ìtújáde ìbínú gbígbóná ni.
Na da dili fifi asi gala enoenoi amoga afagogoi dagoi. Be Na da dilia sogega dili buhagima: ne gagadosea, Na da Na gasa bagade hou amola Na ougi hou dilima olelemu.
35 Èmi yóò si mú yín wá sí aginjù àwọn orílẹ̀-èdè, níbẹ̀ ni ojúkójú ni èmi yóò ṣe ìdájọ́ lé e yín lórí.
Na da dili fifi asi gala eno amoga oule asili, dilia odagia ba: ma: ne se imunusa: fofada: mu. (Amogai esalea, dilia da amo fifi asi gala ‘Hafoga: i Soge Fifi Asi Gagai’ defele ba: mu).
36 Bí mo ṣe ṣe ìdájọ́ àwọn baba yín nínú aginjù nílẹ̀ Ejibiti, bẹ́ẹ̀ ni èmi yóò ṣe ìdájọ́ yín ní Olúwa Olódùmarè wí.
Na da Sainai hafoga: i sogega dilia aowalalia ilima fofada: nanu, se iasu. Amo defele, Na da dilima fofada: mu,” Ouligisudafa Hina Gode da amane sia: sa.
37 Èmi yóò kíyèsi i yín bí mo ti mú un yín kọjá lábẹ́ ọ̀pá, èmi yóò sì mú yín wá sí abẹ́ ìdè májẹ̀mú.
“Na da dili gasawane ouligimu amola dilia Na gousa: su nabawane hamoma: mu.
38 Èmi yóò si ṣa àwọn ọlọ̀tẹ̀ kúrò láàrín yín, àti àwọn o lù re òfin kọjá, èmi yóò mu wọn jáde kúrò ni ilẹ̀ tiwọn gbé ṣe àtìpó, wọn ki yóò si wọ ilẹ̀ Israẹli. Nígbà náà ní ẹ̀yin yóò mọ̀ pé, èmi ní Olúwa.
Nowa da lelelewane wadela: i hou hamosea, Na da dilia mugululi misi gilisisu amoga fadegale fasimu. Ilia wali esalebe soge amoga Na da fadegamu. Be ilia da Isala: ili sogega hame buhagimu. Amasea, Na da Hina Gode, amo dilia da dawa: mu.”
39 “‘Ní tí ẹ̀yin, ilé Israẹli, èyí ni ohun tí Olúwa Olódùmarè wí: Kí olúkúlùkù yín lọ máa sìn òrìṣà rẹ̀, ṣùgbọ́n lẹ́yìn èyí, ẹ̀yin yóò gbọ́ tèmi, ẹ̀yin kò sí ní i bá orúkọ mímọ́ mi jẹ́ pẹ̀lú ọrẹ àti àwọn òrìṣà yín mọ́.
Ouligisudafa Hina Gode da amane sia: i, “Defea! Dilia Isala: ili dunu huluane! Dilia hanaiga hamoma! Dilia ogogosu ‘gode’ ilima fa: no bobogema! Be Na da dilima sisane sia: sa. Dilia fa: no dilia hanai yolesili, Nama nabawane hawa: hamonanebe ba: mu. Amola dilia da ogogosu ‘gode’ ilima iasu yolesimuba: le, dilia da Na Dio bu hame lasogolalumu.
40 Nítorí lórí òkè mímọ́ mi, lórí òkè gíga Israẹli, ni Olúwa Olódùmarè wí, níbẹ̀ ni ilẹ̀ náà ní gbogbo ilé Israẹli yóò sìn mí; èmi yóò sì tẹ́wọ́ gba wọ́n níbẹ̀. Níbẹ̀ èmi yóò béèrè ọrẹ àti ẹ̀bùn nínú àkọ́so yín pẹ̀lú gbogbo ẹbọ mímọ́ yín.
Isala: ili soge ganodini, Na hadigi gadodafa goumi amo da: iya, Isala: ili dunu dilia da Nama nodone sia: ne gadomu. Na da dilima hahawane ba: mu. Amasea, Na da dilia gobele salasu liligi amola hahawane hadigi iasu amo huluane Nama gaguli misa: ne sia: mu.
41 Èmi yóò tẹ́wọ́ gbà yín gẹ́gẹ́ bí tùràrí olóòórùn dídùn nígbà tí mo ba mú yín jáde láàrín àwọn orílẹ̀-èdè tí a fọ́n yín ká sí, èmi yóò sì fi ìwà mímọ́ mi hàn láàrín yín lójú àwọn orílẹ̀-èdè.
Na da dili fifi asi gala enoenoi amo ganodini esaloma: ne, amoga afagogoi dagoi. Be Na da dilia sogega dili buhagima: ne gagadosea, amo fa: no Na da liligi dilia gobele salimusa: gaguli maha, amo nodone lamu. Amasea, fifi asi gala huluane da Na da hadigidafa ba: mu.
42 Nígbà náà ni ẹ o mọ̀ pé èmi ní Olúwa, nígbà tí mo bá mú yín wa sí ilẹ̀ Israẹli; sí ilẹ̀ tí mo gbọ́wọ́ mí sókè nínú ẹ̀jẹ́ láti fún àwọn baba yín.
Na da Isala: ili soge amo dilia aowalalima imunusa: ilegele sia: i. Na da dili amogawi bu oule masea, dilia da Na da Hina Gode dawa: mu.
43 Níbẹ̀ ni ẹ ó wa rántí ìwà àti gbogbo ìṣesí yín, èyí tí ẹ̀yin fi sọ ara yín di aláìmọ́, ẹ̀yin yóò sì kórìíra ara yín fún gbogbo ibi tí ẹ̀yin ti ṣe.
Amasea, dilia da wadela: i hou hamoi amola dilia hou ledo hamoi, amo dilia da bu gogosiane dawa: mu. Dilia da dilia musa: wadela: i hou dawa: beba: le, dilila: hou higamu.
44 Nígbà náà ní ẹ̀yin yóò mọ̀ pé, Èmi ni Olúwa, nígbà tí mo bá hùwà sí yín nítorí orúkọ mi ni, tí ń kò hùwà sí yín gẹ́gẹ́ bí ọ̀nà ibi àti ìwà ìríra yín. Ẹ̀yin ilé Israẹli, ni Olúwa Olódùmarè wí.’”
Amola Na da Na hadigi hou gaga: musa: hamosea, dilia Isala: ili dunu da Na da Hina Gode dawa: mu. Bai Na da dilia wadela: idafa hou hamoi defele, dilima se hame iaha.” Ouligisudafa Hina Gode da sia: i dagoi.
45 Ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá:
Hina Gode da nama amane sia: i, “Dunu egefe!
46 “Ọmọ ènìyàn, dojúkọ ìhà gúúsù; wàásù lòdì sí gúúsù kí ìwọ sì sọtẹ́lẹ̀ sí igbó ilẹ̀ gúúsù.
Ga (south) ba: le gale, amo soge amola iwila amoma fofada: ma.
47 Sọ fún igbó ìhà gúúsù pé: ‘Gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa. Èyí ní ohun tí Olúwa Olódùmarè wí: Kíyèsi í, èmi yóò dá iná kan nínú rẹ̀, yóò sì jó olúkúlùkù igi tútù nínú rẹ̀, àti olúkúlùkù igi gbígbẹ. Jíjò ọwọ́ iná náà ní kí yóò ṣé é pa, àti gbogbo ojú láti gúúsù dé àríwá ni a ó sun nínú rẹ̀.
Ga (south) iwila amoma e da Ouligisudafa Hina Gode Ea sia: nabima: ne amane sia: ma, ‘Ba: ma! Na da lalu didisa. Amo lalu da dia ifa huluane, gahe amola bioi, huluane nemu. Ha: ba: domu da hamedei ba: mu. E da gadili nene ahoasea, dunu huluane da lalu sawa: ga fane dogolomu.
48 Gbogbo ènìyàn yóò sì mọ̀ pé, Èmi Olúwa ni ó dá a, a kì yóò sì le è pa á.’”
Ilia huluane da Na, Hina Gode, Ni fawane da lalu ulagisiba: le, enoga ha: ba: domu hamedei ba: mu.’”
49 Nígbà náà ni mo wí pé, “Háà! Olúwa Olódùmarè! Wọn ń wí fún mi pé, ‘Kì í wa ṣe pé òwe lo ń pa bí?’”
Be na da Godema gagabole sia: i, “Ouligisudafa Hina Gode! Nama agoane hamoma: ne, mae sia: ma! Dunu huluane da na da fedege idinamasu sia: fawane sia: sa, amo ilia hihini sia: daha.”