< Ezekiel 19 >

1 “Kọ orin ọ̀fọ̀ nítorí àwọn ọmọ-aládé Israẹli
E LAWE hoi oe i ke kanikau no na'lii o ka Iseraela,
2 wí pé: “‘Èwo nínú abo kìnnìún ni ìyá rẹ̀ ní àárín àwọn kìnnìún yòókù? Ó sùn ní àárín àwọn ọ̀dọ́ kìnnìún ó sì ń tọ́jú àwọn ọmọ rẹ̀.
A e olelo aku, Heaha kou makuwahine? He liona wahine. Ua moe ia ilalo me na liona, ua hanai oia i kana mau keiki liona iwaena o na liona opiopio.
3 Ó sì tọ́ ọ̀kan nínú àwọn ọmọ rẹ̀ dàgbà, ó sì di kìnnìún tó ní agbára, ó kọ́ ọ láti ṣọdẹ, ó sì ń pa àwọn ènìyàn jẹ.
Ua alakai oia i kekahi o kana mau keiki liona: lilo ia i liona opiopio, ao iho la ia e hopu i ka ai kaili, ai iho la ia i kanaka.
4 Àwọn orílẹ̀-èdè gbọ́ nípa rẹ̀, wọ́n sì fi ẹ̀wọ̀n mú un nínú iho wọn. Wọn fi ẹ̀wọ̀n mu nu lọ sí ilẹ̀ Ejibiti.
Lohe hoi na lahuikanaka nona, a ua hopuia oia iloko o ko lakou lua; lawe ae la lakou ia ia me na kaulahao i ka aina o Aigupita.
5 “‘Nígbà tí abo kìnnìún yìí rí pé ìrètí rẹ̀ sì jásí asán, ó mú ọmọ rẹ̀ mìíràn ó sì tún tọ́ ọ dàgbà di kìnnìún tó ní agbára.
A ike iho la ia makuwahine ua kali ia, a lilo kona mea i manaolana ai, alaila lawe oia i kekahi o kana mau keiki liona, a hoolilo ia ia i liona opiopio.
6 Ó sì ń rìn káàkiri láàrín àwọn kìnnìún nítorí pé ó ti lágbára, o kọ ọdẹ ṣíṣe, ó sì pa àwọn ènìyàn.
Holoholo ae la ia io ia nei iwaena o na liona, lilo oia i liona opiopio; ao iho la ia e hopu i ka ai kaili, a ai iho la i kanaka.
7 Ó sì wó odi wọn palẹ̀ ó sì sọ àwọn ìlú wọn di ahoro. Ilẹ̀ náà àti àwọn olùgbé ibẹ̀ sì wà ní ìpayà nítorí bíbú ramúramù rẹ̀.
Ike iho la ia i ko lakou mau hale alii neoneo, hooneoneo ae la ia i ko lakou mau kulanakauhale; a neoneo ka aina a me kona mea i piha ai, no ka halulu o kona uwo ana.
8 Nígbà náà ni àwọn orílẹ̀-èdè dìde sí i, àwọn tó yìí ká láti ìgbèríko wá. Wọn dẹ àwọ̀n wọn fún un, wọn sì mú nínú ihò wọn.
Alaila hooku e na lahuikanaka ia ia a puni mailoko mai o na aina, a hohola i ko lakou upena maluna ona, a ua hopuia oia iloko o ka lakou lua.
9 Wọn fi ìwọ̀ gbé e sínú àgò, wọn mú un lọ sí ọ̀dọ̀ ọba Babeli, wọn fi sínú ìhámọ́, a kò sì gbọ́ bíbú rẹ̀ mọ́ lórí òkè Israẹli.
Hoopaahao ae la lakou ia ia me na kaulahao, a lawe hoi ia ia i ke alii o Babulona: alakai ae la ia ia iloko o na wahi e paa ai, i ole e lohe hou ia kona leo maluna o na mauna o ka Iseraela.
10 “‘Ìyá rẹ dàbí àjàrà nínú ọgbà àjàrà rẹ̀; tí á gbìn sí etí odò ó, kún fún èso, ó sì kún fún ẹ̀ka nítorí ọ̀pọ̀lọpọ̀ omi.
O kou makuwahine, ua like ia me ke kumu waina iloko o kou koko, i kanuia ma na wai; paapu ia i ka hua a me na lala he nui, no ka nui o na wai.
11 Àwọn ẹ̀ka rẹ̀ lágbára tó láti fi ṣe ọ̀pá àṣẹ ìjòyè, ó ga sókè láàrín ewé rẹ̀, gíga rẹ̀ hàn jáde láàrín ọ̀pọ̀lọpọ̀ ẹ̀ka rẹ̀.
He mau kookoo paa kona i mau hoailonamoi no ka poe e alii ana, a ua hookiekieia kona kino mawaena o na lala paapu: ua ikeia hoi ia i kona kiekie ana ma ka lehulehu o kona poe lala.
12 Ṣùgbọ́n ó fà á tu ní ìrunú, á sì wọ́ ọ lulẹ̀, afẹ́fẹ́ láti ìlà-oòrùn sì gbé èso rẹ̀, ọ̀pá líle rẹ̀ ti ṣẹ́, ó sì rọ iná sì jó wọn run.
Aka, uhukiia'e la ia me ka ukiuki; kiolaia iho la ia ilalo i ka lepo: hoomaloo ae la ka makani hikina i kona mau hua; uhaiia iho la kona mau kookoo paa; a hoopau iho la ke ahi ia lakou.
13 Báyìí, a tún ún gbìn sínú aṣálẹ̀ ni ilẹ̀ gbígbẹ àti ilẹ̀ tó ń pòǹgbẹ omi.
Ua kanuia'e nei ia ma ka waonahele, ma ka aina maloo a me ka makewai.
14 Iná sì jáde láti ọ̀kan lára ẹ̀ka rẹ̀ ó sì pa ẹ̀ka àti èso rẹ̀ run, dé bi pé kò sí ẹ̀ka tó lágbára lórí rẹ̀ mọ́; èyí to ṣe fi ṣe ọ̀pá fún olórí mọ́.’ Èyí ni orin ọ̀fọ̀ a o sì máa lo bí orin ọ̀fọ̀.”
Ua puka ae la ke ahi mailoko ae o kekahi kookoo o kona mau lala; ua hoopau ae la ia i kona hua, i ole hoi ona kookoo paa i hoailonamoi e alii ai. He kanikau keia, a he mea ia e kanikau ai.

< Ezekiel 19 >