< Ezekiel 17 >

1 Ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ ní wá wí pé:
Ra Anumzamo'a amanage huno nasmi'ne,
2 “Ọmọ ènìyàn pa àlọ́ kan, sì pa òwe kan fún ilé Israẹli.
Vahe'mofo mofavremoka, fronka kema kasamisua nanekea Israeli vahera zamasmio.
3 Sọ fún wọn pé, ‘Báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí, idì ńlá kan tó ní apá títóbi àti ìyẹ́ gígùn tó kún fún àwọ̀ oríṣìíríṣìí wa si Lebanoni, ó sì mu ẹ̀ka igi kedari tó ga jùlọ,
Amanage hunka zamasamio, Mikozama Kegava Hu'nea Ra Anumzamo'a amanage hie hunka zamasamio, mago ra tumpamofona ra agekonarare hunte'negeno, azokamo'a za'za huno ruzahu ruzahu avonkrenakre huno konarari'amo'a agatere'nea tumpamo hareno Lebanoni zafafi vuno sida zafamofo amumpa ome nekafrie.
4 ó gé ọ̀mùnú orí ẹ̀ka yìí kúrò, ó mú un lọ sí ilẹ̀ oníṣòwò, ó sì gbìn ín sí ìlú àwọn oníṣòwò.
Hagi ana sida zafa amumpama akafriteno'a erino keonke'zama zagore'ma netraza vahe'mokizmi mopafi vuno, ana vahe'mokizmi rankumapi ome kri'ne.
5 “‘Ó mú lára irúgbìn ilẹ̀ náà, ó gbìn ín sí ilẹ̀ ọlọ́ràá, lẹ́gbẹ̀ẹ́ ọ̀pọ̀lọpọ̀ omi, ó gbìn ín bí igi wílóò.
Hagi ana'ma huteno'a ana tumpamo'a mago'a avimzana Israeli mopafintira erino vuno, knare huno tima'ane mopafi ome hankre'ne. Hagi anama hankre'neana, rama'a ti me'nefi wilo zafa hankreankna huno ome hankre'ne.
6 Ó dàgbà, ó sì di àjàrà tó kúrú ṣùgbọ́n to bolẹ̀. Àwọn ẹ̀ka rẹ̀ kọjú sí i, gbòǹgbò rẹ̀ sì dúró lábẹ́ rẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni ó di àjàrà, ó sì mu ẹ̀ka àti ewé jáde.
Ana avimzamo'a hageno waini zafa sampreno, mopafi rafu'nare'ne. Hagi ana azankunamo'za eri arufagagi'za ana tumpama mani'nerega zamavugosa hunente'za, agata hage'za azankunara omere emere hu'naze.
7 “‘Ṣùgbọ́n ẹyẹ idì ńlá mìíràn tún wá, tó ní apá títóbi pẹ̀lú ìyẹ́ púpọ̀. Gbòǹgbò àjàrà náà sì ta lọ sọ́dọ̀ rẹ̀ láti orí ilẹ̀ tí wọn gbìn ín sí, ó wá pẹ̀ka lọ sọ́dọ̀ rẹ̀ kí ó le fún un ni omi.
Hagi ete mago ra tumpamofona anahukna huno ra agekona hunte'negeno, rama'a azoka me'ne. Hagi ana waini zafamofo arafu'naramine azankunatmimo'za ana tumpamo'a ti erino egahie hu'za zamagesa nentahi'za, rukrahe hu'za ana tumpama mani'nea kaziga zamavugosa hunte'naze.
8 Orí ilẹ̀ tó dára lẹ́gbẹ̀ẹ́ ọ̀pọ̀lọpọ̀ omi ni a gbìn ín sí, kí ó bá à le pẹ̀ka, kò sì so èso, ó sì wá di igi àjàrà tó lọ́lá púpọ̀.’
Hianagi ana waini zafama hankre'neana rama'a azankuna reno rama'a ragarami renenteno, knare waini zafa fore hinogu knare mopafi tinkenare hankre'ne.
9 “Sọ fún wọn pé, ‘Ohun tí Olúwa Olódùmarè wí nìyí, yóò wá gbilẹ̀ bí? A kò wá ní i wú gbòǹgbò rẹ̀, ki a si gé èso rẹ̀ kúrò kí ó bá à le rọ? Gbogbo ewé rẹ̀ tó ṣẹ̀ṣẹ̀ yọ ni yóò rẹ̀. Kò sì nígbà agbára tàbí ènìyàn púpọ̀ láti fà gbòǹgbò rẹ̀ tu.
Hanki Ra Anumzana miko'zama kegavama hu'nea Anumzamo'a amanage hie hunka zamasamio, ana wainimo'a knare huno hageno marerino raga reontegahianki, Nagra rafuna'a eri vatitrenugeno raga reontenigeno a'ninamo'a hariri hanigeno osaparegahie. Nagra amuhoa osu'na fru hu'na eri vati tregahuankino, mago hankave vahe'mo'a eme vati otresigeno rama'a sondia vahe'mo'zanena eme vati otregahaze.
10 Bí a tilẹ̀ tún un gbìn, yóò wa gbilẹ̀ bí? Kò wá ní i rọ pátápátá nígbà ti afẹ́fẹ́ láti ìlà-oòrùn bá kọlù ú. Gbogbo ewé rẹ̀ yóò rẹ̀ lórí ilẹ̀ tó ti dàgbà?’”
Hagi ana wainima ete vatinoma krisiana, knare huno hagegahifi ko? Ifi zage hanati kazigati'ma esia zaho'mo eme eri hagage hugahio? I'o, anama knare'ma huno hageno mareri'nea mopafi mani'neno hagage hugahie.
11 Nígbà náà, ni ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mi wá pé:
Hagi Ra Anumzamo'a amanage huno nasmi'ne,
12 “Sọ fún ọlọ̀tẹ̀ ilé yìí, ‘Ǹjẹ́ ẹ mọ ìtumọ̀ àwọn nǹkan wọ̀nyí?’ Sọ fún wọn: ‘Ọba Babeli wá sí Jerusalẹmu, ó sì kó ọba àti àwọn ìjòyè ọmọ-aládé ibẹ̀ lọ sí Babeli lọ́dọ̀ rẹ̀.
Keontahi Israeli vahera amanage hunka zamasmio, Tamagra tumpamofo fronka kemofo agafa'a antahi ani' hu'nazafi? Babiloni kumate kini ne'mo'a Jerusalemi kumate eno, kini ne'ene ugagota kva vahe'araminena zamavareno Babiloni vu'ne hunka zamasamio.
13 Lẹ́yìn èyí, ó bá ọ̀kan nínú ọmọ ọba dá májẹ̀mú, ó mú un ìbúra, ó tún kó àwọn alágbára ilẹ̀ náà lọ.
Hagi Juda kva vahe'mofo mofavre'ramimpinti mago ne' avreno ana ne'ene huhagerafi huvempage nehuno, agri agoragama mani'neno maka kema haniama antahimisigura huvempage hu'ne. Ana nehuno ana mopafima ugagotama hu'naza kva vahetmina zamavareno Babiloni kumate vu'ne.
14 Kí ìjọba ilẹ̀ náà le rẹ ilẹ̀, kí ó má lè gbé ara rẹ̀ sókè, kí ó lè dúró nípa pípa májẹ̀mú rẹ̀ mọ́.
Hagi e'inama hu'neana Israeli vahe'mo'za hanaveti'za hara huonte'za, agri agorga mani'neza agri kema nevaririza mopazmire'ma manisagu huvempa kea hu'naze.
15 Ṣùgbọ́n ọba ṣọ̀tẹ̀ sí i nípa ríran àwọn ikọ̀ rẹ̀ lọ sí Ejibiti, kí wọn bá à lè fún un ni ẹṣin àti àwọn ọmọ-ogun púpọ̀. Yóò ha ṣe àṣeyọrí? Ṣe ẹni tó ṣe irú nǹkan yìí yóò sì bọ́ níbẹ̀? Yóò ha dalẹ̀ tán kí ó sì bọ́ níbẹ̀ bí?
Hianagi Juda kini ne'mo'a Babiloni kini nera ha' arenenteno, ha'ma eme aza huza hanagu rama'a sondia vahetamine hosi afutaminena Isipi kumateti ome zamavarenka eno huno agri agi'ma erino Isipima unemania eri'za ne'a hunte'ne. Hagi ana antahintahi'amo'a ome knare hugahifi? E'i ana'ma hania zamo'a Babiloni kini ne'mofo azampintira rugraru vazigahifi? Nanekema huvempa huke huhagerafina'a kea ruhantgino atreno fregahifi?
16 “‘Bí mo ti wà láààyè ni Olúwa Olódùmarè wí, òun yóò kú ní Babeli, ní ilẹ̀ ọba tó fi sórí oyè, ìbúra ẹni tí ó kẹ́gàn àti májẹ̀mú ẹni tí ó dà.
Kasefa hu'na mani'noa Ra Anumzana Nagra hankavenentake Anumzamo'na huankino, tamage huno Juda kini ne'mo'a kinima azeri otigekema kema anakike huhagerafi huvempa kema hu'na'a kini ne'mofo kumapi Babiloni frigahie.
17 Farao pẹ̀lú àwọn ọmọ-ogun àti àjọ ńlá rẹ̀ kò ní lè ṣe ìrànwọ́ fún un lójú ogun. Nígbà tí wọ́n bá pa bùdó ogun tì í, tí wọ́n sì mọ odi láti pa ọ̀pọ̀ ènìyàn.
Hagi Babiloni sondia vahe'mo'ma Juda vahe kuma'ma avazagi kagiza mani'neza ha'ma hanaza zama kuma keginamofo megi'ama mopama ante hihi hu'za mani'neza rama'a vahe'ma zamahe fri'zama nehanageno'a, Isipi kini ne' Fero'a hankave sondia vahe'a zamavareno egahianagi, zamaza osugahaze.
18 Nítorí pé ó kẹ́gàn ìbúra nípa dída májẹ̀mú, àti pé ó juwọ́ sílẹ̀ nínú ṣíṣe ìlérí, kì yóò bọ níbẹ̀ pẹ̀lú gbogbo àwọn nǹkan tí ó ṣe yìí.
Hagi Juda kini ne'mo'a kema ananekino huvempama hu'nea kea ruha'nentagino Babiloni kini ne'enema huhagerafi'nea kea ovariri'ne. Na'ankure agra azana ante nagamuteno huvempa huteno, ana kea ovariri'neankino ana knazana agate'oregahie.
19 “‘Nítorí náà Olúwa Olódùmarè wí pé, bí mo ti wà láààyè, Èmi yóò mú ẹ̀san ẹ̀jẹ́ mi tó kẹ́gàn àti májẹ̀mú mi tó dà wa sórí rẹ̀.
E'ina hu'negu miko'zama kegava hu'noa Ra Anumzamo'na huankino, Nagri nagifima huhagerafi huvempa kema hu'neana ruhanentagino ovariri'neankina, Nagra ana nona'a knazana amigahue.
20 Èmi yóò ta àwọ̀n mi sórí rẹ̀, yóò sì bọ sínú okùn mi, Èmi yóò mú ọ lọ Babeli láti ṣe ìdájọ́ ìwà ọ̀dàlẹ̀ tó hù sí mi.
Nagra kukoni'a eri atranenkeno ana kukomo azerinige'na avre'na Babiloni kumate knazana ome amigahue. Na'ankure huvempama hu'nea kea rutagreno, Nagritera mani fatgo hunora omani'ne.
21 Gbogbo ìgbèkùn àti ọ̀wọ́ ọmọ-ogun rẹ̀ ni yóò kú pẹ̀lú idà, èmi yóò sì fọn àwọn ìyókù ká sínú afẹ́fẹ́ káàkiri. Nígbà náà ni yóò mọ̀ pé, “Èmi Olúwa ni ó ti sọ̀rọ̀.”
Hagi hankave sondia vahe'aramina bainati kazinteti zamahe hana hanige'za, manisaza sondia vahe'mo'za maka kaziga atre'za panani hu'za fresagenka, Ra Anumzamo hu'nea kante amanara hie hunka kenka antahinka hugahane.
22 “‘Báyìí ní Olúwa Olódùmarè wí, Èmi fúnra mi yóò mú ọ̀kan lára ẹ̀ka tí ó ga jùlọ lórí igi kedari gíga, tí èmi yóò sì gbìn ín, èmi yóò sì gé ọ̀mùnú tí ó ṣẹ̀ṣẹ̀ yọ láti òkè, èmi yóò sì gbìn ín sórí òkè tó ga tó sì lókìkí.
Hagi Mika'zama Kegava Hu'nea Ra Anumzamo'a amanage hu'ne, Nagra zaza sida zafamofo amumpa'a akafri'na, Israeli mopafima za'za huno mareri agatere'nea agonafi ome krigahue.
23 Ní ibi gíga òkè Israẹli ni èmi yóò gbìn ín sí; yóò pẹ̀ka, yóò sì so èso, yóò wa di igi kedari tí ó lọ́lá. Oríṣìíríṣìí ẹyẹ yóò sì fi òjìji abẹ ẹ̀ka rẹ ṣe ibùgbé; wọn yóò ṣe ibùgbé si abẹ́ òjìji ẹ̀ka rẹ̀.
Hianagi Israeli mopafima za'za huno mareri agatere'nesia agonafi ome krisugeno, hageno ome rahuno azankunatamina vuno eno huno ragaramina renenteno marerisa zafa fore hanigeno, agigu agigu namaramimo'za e'za ana sida zafa tonapinka nona eme ki'za manigahaze.
24 Gbogbo igi inú oko yóò mọ̀ pé, Èmi Olúwa ni ó mú igi gíga walẹ̀, tí mo sì mú kúkúrú ga sókè, tí mo mu igi tútù gbẹ, tí mo sì mú igi gbígbẹ rúwé. “‘Èmi Olúwa ni ó sọ bẹ́ẹ̀, Èmi yóò sì ṣe e.’”
Hagi zaza zafaramina eri atupa nehu'na, atupa zafaramina eri za'za nehu'na, kasefa zafaramina eri hagage nehu'na, hagage zafaramina eri kasefa hanenkeno kasefa huno hageno marerinke'za, Nagrikura Ra Anumza mani'ne hu'za zafaramimo'za ke'za antahi'za hugahaze. Nagra Ra Anumzamo'na huanki'na ana zana hugahue.

< Ezekiel 17 >