< Ezekiel 15 >

1 Ọ̀rọ̀ Olúwa sì tọ̀ mí wá wí pé:
I puta mai ano te kupu a Ihowa ki ahau, i mea,
2 “Ọmọ ènìyàn, báwo ni igi àjàrà ṣe dára ju igi mìíràn lọ tàbí jù ẹ̀ka àjàrà tó wà láàrín igi yòókù nínú igbó?
E te tama a te tangata, he aha te nuinga ake o te waina i nga rakau katoa, o te manga waina i roto i nga rakau o te ngahere?
3 Ǹjẹ́ a wa lè mú igi lára rẹ̀ ṣe nǹkan tí ó wúlò bí? Tàbí kí ènìyàn fi ṣe èèkàn tí yóò fi nǹkan kọ́?
E tangohia mai ranei tetahi wahi o reira, hei mahinga i tetahi mahi? e tangohia ranei tetahi titi i reira hei whakairi mo tetahi mea?
4 Lẹ́yìn èyí, ṣe a jù ú sínú iná gẹ́gẹ́ bí epo ìdáná, gbogbo igun rẹ̀ jóná pẹ̀lú àárín rẹ, ṣé o wà le wúlò fún nǹkan kan mọ́?
Nana, e maka ana ki te ahi hei wahie; pau ake i te ahi ona pito e rua, wera iho a waenganui; he pai ranei mo tetahi mahi?
5 Tí kò bá wúlò fún nǹkan kan nígbà tó wà lódidi, báwo ni yóò ṣe wá wúlò nígbà tí iná ti jó o, tó sì dúdú nítorí èéfín?
Nana, i tona toitutanga, kihai i pai mo tetahi mahi; katahi ka he rawa mo tetahi mahi a muri ake nei, i te mea ka kaia nei e te ahi, a ka wera?
6 “Nítorí náà, báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí, bí mo ṣe sọ igi àjàrà tó wà láàrín àwọn igi inú igbó yòókù di igi ìdáná, bẹ́ẹ̀ ni Èmi yóò ṣe ṣe gbogbo ènìyàn tó ń gbé Jerusalẹmu.
Mo reira ko te kupu tenei a te Ariki, a Ihowa, Ka rite ki taua rakau, ki te waina i roto i nga rakau o te ngahere, i tukua ra e ahau ki te ahi hei wahie, ka pera taku tukunga atu i nga tangata o Hiruharama.
7 Èmi yóò dojúkọ wọ́n. Bó tilẹ̀ jẹ́ pé wọn ti jáde kúrò nínú iná kan, síbẹ̀ iná mìíràn yóò pàpà jó wọn. Nígbà tí mo bá sì dojúkọ wọ́n, ẹ̀yin yóò sì mọ̀ pé, Èmi ni Olúwa.
Ka u atu ano toku mata hei he mo ratou. Ka puta mai ratou i te ahi, otiia ma te ahi ano ratou e kai: a ka mohio koutou ko Ihowa ahau, ina u atu toku mata ki te he mo ratou.
8 Èmi yóò sọ ilé náà di ahoro nítorí ìwà àìṣòótọ́ wọn, ni Olúwa Olódùmarè wí.”
Ka meinga ano e ahau te whenua hei ururua mo te he i he ai ratou, e ai ta te Ariki, ta Ihowa.

< Ezekiel 15 >