< Ezekiel 14 >

1 Díẹ̀ nínú àwọn àgbàgbà Israẹli wá sọ́dọ̀ mi, wọ́n sì jókòó níwájú mi.
Atunci au venit unii dintre bătrânii lui Israel la mine și au șezut înaintea mea.
2 Nígbà náà ni ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá,
Și cuvântul DOMNULUI a venit la mine, spunând:
3 “Ọmọ ènìyàn, àwọn ọkùnrin wọ̀nyí ti gbé òrìṣà kalẹ̀ sínú ọkàn wọn, wọ́n sì gbé àwọn ohun tó lè mú wọn ṣubú sínú ẹ̀ṣẹ̀ síwájú wọn; Èmi yóò ha jẹ́ kí wọ́n béèrè lọ́wọ́ mi rárá bí?
Fiu al omului, acești oameni și-au înălțat idolii în inima lor și au pus piatra de poticnire a nelegiuirii lor înaintea feței lor: să fiu eu cumva luat la întrebări de ei?
4 Nítorí náà, sọ fún wọn pé, ‘Báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí: Bí ẹnikẹ́ni ní ilé Israẹli tó gbé òrìṣà sí ọkàn rẹ̀, tó tún gbé ohun ìkọ̀sẹ̀ síwájú rẹ̀, tí ó sì wá sọ́dọ̀ wòlíì, Èmi Olúwa fúnra mi ni yóò dá ẹni tí ó wa lóhùn gẹ́gẹ́ bí ìwà ìbọ̀rìṣà rẹ.
De aceea vorbește-le și spune-le: Astfel spune Domnul DUMNEZEU: Fiecare om din casa lui Israel care își înalță idolii săi în inima sa și pune piatra de poticnire a nelegiuirii lui înaintea feței lui și vine la profet; eu, DOMNUL, îi voi răspunde, celui care vine, conform cu mulțimea idolilor săi;
5 Èmi yóò ṣe èyí láti gba ọkàn àwọn ará Israẹli tó ti tẹ̀lé òrìṣà wọn lọ padà sí ọ̀dọ̀ mi.’
Ca să prind casa lui Israel în propria lor inimă, căci toți s-au înstrăinat de mine prin idolii lor.
6 “Nítorí náà sọ fún ilé Israẹli, ‘Èyí ni ohun tí Olúwa Olódùmarè wí: Ẹ ronúpìwàdà! Ẹ yípadà kúrò lọ́dọ̀ òrìṣà yín, kí ẹ̀yin sì kọ gbogbo ìwà ìríra yín sílẹ̀!
De aceea spune casei lui Israel: Astfel spune Domnul DUMNEZEU: Pocăiți-vă și întoarceți-[vă] de la idolii voștri; și întoarceți-vă fețele de la toate urâciunile voastre.
7 “‘Bí ẹnikẹ́ni ní ilé Israẹli tàbí àlejò tó ń gbé ní ilẹ̀ Israẹli, bá ya ara rẹ̀ kúrò lọ́dọ̀ mi, tó gbé òrìṣà rẹ̀ sí ọkàn rẹ̀, tó tún gbé ohun tó mú ni ṣubú sínú ẹ̀ṣẹ̀ síwájú rẹ, lẹ́yìn èyí tó tún lọ sọ́dọ̀ wòlíì láti béèrè nǹkan lọ́wọ́ mi! Èmi Olúwa fúnra ara mi ní èmi yóò dá a lóhùn.
Căci fiecare om din casa lui Israel, sau dintre străinii care locuiesc temporar în Israel, care se îndepărtează de mine și își înalță idolii săi în inima sa și pune piatra de poticnire a nelegiuirii lui înaintea feței lui și vine la profet pentru a-l întreba referitor la mine; eu, DOMNUL, singur îi voi răspunde;
8 Èmi yóò lòdì si irú ọkùnrin bẹ́ẹ̀ lọ́nà òdì, Èmi yóò sì fi i ṣe àmì àti òwe. Èmi yóò sì gé e kúrò láàrín àwọn ènìyàn mi. Nígbà náà, ẹ̀yin yóò mọ̀ pé èmi ni Olúwa.
Și îmi voi îndrepta fața împotriva acelui om și îl voi face un semn și un proverb și îl voi stârpi din mijlocul poporului meu; și veți cunoaște că eu [sunt] DOMNUL.
9 “‘Bí wọ́n bá sì tan wòlíì náà láti sọtẹ́lẹ̀, Èmi Olúwa ló tan wòlíì náà, Èmi yóò nawọ́ sí i, èmi yóò sì pa á run kúrò láàrín àwọn ènìyàn mi Israẹli.
Și dacă profetul este înșelat când a vorbit un cuvânt, eu, DOMNUL, am înșelat pe acel profet și îmi voi întinde mâna asupra lui și îl voi nimici din mijlocul poporului meu Israel.
10 Wọn yóò ru ẹ̀bi ẹ̀ṣẹ̀ wọn—ìjìyà kan náà là ó fún wòlíì àti ẹni tó lọ béèrè lọ́dọ̀ rẹ̀.
Și ei vor purta pedeapsa nelegiuirii lor; pedeapsa profetului va fi chiar ca pedeapsa celui care [îl] caută;
11 Kí ilé Israẹli má ba à ṣáko kúrò lọ́dọ̀ mi mọ, kí wọ́n má ba à fi gbogbo ìrékọjá ba ara wọn jẹ́ mọ́. Ṣùgbọ́n kí wọ́n le jẹ́ ènìyàn mi, kí Èmi náà sì le jẹ́ Ọlọ́run wọn, ni Olúwa Olódùmarè wí.’”
Pentru ca să nu mai rătăcească de la mine casa lui Israel, nici să nu mai fie pângărită cu toate fărădelegile lor; ci ca ei să fie poporul meu și eu să le fiu Dumnezeu, spune Domnul DUMNEZEU.
12 Ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá wí pé:
Cuvântul DOMNULUI a venit din nou la mine, spunând:
13 “Ọmọ ènìyàn bí orílẹ̀-èdè kan bá dẹ́ṣẹ̀ sí mi nípa ìwà àìṣòdodo, èmi yóò nawọ́ mi jáde sí wọn, láti gé ìpèsè oúnjẹ wọn, èmi yóò rán ìyàn sí wọn, èmi yóò sì pa ènìyàn àti ẹranko inú rẹ̀,
Fiu al omului, când țara păcătuiește împotriva mea încălcând [legea] cumplit, atunci îmi voi întinde mâna asupra ei și îi voi sfărâma toiagul pâinii și voi trimite foamete asupra ei și voi stârpi pe om și pe animal din ea;
14 bí àwọn ọkùnrin mẹ́ta yìí. Noa, Daniẹli àti Jobu tilẹ̀ wà nínú rẹ, kìkì ẹ̀mí ara wọn nìkan ni wọ́n lé fi òdodo wọn gbàlà, Olúwa Olódùmarè wí.
Chiar dacă acești trei bărbați: Noe, Daniel și Iov, ar fi în ea, ei și-ar elibera [numai] propriile lor suflete prin dreptatea lor, spune Domnul DUMNEZEU.
15 “Tàbí bí mo bá jẹ́ kí ẹranko búburú gba orílẹ̀-èdè náà kọjá, tí wọn sì bà á jẹ́ tó bẹ́ẹ̀ tí ó di ahoro, tí kò sí ẹni tó le gba ibẹ̀ kọjá torí ẹranko búburú yìí,
Dacă eu fac să treacă prin țară fiare vătămătoare și ele o jefuiesc, astfel încât este pustiită, încât niciun om să nu poată trece prin ea din cauza fiarelor,
16 bí àwọn ọkùnrin mẹ́ta wọ̀nyí tilẹ̀ wà nínú rẹ̀, Olúwa Olódùmarè wí pé, wọn kì yóò gba ọmọkùnrin tàbí ọmọbìnrin là: àwọn nìkan ni a ó gbàlà, ṣùgbọ́n ilẹ̀ náà yóò di ahoro.
[Chiar dacă] acești trei bărbați [ar fi] în ea, [precum] eu trăiesc, spune Domnul DUMNEZEU, ei nu vor elibera nici fii nici fiice; numai ei vor fi eliberați, iar țara va fi pustiită.
17 “Tàbí tí mo bá mú idà kọjá láàrín orílẹ̀-èdè náà tí mo wí pé, ‘Ẹ jẹ́ kí idà kọjá láàrín ilẹ̀ náà,’ tí mo sì tú ìbínú gbígbóná lé wọn lórí nípa ìtàjẹ̀ sílẹ̀, tí mo pa ènìyàn àti ẹranko inú rẹ.
Sau [dacă] aduc o sabie asupra acelei țări și spun: Sabie, străbate țara; pentru ca eu să stârpesc pe om și pe animal din ea;
18 Bí àwọn ọkùnrin mẹ́ta yìí tilẹ̀ wà nínú rẹ̀, Olúwa Olódùmarè wí pé, bí mo ti wà, wọn ki yóò gba ọmọkùnrin tàbí ọmọbìnrin là, ṣùgbọ́n àwọn tìkára wọn nìkan ni a ó gbàlà.
Chiar dacă acești trei bărbați [ar fi] în ea, [precum] eu trăiesc, spune Domnul DUMNEZEU, ei nu vor elibera nici fii nici fiice, ci numai ei singuri vor fi eliberați.
19 “Tàbí bí mo rán àjàkálẹ̀-ààrùn si ilẹ̀ náà, ti mo si da ìrunú mi lé e lórí pẹ̀lú ẹ̀jẹ̀, láti gé ènìyàn àti ẹranko kúrò nínú rẹ̀,
Sau [dacă] trimit o ciumă în acea țară și îmi torn furia asupra ei în sânge, pentru a stârpi pe om și pe animal din ea;
20 bó tilẹ̀ jẹ́ pé Noa, Daniẹli àti Jobu wà nínú rẹ, bí mo ti wà láààyè ni Olúwa Olódùmarè wí, wọn kò le gba ọmọkùnrin tàbí ọmọbìnrin wọn lá. Ara wọn nìkan ni ìwà òdodo wọn lè gbàlà.
Chiar dacă Noe, Daniel și Iov, [ar fi] în ea, [precum] eu trăiesc, spune Domnul DUMNEZEU, ei nu vor elibera nici fiu nici fiică; ei, prin dreptatea lor, vor elibera [numai] propriile lor suflete.
21 “Nítorí báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí, báwo ni yóò ti burú tó nígbà tí mo bá rán ìdájọ́ kíkan mi mẹ́rin sórí Jerusalẹmu, èyí ni idà àti ìyàn, ẹranko búburú àti àjàkálẹ̀-ààrùn láti pa àwọn ènìyàn àti ẹranko inú rẹ̀!
Pentru că astfel spune Domnul DUMNEZEU: Cu cât mai mult atunci, când voi trimite cele patru judecăți cumplite ale mele asupra Ierusalimului: sabia și foametea și fiara nimicitoare și ciuma, pentru a stârpi din el pe om și pe animal?
22 Síbẹ̀, yóò ṣẹ́kù àwọn díẹ̀, àwọn ọmọkùnrin àti ọmọbìnrin tí a ó kó jáde nínú rẹ̀. Wọn yóò wá bá yin, ẹ̀yin yóò rí ìwà àti ìṣe wọn, nígbà náà ni ẹ̀yin yóò rí ìtùnú nípa àjálù tí mo mú wá sórí Jerusalẹmu—àní gbogbo àjálù ní mo ti mú wá sórí rẹ̀.
Totuși, iată, va fi lăsată în el o rămășiță care va fi scoasă, [deopotrivă] fii și fiice; iată, ei vor ieși la voi și voi veți vedea calea lor și facerile lor; și veți fi mângâiați referitor la răul pe care l-am adus asupra Ierusalimului, [da], referitor la tot ce am adus asupra lui.
23 Nígbà tí ẹ̀yin bá rí ìwà àti ìṣe wọn, a ó tù yín nínú, nítorí pé ẹ̀yin yóò mọ̀ pé èmi kò ṣe nǹkan kan láìnídìí, ni Olúwa Olódùmarè wí.”
Și, când voi vedeți căile lor și facerile lor, ei vă vor mângâia; și veți cunoaște că, tot ce am făcut în el, nu am făcut fără motiv, spune Domnul DUMNEZEU.

< Ezekiel 14 >