< Ezekiel 14 >

1 Díẹ̀ nínú àwọn àgbàgbà Israẹli wá sọ́dọ̀ mi, wọ́n sì jókòó níwájú mi.
Isala: ili ouligisu dunu mogili da Hina Gode Ea hanai bai dawa: musa: , nama adole ba: musa: misi.
2 Nígbà náà ni ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá,
Amalalu, Hina Gode da nama amane sia: i,
3 “Ọmọ ènìyàn, àwọn ọkùnrin wọ̀nyí ti gbé òrìṣà kalẹ̀ sínú ọkàn wọn, wọ́n sì gbé àwọn ohun tó lè mú wọn ṣubú sínú ẹ̀ṣẹ̀ síwájú wọn; Èmi yóò ha jẹ́ kí wọ́n béèrè lọ́wọ́ mi rárá bí?
“Dunu egefe! Amo dunu da ogogosu loboga hamoi ‘gode’ ilima fa: no bobogei dagoiba: le, wadela: i hou bagade hamosa. Di adi dawa: bela: ? Na da ilima bu adole ima: bela: ? Hame mabu!
4 Nítorí náà, sọ fún wọn pé, ‘Báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí: Bí ẹnikẹ́ni ní ilé Israẹli tó gbé òrìṣà sí ọkàn rẹ̀, tó tún gbé ohun ìkọ̀sẹ̀ síwájú rẹ̀, tí ó sì wá sọ́dọ̀ wòlíì, Èmi Olúwa fúnra mi ni yóò dá ẹni tí ó wa lóhùn gẹ́gẹ́ bí ìwà ìbọ̀rìṣà rẹ.
Wali ilima sia: ma! Na, Ouligisu Hina Gode, Na sia: ilima amane adosima, ‘Nowa Isala: ili dunu da ogogosu ‘gode’ liligi ilima fa: no bobogebeba: le, wadela: le hamosea, amola bu balofede dunudafa amoma adole ba: musa: dawa: sea, amo dunuma Na da hina: ogogosu ‘gode’ loboga hamoi ilima adole imunu defele, ema adole imunu.
5 Èmi yóò ṣe èyí láti gba ọkàn àwọn ará Israẹli tó ti tẹ̀lé òrìṣà wọn lọ padà sí ọ̀dọ̀ mi.’
Isala: ili fi dunu huluane da ogogosu ‘gode’ ilima fa: no bobogebeba: le, Na hou yolesi. Be ilia da sinidigili, Nama bu dogolegemusa: , Na da amo defele ilima adole imunu.
6 “Nítorí náà sọ fún ilé Israẹli, ‘Èyí ni ohun tí Olúwa Olódùmarè wí: Ẹ ronúpìwàdà! Ẹ yípadà kúrò lọ́dọ̀ òrìṣà yín, kí ẹ̀yin sì kọ gbogbo ìwà ìríra yín sílẹ̀!
Amaiba: le, Na, Ouligisudafa Hina Gode, Na sia: Isala: ili dunuma amane olelema, ‘Sinidigima! Dilia wadela: idafa loboga hamoi ogogosu ‘gode’ yolesima.
7 “‘Bí ẹnikẹ́ni ní ilé Israẹli tàbí àlejò tó ń gbé ní ilẹ̀ Israẹli, bá ya ara rẹ̀ kúrò lọ́dọ̀ mi, tó gbé òrìṣà rẹ̀ sí ọkàn rẹ̀, tó tún gbé ohun tó mú ni ṣubú sínú ẹ̀ṣẹ̀ síwájú rẹ, lẹ́yìn èyí tó tún lọ sọ́dọ̀ wòlíì láti béèrè nǹkan lọ́wọ́ mi! Èmi Olúwa fúnra ara mi ní èmi yóò dá a lóhùn.
Isala: ili dunu afae o ga fi dunu amo da Isala: ili fi ganodini esala, amo da Na yolesili, ogogosu ‘gode’ ilima fa: no bobogesea, amola fa: no balofededafa ema adole ba: sea, Na, Hina Gode da amo dunuma bu adole imunu agoane;
8 Èmi yóò lòdì si irú ọkùnrin bẹ́ẹ̀ lọ́nà òdì, Èmi yóò sì fi i ṣe àmì àti òwe. Èmi yóò sì gé e kúrò láàrín àwọn ènìyàn mi. Nígbà náà, ẹ̀yin yóò mọ̀ pé èmi ni Olúwa.
Na da ema ha lamu. Na da eno dunu ilia dawa: digima: ne, ema se imunu. Na da Na fi dunu ilima, e fadegamu. Amasea, Na da Hina Godedafa, amo dilia da dawa: mu.
9 “‘Bí wọ́n bá sì tan wòlíì náà láti sọtẹ́lẹ̀, Èmi Olúwa ló tan wòlíì náà, Èmi yóò nawọ́ sí i, èmi yóò sì pa á run kúrò láàrín àwọn ènìyàn mi Israẹli.
Ogogosu balofede dunu da ea fi dunuma ogogole adole iasea, Na da ea asigi dawa: su olelebeba: le, e da ogogosu sia: sa. Na da amo dunu Isala: ili fi ilima fadegamu.
10 Wọn yóò ru ẹ̀bi ẹ̀ṣẹ̀ wọn—ìjìyà kan náà là ó fún wòlíì àti ẹni tó lọ béèrè lọ́dọ̀ rẹ̀.
Ogogosu balofede dunu, amola nowa dunu da ema bai adole ba: sea, ela galu da se dabe iasu defele ba: mu.
11 Kí ilé Israẹli má ba à ṣáko kúrò lọ́dọ̀ mi mọ, kí wọ́n má ba à fi gbogbo ìrékọjá ba ara wọn jẹ́ mọ́. Ṣùgbọ́n kí wọ́n le jẹ́ ènìyàn mi, kí Èmi náà sì le jẹ́ Ọlọ́run wọn, ni Olúwa Olódùmarè wí.’”
Isala: ili dunu da Na yolesisa: besa: le, amola wadela: i hou hamobeba: le, ledo agoai ba: sa: besa: le, Na da ilima amo se imunu. Isala: ili dunu da Na fidafa esalumu da defea, amola Na da ilia Gode esalumu.” Ouligisu Hina Gode da sia: i dagoi.
12 Ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá wí pé:
Hina Gode da nama amane sia: i,
13 “Ọmọ ènìyàn bí orílẹ̀-èdè kan bá dẹ́ṣẹ̀ sí mi nípa ìwà àìṣòdodo, èmi yóò nawọ́ mi jáde sí wọn, láti gé ìpèsè oúnjẹ wọn, èmi yóò rán ìyàn sí wọn, èmi yóò sì pa ènìyàn àti ẹranko inú rẹ̀,
“Dunu egefe! Fifi asi gala afae da Na yolesili, amola wadela: i hou hamosea, Na da na lobo molole gale, amola ilia ha: i nasu logo hedofamu.
14 bí àwọn ọkùnrin mẹ́ta yìí. Noa, Daniẹli àti Jobu tilẹ̀ wà nínú rẹ, kìkì ẹ̀mí ara wọn nìkan ni wọ́n lé fi òdodo wọn gbàlà, Olúwa Olódùmarè wí.
Be amomane dunu Nowa, amola Da: niele, amola Yoube, ilia da amogai esala ganiaba, be ilia hou ida: iwane da eno dunu hame gaga: la: loba, be ilila: esalusu fawane gaga: la: loba.” Ouligisu Hina God da sia: i dagoi.
15 “Tàbí bí mo bá jẹ́ kí ẹranko búburú gba orílẹ̀-èdè náà kọjá, tí wọn sì bà á jẹ́ tó bẹ́ẹ̀ tí ó di ahoro, tí kò sí ẹni tó le gba ibẹ̀ kọjá torí ẹranko búburú yìí,
Hina Gode da eno amane sia: i, “Amama: bela: ? Na da dunu huluane fane legema: ne nimi bagade sigua ohe asunasima: bela: ? Soge huluane da sigua ohega nabaiba: le, dilia da sogega masunu beda: mu.
16 bí àwọn ọkùnrin mẹ́ta wọ̀nyí tilẹ̀ wà nínú rẹ̀, Olúwa Olódùmarè wí pé, wọn kì yóò gba ọmọkùnrin tàbí ọmọbìnrin là: àwọn nìkan ni a ó gbàlà, ṣùgbọ́n ilẹ̀ náà yóò di ahoro.
Amola amomane, amo dunu udiana da amoga esala ganiaba, (Na, Ouligisudafa amola Fifi Ahoanusu Hina Godedafa, Na da sia: sa) ilia da ilia manodafa amo gaga: musa: hame dawa: laloba. Ilia da ilila: musu gaga: mu fawane dawa: la: loba. Amola soge huluane da wadela: lesi dagoi ba: la: loba.
17 “Tàbí tí mo bá mú idà kọjá láàrín orílẹ̀-èdè náà tí mo wí pé, ‘Ẹ jẹ́ kí idà kọjá láàrín ilẹ̀ náà,’ tí mo sì tú ìbínú gbígbóná lé wọn lórí nípa ìtàjẹ̀ sílẹ̀, tí mo pa ènìyàn àti ẹranko inú rẹ.
O amama: bela: ? Na da amo soge ganodini gegema: ne gasa bagade gegesu liligi iasili, amoga ilia da gegesea, dunu amola ohe fi esalebe da huluane bogogia: le ebelemu.
18 Bí àwọn ọkùnrin mẹ́ta yìí tilẹ̀ wà nínú rẹ̀, Olúwa Olódùmarè wí pé, bí mo ti wà, wọn ki yóò gba ọmọkùnrin tàbí ọmọbìnrin là, ṣùgbọ́n àwọn tìkára wọn nìkan ni a ó gbàlà.
Amola amo dunu udiana (Nowa, amola Da: niele, amola Yoube) da esala ganiaba, (Na Ouligisudafa Hina Gode, amola Fifi Ahoanusu Hina Gode da amane sia: sa), ilia da ilia manodafa gaga: mu hame dawa: la: loba, be ilila: musu gaga: mu fawane dawa: la: loba.
19 “Tàbí bí mo rán àjàkálẹ̀-ààrùn si ilẹ̀ náà, ti mo si da ìrunú mi lé e lórí pẹ̀lú ẹ̀jẹ̀, láti gé ènìyàn àti ẹranko kúrò nínú rẹ̀,
Be Na da ougiba: le, amo fifi asi gala ili hamoi amoga ilima olo momadela ahoasea amola dunu amola ohe bagohame bogogia: sea,
20 bó tilẹ̀ jẹ́ pé Noa, Daniẹli àti Jobu wà nínú rẹ, bí mo ti wà láààyè ni Olúwa Olódùmarè wí, wọn kò le gba ọmọkùnrin tàbí ọmọbìnrin wọn lá. Ara wọn nìkan ni ìwà òdodo wọn lè gbàlà.
Nowa amola Da: niele amola Yoube da amogai esala ganiaba, (Na, Ouligisu Hina Gode, Ouligisudafa Hina Gode da dafawane sia: sa), ilia da ilia manodafa gaga: musa: hame dawa: la: loba. Be ilila: hou noga: i hamobeba: le, ili fawane gaga: i dagoi ba: la: loba.”
21 “Nítorí báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí, báwo ni yóò ti burú tó nígbà tí mo bá rán ìdájọ́ kíkan mi mẹ́rin sórí Jerusalẹmu, èyí ni idà àti ìyàn, ẹranko búburú àti àjàkálẹ̀-ààrùn láti pa àwọn ènìyàn àti ẹranko inú rẹ̀!
Ouligisudafa Hina Gode da amane sia: na, “Na da Na baligili se iasu biyaduyale gala amo Yelusaleme fi ilima iasimu. Amo da gegesu, amola ha: su amola sigua ohe fi gasonasu amola ologia: su. Amoga dunu amola ohe da defele bogogia: mu.
22 Síbẹ̀, yóò ṣẹ́kù àwọn díẹ̀, àwọn ọmọkùnrin àti ọmọbìnrin tí a ó kó jáde nínú rẹ̀. Wọn yóò wá bá yin, ẹ̀yin yóò rí ìwà àti ìṣe wọn, nígbà náà ni ẹ̀yin yóò rí ìtùnú nípa àjálù tí mo mú wá sórí Jerusalẹmu—àní gbogbo àjálù ní mo ti mú wá sórí rẹ̀.
Be Yelusaleme fi dunu mogili da mae bogole esalebe ba: mu. Amola dunu mano amola uda mano gaga: i, ilia da dima masea, di da ilia hou ba: ma. Ilia da wadela: idafa, di da ba: mu. Amasea, se iasu Na da Yelusaleme fi amo iasi da moloidafa, amo di da dawa: mu.
23 Nígbà tí ẹ̀yin bá rí ìwà àti ìṣe wọn, a ó tù yín nínú, nítorí pé ẹ̀yin yóò mọ̀ pé èmi kò ṣe nǹkan kan láìnídìí, ni Olúwa Olódùmarè wí.”
Amasea, hou huluane Na hamoi amo da bai gala, di da dawa: mu.” Ouligisu Hina Gode da sia: i dagoi.

< Ezekiel 14 >