< Ezekiel 12 >

1 Ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá wí pé:
HIKI mai la hoi ka olelo a Iehova ia'u, i mai la.
2 “Ọmọ ènìyàn, ìwọ ń gbé ní àárín ọlọ̀tẹ̀ ènìyàn. Wọ́n lójú láti fi ríran, ṣùgbọ́n wọn kò ríran, bẹ́ẹ̀ ni wọ́n létí láti fi gbọ́rọ̀ ṣùgbọ́n wọn kò gbọ́rọ̀, torí pé ọlọ̀tẹ̀ ènìyàn ni wọ́n.
E ke keiki a ke kanaka, ke noho nei no oe iwaenakonu o ka ohana kipi, he mau maka e ike ai ko lakou, aole hoi i ike; he mau pepeiao e lohe ai ko lakou, aole hoi i lohe: no ka mea, he ohana kipi lakou.
3 “Nítorí náà, ọmọ ènìyàn, palẹ̀ ẹrù rẹ mọ́ láti lọ sí ìgbèkùn, ní ọ̀sán gangan ní ojú wọn, kúrò láti ibi tí ìwọ wà lọ sí ibòmíràn. Bóyá bí wọ́n bá rí ọ, wọn yóò sì ronú bó tilẹ̀ jẹ́ pé ọlọ̀tẹ̀ ilé ni wọ́n.
Nolaila, e ke keiki a ke kanaka, e hoomakaukau oe i mau mea no ka hele ana; a e hele hoi oe ma ka la imua o ko lakou mau maka, a e hele ae mai kou wahi aku, i kekahi wahi aku imua o ko lakou mau maka; malia paha e noonoo lakou; he ohana kipi no hoi lakou.
4 Di ẹrù ìgbèkùn rẹ lójú wọn ní ọ̀sán án gangan, nígbà tí ó bá sì di alẹ́, ní ojú wọn, máa lọ sí ìgbèkùn gẹ́gẹ́ bí àwọn tí ó lọ ìgbèkùn ṣe máa ń ṣe.
Alaila oe e lawe ae iwaho i kou ukana ma ka la no, imua o ko lakou mau maka, me he ukana la no ka hele ana: a e hele aku i ke ahiahi imua o ko lakou mau maka, me he hele ana la i ke pio ana.
5 Dá ògiri lu ní ojú wọn, kí ìwọ sì gba ibẹ̀ kó ẹrù rẹ jáde.
Imua o ko lakou mau maka e pao ae oe iloko o ka pa, a malaila e lawe aku ai iwaho.
6 Gbé ẹrù rẹ lé èjìká ní ojú wọn, bo ojú rẹ, kí ìwọ má ba à rí ilẹ̀, sì ru ẹrù rẹ lọ ní alẹ́ nítorí pé mo fi ọ́ ṣe àmì fún ilé Israẹli.”
Imua o ko lakou mau maka e amo ai oe maluna o kou mau pohiwi, a e hali aku iwaho i ka powehiwehi; e uhi hoi oe i kou wahi maka i ike ole ai oe i ka honua, no ka mea, ua hoonoho iho au ia oe i hoailona no ka ohana a Iseraela.
7 Mo ṣe gẹ́gẹ́ bí Olúwa ti pàṣẹ fún mi. Mo kó ẹrù mi jáde ní ọ̀sán án láti lọ fun ìgbèkùn. Nígbà tó di ìrọ̀lẹ́, mo dá ògiri lu pẹ̀lú ọwọ́ mi. Mo sì gbe ẹrù mi lé èjìká nínú òkùnkùn ní ojú wọn.
A hana iho la au e like me au i kauohaia mai ai; ua lawe ae au i kuu ukana i ka la me he ukana la no ke pio ana, a i ke ahiahi pao ae la au iloko o ka pa me ka lima o'u; hali ae la au iwaho i ka powehiwehi, a amo hoi au maluna o ka pohiwi imua o ko lakou mau maka.
8 Ní òwúrọ̀ ọjọ́ kejì, ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá wí pé:
A i ke kakahiaka, hiki mai la ka olelo a Iehova ia'u, i mai la,
9 “Ọmọ ènìyàn, ǹjẹ́ ọlọ̀tẹ̀ ilé Israẹli tilẹ̀ bi ọ́ pé, ‘Kí ni ohun tí o ń ṣe túmọ̀ sí?’
E ke keiki a ke kanaka, aole anei i ninau ia oe ka ohana a Iseraela, ka ohana kipi, Heaha kau e hana nei?
10 “Sọ fún wọn pé, ‘Báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí, ọ̀rọ̀-ìjìnlẹ̀ yìí kan àwọn ọmọ-aládé Jerusalẹmu àti gbogbo ilé Israẹli tí ó wà ní àárín rẹ.
E olelo oe ia lakou, Ke i mai nei o Iehova ka Haku, penei; O keia ukana, no ke alii iloko o Ierusalema, a me ka ohana a pau a Iseraela iwaena o lakou.
11 Sọ fún wọn pé, Èmi jẹ́ àmì fún yín’. “Gẹ́gẹ́ bí mo ti ṣe, bẹ́ẹ̀ ni a ó ṣe sí wọn. Wọn ó kó lọ sí ìgbèkùn. Gẹ́gẹ́ bí ẹni ti a dè ní ìgbèkùn.
E olelo ae, Owau no ka hoailona no oukou; e like me ka'u i hana'i, pela e hanaia mai ai lakou; a e hele aku lakou, a e lilo i ke pio ana.
12 “Ọmọ-aládé tí ó wà ní àárín wọn yóò di ẹrù rẹ̀ lé èjìká ní alẹ́ yóò sì jáde lọ, òun náà yóò da ògiri lu kí ó le gba ibẹ̀ jáde. Yóò sì bo ojú rẹ̀ kí ó má ba à rí ilẹ̀.
A o ke alii iwaena o lakou, e amo no oia ma kona pohiwi i ka powehiwehi, a puka aku no; e wawahi lakou i ka pa i kahi e halihali ai lakou iwaho: e uhi no hoi oia kona wahi maka i ike ole oia i ka honua me na maka.
13 Èmi yóò ta àwọ̀n mi lé e lórí, yóò sì kó sínú okùn, Èmi yóò sì mú lọ sí Babeli, ní ilẹ̀ Kaldea, ṣùgbọ́n kò ní fojúrí ilẹ̀ náà ibẹ̀ ni yóò kú sí.
E hohola hoi au i ko'u upena maluna ona, a e hei no ia i kuu pahele; a e lawe au ia ia ma Babulona, ka aina o ko Kaledea; aole nae ia e ike aku ia, e make no nae oia ilaila.
14 Gbogbo àwọn tó yí i ká láti ràn án lọ́wọ́ ọ̀pá ìtẹ̀lẹ̀ àti àwọn ọmọ-ogun rẹ̀ ni Èmi yóò túká sí afẹ́fẹ́, èmi yóò sì tún fi idà lé wọn kiri.
A o ka poe a pau e hoopuni ana ia ia, e kokua ia ia, oia ka'u e hoopuehu i kela makani i keia makani, a me kana mau poe; a e unuhi ae au i ka pahikaua mahope iho o lakou.
15 “Wọn yóò sì mọ̀ pé èmi ni Olúwa nígbà tí mo bá tú wọn ká ní àárín àwọn orílẹ̀-èdè, tí mo sì fọ́n wọn ká sí ilẹ̀ káàkiri.
A e ike no lakou, owau no Iehova, aia hoopuehu au ia lakou iwaena o na lahuikanaka, a e hoohele liilii ia lakou i na aina.
16 Ṣùgbọ́n èmi yóò ṣẹ́ díẹ̀ kù lára wọn, ní ọwọ́ idà, ìyàn àti àjàkálẹ̀-ààrùn, kí wọn le jẹ́wọ́ gbogbo ìṣe ìríra wọn ní àárín àwọn orílẹ̀-èdè yìí. Nígbà náà ni wọn yóò mọ̀ pé, Èmi ni Olúwa.”
Aka, e hookoe au i kekahi mau kanaka o lakou, i ka pahikaua, a i ka wi, a i ka mai ahulau; i hai aku lakou i ko lakou mau mea hoopailua a pau iwaena o na lahuikanaka i hele ai lakou; a e ike lakou owau no Iehova.
17 Ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá wí pé:
Hiki mai la no hoi ka olelo a Iehova ia'u, i mai la,
18 “Ọmọ ènìyàn, jẹ oúnjẹ rẹ pẹ̀lú ìwárìrì, sì mu omi rẹ pẹ̀lú ìwárìrì àti àìbalẹ̀ àyà.
E ke keiki a ke kanaka, e ai i kau berena me ka haalulu, a e inu i kou wai me ka weliweli, a me ke kaumaha;
19 Sọ fún àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà pé, ‘Báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí fún àwọn olùgbé Jerusalẹmu àti ilẹ̀ Israẹli pé, pẹ̀lú àìbalẹ̀ àyà ni wọn yóò máa jẹun wọn, wọn yóò sì mu omi pẹ̀lú àìnírètí, kí ilẹ̀ wọn lè di ahoro torí ìwà ipá àwọn tó ń gbé ibẹ̀.
A e olelo aku i na kanaka o ka aina, Ke i mai nei o Iehova ka Haku no ko Ierusalema, a me ko ka aina o Iseraela, E ai lakou i ka lakou berena me ka malama pono, a e inu i ko lakou wai me ka pihoihoi, i neoneo loa ka aina i ka ole o ko laila a pau, no ka hoohaunaele ana o ka poe a pau e noho ana ilaila.
20 Ìlú tó jẹ́ ibùgbé ènìyàn tẹ́lẹ̀ yóò di òfo, ilẹ̀ náà yóò sì di ahoro. Ẹ̀yin yóò sì mọ̀ pé, Èmi ni Olúwa.’”
A e hooneoneoia na kulanakauhale i nohoia, a e neoneo no hoi ka aina; a e ike no hoi oukou owau no Iehova.
21 Ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá pé:
Hiki mai la hoi ka olelo a Iehova ia'u, i mai la,
22 “Ọmọ ènìyàn, irú òwe wo ni ẹ pa nílẹ̀ Israẹli pé: ‘A fa ọjọ́ gùn, gbogbo ìran di asán’?
E ke keiki a ke kanaka, he aha kela olelo a oukou ma ka aina o ka Iseraela, o ka i ana, Ua hoopaneeia na la, a ua lilo e na hihio a pau?
23 Nítorí náà wí fún wọn pé, ‘Báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí, Èmi yóò fi òpin sí òwe yìí, wọn kò ní ipa mọ́ ní Israẹli.’ Sọ fún wọn, ‘Ọjọ́ náà súnmọ́ tòsí nígbà tí gbogbo ìran àti ìsọtẹ́lẹ̀ yóò sì wá sí ìmúṣẹ.
Nolaila e olelo aku oe ia lakou, Ke i mai nei o Iehova ka Haku penei; E hooki au i keia olelo, aole lakou e lawe hou ia mea me he olelo akamai la iloko o ka Iseraela; aka, e olelo aku ia lakou, Kokoke mai na la, a me ka io o na hihio a pau.
24 Nítorí kò ní sí ìran asán tàbí àfọ̀ṣẹ tí ó ń pọ́n ni mọ́ ní àárín ilé Israẹli.
No ka mea, aole e hihio oiaio ole hou, a me ka wanana malimali iloko o ka ohana a Iseraela.
25 Ṣùgbọ́n, Èmi Olúwa yóò sọ̀rọ̀, ọ̀rọ̀ tí mo sọ yóò sì ṣẹ láì falẹ̀. Báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí, ní àsìkò yín, ẹ̀yin ọlọ̀tẹ̀ ilé ni Èmi yóò mú ọ̀rọ̀ yówù tí mo bá sọ ṣẹ.’”
No ka mea, Owau no Iehova; e olelo aku no wau, a e ko io no ka mea a'u i olelo ai, aole e hoopanee hou ia'ku; no ka mea, i ko oukou mau la, e ka ohana kipi, e olelo au i ka olelo, a e hooko iho no, wahi a Iehova ka Haku.
26 Ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá pé:
Hiki hou mai la ka olelo a Iehova ia'u, i mai la,
27 “Ọmọ ènìyàn, ilé Israẹli ń wí pé, ‘Ìran ọjọ́ pípẹ́ ni ìwọ rí, ìwọ sì sọtẹ́lẹ̀ nípa àsìkò tó jìnnà réré.’
E ke keiki a ke kanaka, eia hoi, ke olelo nei ka ohana a Iseraela, O ka hihio ana i ike ai, no na la he nui no ia, a ke wanana nei no ia no na manawa loihi aku.
28 “Nítorí náà sọ fún wọn, ‘Báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí, kò sí ọ̀kan nínú ọ̀rọ̀ mi tí yóò sún síwájú mọ́; ṣùgbọ́n ọ̀rọ̀ tí mo bá sọ yóò ṣẹ.’”
Nolaila e olelo aku ia lakou, Ke i mai nei o Iehova ka Haku, peneia; Aole olelo a'u e hoopanee hou ia'ku, aka, e hookoia'ku ka olelo a'u i olelo ai, wahi a Iehova ka Haku.

< Ezekiel 12 >