< Ezekiel 11 >

1 Ẹ̀mí sì gbé mi sókè, ó mú mi lọ sí ẹnu-ọ̀nà ilé Olúwa èyí tó dojúkọ ìlà-oòrùn. Ní àbáwọlé ẹnu-ọ̀nà yìí ni àwọn ọkùnrin mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n wá, mo rí Jaaṣaniah ọmọ Assuri àti Pelatiah ọmọ Benaiah, tí wọ́n jẹ́ ìjòyè àwọn ènìyàn.
Muithla mah ang tapom tahang moe, nih angyae bang anghae Angraeng im khongkha ah ang caeh haih; khongkha thok taengah loe nongpa pumphae pangato oh o, nihcae thungah kami zaehoikung, Azur capa Jaazaniah hoi Benaiah capa Pelatiah to ka hnuk.
2 Olúwa sì sọ fún mi pé, “Ọmọ ènìyàn, àwọn ọkùnrin yìí ló ń pète ibi, wọ́n sì ń gbé ìmọ̀ràn búburú kalẹ̀ nínú ìlú.
Anih mah kai khaeah, Kami capa, hae kaminawk loe kahoih ai hmuen sah kami, hae vangpui thungah kasae poekhaih paekkung ah oh o:
3 Wọ́n ní, ‘Kò ha tí ì tó àsìkò láti kọ́lé? Ìlú yìí ni ìkòkò ìdáná, àwa sì ni ẹran’.
nihcae mah, Atue pha ai vop, im kapop ah sah o si, hae vangpui loe moi thonghaih laom ah oh moe, aicae loe moi ah a oh o, tiah a thuih o.
4 Nítorí náà sọtẹ́lẹ̀ nípa wọn; ọmọ ènìyàn, sọtẹ́lẹ̀.”
To pongah nihcae misa haih lok to taphong ah, Aw kami capa, lok to taphong ah, tiah ang naa.
5 Ẹ̀mí Olúwa sì bà lé mi, ó sì wí pé, “Sọ̀rọ̀!” Báyìí ni Olúwa wí, ohun tí ẹ ń sọ nìyìí, ilé Israẹli, mo mọ ohun tó wà lọ́kàn yín.
To pacoengah Angraeng ih Muithla ka nuiah angzoh moe, Aw Israel imthung takohnawk, na thuih o ih lok hoi na poek o ih hmuennawk to ka panoek boih, tiah Angraeng mah thuih, tiah lok to thui pae ah, tiah ang naa.
6 Ẹ̀yin ti sọ òkú yín di púpọ̀ nínú ìlú yìí, òkú sì ti kún gbogbo ìgboro rẹ̀.
Hae vangpui thungah pop parai kami to na hum o moe, kami qok hoiah loklam to na koi o sak boeh.
7 “Torí náà, báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí, àwọn òkú tí ẹ fọn sílẹ̀ sí àárín yín ni ẹran, ìlú yìí sì ni ìkòkò ìdáná ṣùgbọ́n èmi yóò le yín jáde níbẹ̀.
To pongah Angraeng Sithaw mah, Vangpui um ah na vah o ih kami qok loe, moi ah oh moe, vangpui loe laom ah oh, toe hae vangpui thung hoiah kang haek o han, tiah thuih.
8 Ẹ bẹ̀rù idà, èmi yóò sì mú idà wá sórí yín, bẹ́ẹ̀ ni Olúwa Olódùmarè wí.
Nangcae mah sumsen to na zit o, to pongah nangcae tuk hanah to sumsen to ka sin han, tiah Angraeng Sithaw mah thuih.
9 Èmi yóò lé yín jáde kúrò ní ìlú yìí, èmi yóò sì fà yín lé àjèjì lọ́wọ́, èmi yóò sì mú ìdájọ́ ṣẹ lé yín lórí.
Vangpui thung hoiah kang haek o moe, prae kalah kaminawk ban ah kang paek o pacoengah, kang thuitaek o han.
10 Nípa idà ni ẹ̀yin yóò ṣubú, èmi yóò sì ṣe ìdájọ́ yín ní àwọn ààlà ìlú Israẹli. Nígbà náà ni ẹ̀yin yóò mọ̀ pé, Èmi ni Olúwa.
Sumsen hoiah nam timh o tih, Israel ramri ah lok kang caek o han; to naah Kai loe Angraeng ni, tiah na panoek o tih.
11 Ìlú yìí kò ní i jẹ́ ìkòkò ìdáná, bẹ́ẹ̀ ni ẹ̀yin náà kò sì ní jẹ́ ẹran nínú rẹ̀, Èmi yóò ṣe ìdájọ́ yín ní àwọn ààlà ìlú Israẹli.
Hae vangpui loe nangcae han laom ah om mak ai, nangcae loe moi ah doeh na om o mak ai; nangcae loe Israel ramri ah lok kang caek o han:
12 Ẹ̀yin yóò sì mọ̀ pé, Èmi ni Olúwa, nítorí pé ẹ̀yin kò tẹ̀lé àṣẹ mi ẹ̀yin kò sì pa òfin mi mọ́, ṣùgbọ́n ẹ̀yin ti hùwà gẹ́gẹ́ bí àwọn aláìgbàgbọ́ orílẹ̀-èdè tó yí yín ká.”
to naah Kai loe Angraeng ni, tiah na panoek o tih; kang patuk ih lok to na pazui o ai moe, ka lokcaekhaih doeh na pakuem o ai, nangcae taengah kaom Sithaw panoek ai kaminawk baktiah kho na sak o lat, tiah a naa.
13 Bí mo ṣe ń sọtẹ́lẹ̀ lọ́wọ́, Pelatiah ọmọ Benaiah kú. Mo sì dojúbolẹ̀, mo sì kígbe sókè pé, “Háà! Olúwa Olódùmarè! Ṣé ìwọ yóò ha pa ìyókù Israẹli run pátápátá ni?”
To tiah lok ka thuih li naah, Benaiah capa Pelatiah to duek. To naah ka kuep moe, tha hoi ka qah, Aw Angraeng Sithaw! Kanghmat Israel kaminawk doeh na paduek boih han boeh maw? tiah ka naa.
14 Ọ̀rọ̀ Olúwa tún tọ̀ mí wá wí pé,
Angraeng ih lok kai khaeah angzoh let,
15 “Ọmọ ènìyàn, àwọn arákùnrin rẹ, àní àwọn ará rẹ, àwọn ọkùnrin nínú ìbátan rẹ, àti gbogbo ilé Israẹli pátápátá, ni àwọn ará Jerusalẹmu ti wí fún pé, ‘Ẹ jìnnà sí Olúwa, àwa ni a fi ilẹ̀ yìí fún yín ní ìní.’
Kami capa, nam nawkamyanawk, nangmacae acaengnawk, Israel imthung takoh boih hoi Jerusalem kaminawk mah, Angraeng khae hoi kangthla ah om oh; aicae mah toep hanah hae prae hae paek ah oh boeh, tiah a thuih o.
16 “Nítorí náà, sọ fún àwọn tó wà ní ìgbèkùn pé, ‘Báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí, bó tilẹ̀ jẹ́ pé mo ti fọ́n wọn káàkiri orílẹ̀-èdè, síbẹ̀ fún ìgbà díẹ̀, èmi yóò jẹ́ ibi mímọ́ fún wọn níbi tí wọ́n lọ.’
To pongah, Angraeng Sithaw mah, Sithaw panoek ai kaminawk salakah ka haek moe, prae boih ah kang haehsak, toe akra ai ah nihcae phakhaih prae boih ah nihcae han hmuenciim ah ka oh pae han, tiah thuih.
17 “Nítorí náà, wí pé, ‘Báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí, Èmi yóò kó wọn jọ kúrò láàrín àwọn orílẹ̀-èdè tí mo fọ́n wọn ká sí, Èmi yóò sì fún wọn ní ilẹ̀ Israẹli padà.’
Angraeng Sithaw mah, Nihcae to kaminawk salak hoiah pakhueng moe, prae kruekah anghaeh kaminawk to ka tacuu let han; Israel prae to kang paek o han, tiah thuih, tiah thui paeh.
18 “Wọn yóò padà síbẹ̀, wọn yóò sì mú gbogbo àwòrán ìríra rẹ̀ àti ìbọ̀rìṣà rẹ̀ kúrò.
Nihcae loe to prae ah caeh o ueloe, kahoih ai hmuennawk hoi panuet thok hmuennawk to takhoe o boih tih.
19 Èmi yóò fún wọn ní ọ̀kankan; èmi yóò sì fi ẹ̀mí tuntun sínú wọn, Èmi yóò mú ọkàn òkúta kúrò lára wọn, èmi yóò sì fún wọn ní ọkàn tó rọ̀ bí ara ẹran.
Nihcae khaeah amkhraeng ai palungthin to ka paek moe, nangcae thungah kangtha muithla to ka suek han; nihcae thungah kaom thlung baktih kamtaak palungpathin to ka lak moe, ngan kaom palungthin to ka paek han:
20 Kí wọn le tẹ̀lé àṣẹ mi, kí wọn sì le pa òfin mi mọ́. Wọ́n yóò jẹ́ ènìyàn mi, Èmi náà yóò sì jẹ́ Ọlọ́run wọn.
to naah loe nihcae mah ka patuk ih loknawk to pazui o tih, kai ih dannawk to pakuem o ueloe, sah o tih boeh: nihcae loe Kai ih kami ah om o tih, Kai doeh nihcae ih Sithaw ah ka oh han boeh.
21 Ṣùgbọ́n fún àwọn tí wọ́n ń fi gbogbo ọkàn wọn sin àwọn àwòrán ìríra àti àwọn òrìṣà, Èmi yóò mú ẹ̀san ohun tí wọ́n ṣe wá sí orí wọn bẹ́ẹ̀ ni Olúwa Olódùmarè wí.”
Toe kahoih ai hmuennawk, panuet thok hmuennawk ah palungthin paek kaminawk loe a sak o ih hmuen baktih toengah, angmacae lu ah ka kraksak let han, tiah Angraeng Sithaw mah thuih, tiah ang thuihsak.
22 Àwọn kérúbù sì gbé ìyẹ́ wọn sókè pẹ̀lú kẹ̀kẹ́ lẹ́gbẹ̀ẹ́ wọn, ògo Ọlọ́run Israẹli sì wà lókè orí wọn.
To pacoengah cherubimnawk loe pakhraeh to atoengh o tahang, a taengah kaom rel khoknawk doeh caeh o toeng; nihcae nuiah Israel Sithaw lensawkhaih to oh.
23 Ògo Olúwa sì gòkè lọ kúrò láàrín ìlú, ó sì dúró lórí òkè tó wà ní ìlà-oòrùn ìlú náà.
Vangpui thung hoiah Angraeng lensawkhaih to angkhong tahang moe, vangpui ni angyae bang ih mae nuiah anghak.
24 Lẹ́yìn náà, Ẹ̀mí gbé mi sókè, ó sì mú mi wá sí Kaldea lójú ìran, nípa ti Ẹ̀mí Ọlọ́run sí ọ̀dọ̀ àwọn ti ìgbèkùn. Bẹ́ẹ̀ ni ìran tí mo rí lọ kúrò ní ọ̀dọ̀ mi,
Muithla mah kai ang tapom tahang, Sithaw Muithla hnuksakhaih hoiah misong ah naeh ih kaminawk suekhaih Khaldia, tiah kawk ih Babylon ah ang caeh haih. To naah ka hnuk ih hnuksakhaih to kai khae hoiah caeh tahang ving.
25 mo sì sọ gbogbo ohun tí Olúwa fihàn mí fún àwọn tó wà ní ìgbèkùn.
Angraeng mah hnuksak ih hmuennawk boih misong ah naeh ih kaminawk khaeah ka thuih pae.

< Ezekiel 11 >