< Exodus 1 >

1 Ìwọ̀nyí ni àwọn orúkọ ọmọ Israẹli tí wọ́n bá Jakọbu lọ sí Ejibiti, ẹnìkọ̀ọ̀kan pẹ̀lú ìdílé rẹ̀:
Wǝ tɵwǝndikilǝr Israil [bilǝn billǝ] Misirƣa barƣan oƣullirining isimliri (ular ⱨǝrⱪaysisi ɵz bala-qaⱪilirini elip, Yaⱪup bilǝn billǝ Misirƣa barƣanidi): —
2 Reubeni, Simeoni, Lefi àti Juda;
Rubǝn, Ximeon, Lawiy, Yǝⱨuda,
3 Isakari, Sebuluni àti Benjamini;
Issakar, Zǝbulun, Binyamin,
4 Dani àti Naftali; Gadi àti Aṣeri.
Dan, Naftali, Gad wǝ Axir.
5 Àwọn ìran Jakọbu sì jẹ́ àádọ́rin ní àpapọ̀; Josẹfu sì ti wà ní Ejibiti.
Əmdi Yaⱪupning puxtidin bolƣanlar jǝmiy bolup yǝtmix adǝm idi. Bu waⱪitta Yüsüp Misirda idi.
6 Wàyí o, Josẹfu àti gbogbo àwọn arákùnrin rẹ̀ àti gbogbo ìran náà kú,
Keyin Yüsüp, uning barliⱪ ⱪerindaxliri ⱨǝmdǝ barliⱪ zamandaxliri ɵlüp tügidi.
7 ṣùgbọ́n àwọn ará Israẹli ń bí sí i, wọ́n ń pọ̀ sí i gidigidi, wọ́n kò sì ní òǹkà tí ó fi jẹ́ pé wọ́n kún ilẹ̀ náà.
Xundaⱪtimu, Israillar kɵp tuƣulup, tez awup, intayin küqǝydi; ular zeminƣa bir kǝldi.
8 Nígbà náà ni ọba tuntun mìíràn tí kò mọ Josẹfu jẹ ní ilẹ̀ Ejibiti.
U waⱪitlarda Yüsüpni bilmǝydiƣan yengi bir padixaⱨ Misirda tǝhtkǝ qiⱪti.
9 Ó sọ fún àwọn ènìyàn rẹ̀, “Ẹ wò ó, àwọn ará Israẹli ti pọ̀ ní iye àti agbára jù fún wa.
U hǝlⱪigǝ: Mana, Israillarning hǝlⱪi bizdin ziyadǝ awup ⱨǝmdǝ bizdinmu küqlinip kǝtti.
10 Ẹ wá, ẹ jẹ́ kí a lo ọgbọ́n àlùmọ̀kọ́rọ́yí láti dá wọn lẹ́kun, bí kò ṣe bẹ́ẹ̀ wọn yóò túbọ̀ máa pọ̀ sí i. Bí ogun bá sì bẹ́ sílẹ̀, wọn yóò darapọ̀ mọ́ àwọn ọ̀tá wa, wọn yóò sì da ojú ìjà kọ wá, wọn yóò sì sá àsálà kúrò ní ilẹ̀ yìí.”
Əmdi biz ularƣa nisbǝtǝn aⱪilanǝ ix tutayli; bolmisa, ular tehimu awup ketidu, mubada urux partlap ⱪalsa, xundaⱪ boliduki, ular düxmǝnlirimiz tǝrǝpkǝ ɵtüp, bizgǝ ⱨujum ⱪilip, yurttin qiⱪip ketixi mumkin, — dedi.
11 Nítorí náà, wọ́n yan àwọn ọ̀gá akóniṣiṣẹ́ lé wọn lórí láti máa ni wọ́n lára pẹ̀lú iṣẹ́ àṣekára. Wọ́n sì kọ́ Pitomi àti Ramesesi gẹ́gẹ́ bí ìlú ìṣúra pamọ́ sí fún Farao.
Xuning bilǝn ular ularni ⱪattiⱪ ǝmgǝklǝr bilǝn harlax üqün ix baxlirini tǝyinlǝp nazarǝtqilikkǝ ⱪoydi. Xuning bilǝn Israillar Pirǝwn üqün Pitom bilǝn Raamsǝs degǝn maddiy ǝxya saⱪlaydiƣan xǝⱨǝrlǝrni yasap bǝrdi.
12 Ṣùgbọ́n bí a ti ń ni wọ́n lára tó, bẹ́ẹ̀ ni wọ́n ń pọ̀ sí i, tí wọ́n sì ń tànkálẹ̀. Nítorí náà, àwọn ará Ejibiti bẹ̀rù nítorí àwọn ará Israẹli.
Lekin ularni [ⱪanqǝ] ǝzgǝnseri, bular xunqǝ kɵpiyip ⱨǝmmǝ yǝrni ⱪaplidi; buning bilǝn misirliⱪlar Israillarƣa ɵq bolup kǝtti.
13 Àwọn ará Ejibiti sì mú àwọn ọmọ Israẹli sìn ní àsìnpa.
Xuning bilǝn misirliⱪlar Israillarƣa zulum ⱪilip, ularni tehimu ⱪattiⱪ ixlitip eƣir ixlarƣa saldi.
14 Wọ́n mú wọn gbé ìgbé ayé kíkorò nípa iṣẹ́ bíríkì àti àwọn onírúurú iṣẹ́ oko; àwọn ará Ejibiti ń lò wọ́n ní ìlòkulò.
Misirliⱪlar ularni layqiliⱪ, hix-kesǝk ⱪuyux wǝ etizlarning ⱨǝrhil ǝmgǝklirigǝ selip, ixning ⱪattiⱪliⱪi bilǝn ularning turmuxiƣa ⱪattiⱪ eƣirqiliⱪ saldi; ularni nemǝ ǝmgǝkkǝ salmisun, intayin japaliⱪ idi.
15 Ọba Ejibiti sọ fún àwọn agbẹ̀bí Heberu ti orúkọ wọn ń jẹ́ Ṣifura àti Pua pé,
Misir padixaⱨi ikki ibraniy tuƣut anisiƣa sɵz ⱪilip (ularning birining ismi Xifraⱨ, yǝnǝ birining ismi Puaⱨ idi):
16 “Nígbà ti ẹ̀yin bá ń gbẹ̀bí àwọn obìnrin Heberu, tí ẹ sì kíyèsi wọn lórí ìkúnlẹ̀ ìrọbí wọn, bí ó bá jẹ́ ọkùnrin ni ọmọ náà, ẹ pa á; ṣùgbọ́n bí ó bá jẹ́ obìnrin, ẹ jẹ́ kí ó wà láààyè.”
— silǝr ⱪaqanliki ibraniy hotunlarni tuƣdursanglar, tuƣⱪanda obdan ⱪaranglar; bowaⱪ oƣul bolsa, ɵltürüwetinglar; ⱪiz bolsa, tirik ⱪoyunglar, — dedi.
17 Ṣùgbọ́n àwọn agbẹ̀bí bẹ̀rù Ọlọ́run, wọn kò sì ṣe gẹ́gẹ́ bí ọba Ejibiti ti wí fún wọn; wọ́n jẹ́ kí àwọn ọmọkùnrin wà láààyè.
Lekin tuƣut aniliri Hudadin ⱪorⱪup, Misirning padixaⱨi ularƣa eytⱪandǝk ⱪilmay, bǝlki oƣul bowaⱪlarni tirik ⱪoydi.
18 Ọba Ejibiti pe àwọn agbẹ̀bí ó sì béèrè lọ́wọ́ wọn pé, “Èéṣe tí ẹ̀yin fi ṣe èyí? Èéṣe tí ẹ̀yin fi dá àwọn ọmọkùnrin si?”
Xunga Misirning padixaⱨi tuƣut anilirini qaⱪirtip ulardin: — Bu nemǝ ⱪilƣininglar?! Oƣul balilarni nemixⱪa tirik ⱪoydunglar? — dǝp soridi.
19 Àwọn agbẹ̀bí náà sì dá Farao lóhùn pé, “Àwọn obìnrin Heberu kò rí bí àwọn obìnrin Ejibiti, wọ́n ní agbára, wọ́n sì ti máa ń bí ọmọ kí àwọn agbẹ̀bí tó dé ọ̀dọ̀ wọn.”
Tuƣut aniliri Pirǝwngǝ jawab berip: — Ibraniy ayallar misirliⱪ ayallarƣa ohximaydu. Ular küqlük, saƣlam-timǝn bolƣini üqün tuƣut aniliri ularning ⱪexiƣa yetip barƣuqǝ, ɵzliri tuƣup bolidu, — dedi.
20 Nítorí náà Ọlọ́run ṣàánú fún àwọn agbẹ̀bí náà, àwọn ọmọ Israẹli sì ń le sí i, wọ́n sì ń pọ̀ sí i jọjọ.
Nǝtijidǝ, Huda tuƣut aniliriƣa iltipat kɵrsǝtti; Israil hǝlⱪi dawamliⱪ kɵpiyip, tehimu küqǝydi.
21 Nítorí pé àwọn agbẹ̀bí bẹ̀rù Ọlọ́run, Ọlọ́run sì fún wọn ni ìdílé tiwọn.
Xundaⱪ boldiki, tuƣut aniliri Hudadin ⱪorⱪidiƣan ihlasmǝn bolƣanliⱪi üqün Huda ularni aililik boluxⱪa muyǝssǝr ⱪildi.
22 Nígbà náà ni Farao pàṣẹ yìí fún gbogbo àwọn ènìyàn rẹ̀ pé, “Gbogbo ọmọkùnrin tí a bí ni kí ẹ gbé jù sínú odò Naili, ṣùgbọ́n gbogbo àwọn ọmọbìnrin ni kí ẹ jẹ́ kí wọn ó wà láààyè.”
Buning bilǝn Pirǝwn barliⱪ puhraliriƣa: — Israillardin yengi tuƣulƣan oƣul balilarning ⱨǝmmisini dǝryaƣa taxlanglar, lekin ⱪiz balilarning ⱨǝmmisini tirik ⱪaldurunglar, dǝp ǝmr ⱪildi.

< Exodus 1 >