< Exodus 9 >
1 Nígbà náà ni Olúwa sọ fún Mose pé, “Lọ sọ fún Farao, ‘Èyí ni Olúwa Ọlọ́run àwọn Heberu sọ, “Jẹ́ kí àwọn ènìyàn Mi kí ó lọ, kí wọn bá à lè sìn Mí.”
OLELO mai la o Iehova ia Mose, E hele oe io Parao la, a e i aku ia ia, ke olelo mai nei o Iehova ke Akua o na Hebera penei, E hookuu mai oe i ko'u poe kanaka, i hookauwa mai ai lakou na'u.
2 Bí ìwọ bá kọ̀ láti jẹ́ kí wọn ó lọ, tí ó sì dá wọn dúró.
No ka mea, ina aole oe e hookuu mai, a e hoopaa loa ia lakou,
3 Ọwọ́ Olúwa yóò mú ààrùn búburú wá sí ara ẹran ọ̀sìn nínú oko, sí ara ẹṣin, kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́, ìbákasẹ, màlúù, àgùntàn àti ewúrẹ́ yín.
Aia hoi, e kau ana no o Iehova i kona lima maluna o kau poe holoholona ma ke kula, maluna o na lio, a maluna o na hoki, a maluna o na kamelo, a maluna o na bipi, a maluna o na hipa: he ahulau nui loa.
4 Ṣùgbọ́n Olúwa yóò pààlà sí àárín ẹran ọ̀sìn tí ó jẹ́ ti Israẹli àti ti àwọn ara Ejibiti tí yóò fi jẹ́ pé kò sí ẹran ọ̀sìn ti ó jẹ́ ti ará Israẹli tí yóò kùú.’”
A e hookaawale o Iehova mawaena o na holoholona a ka Iseraela, a me na holoholona a ko Aigupita. Aole no e make kekahi mea a ka poe mamo a Iseraela.
5 Olúwa sì dá àkókò kan wí pé, “Ní ọ̀la ni Olúwa yóò ṣe èyí ni ilẹ̀ yìí.”
Haawi mai la o Iehova i wa maopopo, i mai la, Apopo e hana mai ai o Iehova i keia mea ma ka aina.
6 Olúwa sí ṣe é ni ọjọ́ kejì. Gbogbo ẹran ọ̀sìn ará Ejibiti kú, ṣùgbọ́n ẹyọ kan kò kú lára ẹran ọ̀sìn àwọn Israẹli.
A ia la iho no, hana mai la o Iehova i ua mea la, a make iho la na holoholona a pau o Aigupita: aka, o na holoholona a na mamo a Iseraela, aole kekahi i make.
7 Farao rán àwọn ènìyàn rẹ̀ láti lọ ṣe ìwádìí, wọ́n sì rí pé ẹyọ kan kò kú lára àwọn ẹran ọ̀sìn ará Israẹli. Síbẹ̀ náà, Farao kò yí ọkàn rẹ̀ padà àti pé kò jẹ́ kí àwọn ènìyàn ó lọ.
Hoouna aku la o Parao, aia hoi, aole i make kekahi o ka Iseraela poe holoholona. A na hoopaakikiia ka naau o Parao, aole ia i hookuu aku i na kanaka.
8 Nígbà náà ni Olúwa sọ fún Mose àti Aaroni, “Ẹ bu ẹ̀kúnwọ́ eérú gbígbóná láti inú ààrò, kí Mose kù ú sí inú afẹ́fẹ́ ni iwájú Farao.
Olelo mai la o Iehova ia Mose a me Aarona, E lalau olua a piha ko olua mau poho lima i ka lehu o ke kapuahi, a na Mose e lu aku ia mea ma ka lani imua o na maka o Parao.
9 Yóò sì di eruku lẹ́búlẹ́bú ni gbogbo ilẹ̀ Ejibiti, yóò sì di oówo ti ń tú pẹ̀lú ìléròrò sí ara àwọn ènìyàn àti ẹran jákèjádò gbogbo ilẹ̀ Ejibiti.”
A e lilo no ia i lepo makalii ma ka aina a pau o Aigupita, a e lilo ia i puupuu e poha ana i na maihehe, maluna o na Kanaka, a maluna o na holoholona, ma ka aina a pau o Aigupita.
10 Nígbà náà ni wọ́n bú eérú gbígbóná láti inú ààrò, wọ́n dúró ní iwájú Farao. Mose sì ku eérú náà sínú afẹ́fẹ́, ó sì di oówo tí ń tú pẹ̀lú ìléròrò ni ara àwọn ènìyàn àti lára ẹran.
Lalau ae la laua i lehu o ke kapuahi, a ku iho la imua o Parao; a lu ae la o Mose iluna i ka lani, a lilo ae la ia mea i puupuu e poha ana i na maihehe maluna o kanaka, a maluna o na holoholona.
11 Àwọn onídán kò le è dúró níwájú Mose nítorí oówo ti ó wà lára wọn àti ni ara gbogbo àwọn ara Ejibiti.
Aole i hiki i na Magoi ke ku imua o Mose, no na maihehe, no ka mea, maluna no o ka poe Magoi ua maihehe la, a maluna no o ko Aigupita a pau.
12 Ṣùgbọ́n Ọlọ́run sé ọkàn Farao le, kò sì gbọ́ ti Mose àti Aaroni, gẹ́gẹ́ bí Olúwa ti sọ fún Mose.
Hoopaakiki mai la o Iehova i ka naau o Parao, a hoolohe ole mai la oia ia laua, e like me ka Iehova i olelo mai ai ia Mose.
13 Nígbà náà ni Olúwa sọ fún Mose pé, “Dìde ni òwúrọ̀ kùtùkùtù, kí o sì tọ Farao lọ, kí o sì wí fún un pé, ‘Èyí ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run àwọn Heberu wí, Jẹ́ kí àwọn ènìyàn mi kí ó lọ, kí wọn bá à lè sìn mí,
I mai la o Iehova ia Mose, E ala ae oe i kakahiaka nui, a e ku imua o Parao, a e olelo aku ia ia, Ke i mai nei o Iehova ke Akua o ka poe Hebera penei, E hookuu mai i ko'u poe kanaka i hookauwa mai lakou na'u.
14 nítorí nígbà yìí ni èmi yóò rán àjàkálẹ̀-ààrùn ti ó ní agbára gidigidi sí ọ, sí àwọn ìjòyè rẹ àti sí àwọn ènìyàn rẹ, kí ìwọ kí ó lè mọ̀ pé, kò sí ẹni bí èmi ni gbogbo ayé.
No ka mea, ma keia hope aku, e hoouna aku no wau i ko'u mau mea hoino a pau maluna o kou naau, a maluna o kau poe kauwa, a maluna o kou poe kanaka, i ike pono ai oe, ohe mea e ae e like me au ma ka honua a pau.
15 Ó ti yẹ kí n ti na ọwọ́ mi jáde láti kọlù ọ́ àti àwọn ènìyàn rẹ pẹ̀lú ààrùn búburú ti kò bá ti run yín kúrò ni orí ilẹ̀.
No ka mea, ano e o aku ana ko'u lima, i hahau aku ai au ia oe, a me kou poe kanaka i ke ahulau, a e hookiia'e oe mai ka honua aku.
16 Ṣùgbọ́n nítorí èyí ni èmi ṣe mú ọ dúró, kí èmi kí ó le fi agbára mi hàn lára rẹ, àti kí a bá à le máa ròyìn orúkọ mi ká gbogbo ayé.
Aka, no keia mea, i hooku ae au ia oe, i mea e holke aku ai au i ko'u mana ma ou la, a i kaulana aku ai ko'u inoa ma ka honua a pau.
17 Síbẹ̀ ìwọ tún gbógun ti àwọn ènìyàn mi, ìwọ kò sì jẹ́ kí wọn lọ.
Ke hookiekie nei anei oe ia oe iho a hiki i keia wa, e ku e i ko'u poe kanaka, i ole ai e hookuu aku ia lakou?
18 Nítorí náà, ni ìwòyí ọ̀la, Èmi yóò rán òjò o yìnyín tí irú rẹ̀ kò tí i rọ̀ rí ni Ejibiti láti ìpilẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀ títí di àkókò yìí.
Aia hoi, a hiki i keia hora o ka la apopo, alaila e hooua iho no au i ka huahekili he nui loa, aole lua e like me ia ma Aigupita nei, mai kona wa i hookumuia'i a hiki i keia manawa.
19 Pàṣẹ nísinsin yìí láti kó ẹran ọ̀sìn yín àti ohun gbogbo ti ẹ ni ní pápá wá sí abẹ́ ààbò, nítorí òjò yìnyín yóò rọ̀ sí orí àwọn ènìyàn àti ẹran ti a kò kó wá sí abẹ́ ààbò tí wọ́n sì wà ni orí pápá, wọn yóò sì kú.’”
Nolaila la, e hoouna aku oe e hoakoakoa ae i kau poe holoholona a me kau mau mea a pau ma ke kula: o na kanaka a me na holoholona a pau e koe ma ke kula, aole e hoihoiia maloko o ka hale, e haule mai no ka huahekili maluna iho o lakou, a e make lakou.
20 Àwọn ti ó bẹ̀rù ọ̀rọ̀ Olúwa lára àwọn ìjòyè Farao yára lọ láti kó àwọn ẹrú àti àwọn ẹran ọ̀sìn wọn wá sí abẹ́ ààbò.
A o ka mea iwaena o na kauwa a Parao i makau i ka olelo a Iehova, hoakoakoa iho la ia i kana poe kauwa, a me kana poe holoholona iloko o na hale.
21 Ṣùgbọ́n àwọn ti kò kà ọ̀rọ̀ Olúwa sí fi àwọn ẹrú wọn àti àwọn ẹran ọ̀sìn wọn sílẹ̀ ni pápá.
A o ka mea huli ole i kona naau ma ka olelo a Iehova, waiho iho la ia i kana poe kauwa a me kana poe holoholona ma ke kula.
22 Olúwa sọ fún Mose pé, “Gbé ọwọ́ rẹ sókè sí ọ̀run kí yìnyín bá à lè rọ̀ sí orí gbogbo ilẹ̀ Ejibiti, sí orí ènìyàn àti ẹranko, àti sí orí gbogbo ohun ọ̀gbìn tí ó wà ni inú oko.”
I mai la o Iehova ia Mose, E o aku i kou lima ma ka lani, i hiki mai ai ka huahekili ma ka aina a pau o Aigupita, maluna o na kanaka, a maluna o na holoholona, a maluna o na mea uliuli a pau o ke kula, a puni ka aina o Aigupita.
23 Nígbà tí Mose gbé ọ̀pá rẹ̀ sókè sí ojú ọ̀run, Olúwa rán àrá àti yìnyín, mọ̀nàmọ́ná sì bùsi orí ilẹ̀. Olúwa rọ òjò yìnyín sí orí ilẹ̀ Ejibiti.
O aku la o Mose i kona kookoo ma ka lani; a hoouka mai la o Iehova i ke hekili a me ka huahekili, a naholo mai la ka uila maluna o ka honua; a hooua mai la o Iehova i ka huahekili maluna o ka aina o Aigupita.
24 Yìnyín rọ̀, mọ̀nàmọ́ná sì bẹ̀rẹ̀ sí bùsi orí ilẹ̀ èyí ni ó tí ì burú jù ti ó ṣẹlẹ̀ láti ìgbà ti Ejibiti ti di orílẹ̀-èdè.
He huahekili no, a ua hui pu ka uila me ka huahekili, he nui loa, aohe mea e like ai ma ka aina a pau o Aigupita, mai ka manawa i lilo ai ia i aupuni.
25 Jákèjádò gbogbo ilẹ̀ Ejibiti ni yìnyín ti pa gbogbo ohun tí ó wà ni orí pápá; ènìyàn àti ẹranko, ó wò gbogbo ohun ọ̀gbìn lulẹ̀ ó sì fa gbogbo igi ya pẹ̀lú.
Paopao mai la ka huahekili ma ka aina a pau o Aigupita, i na mea a pau ma ke kula, i na kanaka a me na holoholona: paopao mai la ka huahekili i na mea uliuli a pau o ke kula, a weluwelu iho la na laau a pau ma ke kula.
26 Ilẹ̀ Goṣeni ni ibi ti àwọn Israẹli wà nìkan ni òjò yìnyín náà kò rọ̀ dé.
O ka aina i Gosena wale no, o kahi i noho ai na mamo a Iseraela, aohe huahekili ilaila.
27 Nígbà náà ni Farao pe Mose àti Aaroni sì ọ̀dọ́ rẹ̀, ó sì wí fún wọn pé, “Èmi ti ṣẹ̀ ní àkókò yìí; Olúwa jẹ́ olódodo ṣùgbọ́n èmi àti àwọn ènìyàn mi ni aláìṣòdodo.
Hoouna mai la o Parao, hea mai la ia Mose a me Aarona, i mai la ia laua, Ua hewa no wau i keia manawa; ua hemolele o Iehova, aka, owau a me ko'u poe kanaka, ua hewa makou.
28 Èyí ti òjò yìnyín àti àrá rọ̀ yìí tó gẹ́ẹ́, gbàdúrà sí Olúwa kí ó dáwọ́ rẹ̀ dúró. Èmi yóò jẹ́ kí ẹ lọ, n kò tún ni dá a yín dúró mọ́.”
E nonoi aku olua ia Iehova, U'oki; i ole ai e kui hou ke hekili o ke Akua, a i pau hoi ka huahekili: a e hookuu aku no wau ia oukou, aole oukou e kali hou aku.
29 Mose dá a lóhùn pé, “Bí mo bá ti jáde kúrò ní àárín ìlú, èmi yóò gbé ọwọ́ mi sókè sí Olúwa, sísán àrá yóò dáwọ́ dúró, yìnyín kò sì ni rọ̀ mọ́, kí ìwọ kí ó lè mọ̀ pé Olúwa ni ó ni ilẹ̀.
I aku la o Mose ia ia, I ko'u puka ana aku mawaho o ke kulanakauhale, e kikoo aku no wau i ko'u mau lima ia Iehova; a e pau no ke hekili, aole hoi e huahekili hou, i ike ai oe, no Iehova ka honua.
30 Ṣùgbọ́n èmi mọ̀ pé síbẹ̀síbẹ̀ ìwọ àti àwọn ìjòyè rẹ kò bẹ̀rù Olúwa Ọlọ́run.”
Aka o oe, a me kau poe kauwa, ua ike no au, aole no oukou e makau i keia manawa ia Iehova ke Akua.
31 (A sì lu ọ̀gbọ̀ àti ọkà barle bolẹ̀; nítorí barle wà ní ìpẹ́, ọ̀gbọ̀ sì rudi.
A make iho la ke olona, a me ka palaoa huluhulu, no ka mea, ua pua ae la ka palaoa huluhulu, a ua pua ke olona.
32 Alikama àti ọkà ni a kò lù bolẹ̀, nítorí tí wọ́n kò tí ì dàgbà.)
Aka, o ka palaoa, a me ka palaoa eleele, aole i make, no ka mea, ua opiopio.
33 Nígbà náà ni Mose jáde kúrò ni iwájú Farao, ó kúrò ni àárín ìgboro kọjá lọ sí ẹ̀yìn odi ìlú, ó sì gbé ọwọ́ rẹ̀ sókè sí Olúwa, sísán àrá àti òjò yìnyín ti ń rọ̀ sì dáwọ́ dúró, òjò kò sì rọ̀ sí orí ilẹ̀ mọ́.
Hele aku la o Mose mawaho o ke kulanakauhale, mai o Parao aku, a kikoo aku la i kona mau lima imua o Iehova; a ua pau iho la ke hekili a me ka huahekili, aole i ninini hou ia mai ka ua maluna o ka honua.
34 Nígbà tí Farao rí i pé òjò àti yìnyín àti àrá ti ń sán ti dáwọ́ dúró, ó tún ṣẹ̀ ní ẹ̀ẹ̀kan sí i. Òun àti àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ ṣì sé àyà wọn le.
A ike iho la o Parao, ua pau ka ua, a me ke hekili, hewa hou iho la no ia, a hoopaakiki iho la i kona naau, oia a me kana poe kauwa.
35 Àyà Farao sì le, bẹ́ẹ̀ ni kò sì jẹ́ kí àwọn ọmọ Israẹli kí ó lọ, bí Olúwa ti sọ láti ẹnu Mose.
Ua hoopaakikiia ka naau o Parao, aole hoi ia i hookuu aku i na mamo a Iseraela, e like me ka Iehova i olelo mai ai ma o Mose la.