< Exodus 7 >

1 Nígbà náà ni Olúwa sọ fún Mose pé, “Wò ó, Èmi ti ṣe ọ bí Ọlọ́run fún Farao, Aaroni arákùnrin rẹ ni yóò jẹ́ agbẹnusọ rẹ.
Rəbbee Mısayk'le eyhen: – Ğu Yizın cuvab Harunule, yiğne çocule, ğana fironulqa hixhar ha'as. Mana yiğna peyğambar xhinne ixhes.
2 Ìwọ yóò sì sọ ohun gbogbo tí Èmi ti pàṣẹ fún ọ, Aaroni arákùnrin rẹ yóò sísọ fún Farao kí ó jẹ́ kí àwọn ọmọ Israẹli jáde kúrò ni ilẹ̀ rẹ̀.
Zı vak'le uvhuyn gırgın kar yiğne çocus Harunus yuşan he'e. Hasre mang'veeyid fironuk'le eyhecen İzrailybı Misirğançe g'avkeva.
3 Ṣùgbọ́n èmi yóò sé Farao lọ́kàn le. Bí Mo tilẹ̀ ṣe ọ̀pọ̀lọpọ̀ iṣẹ́ àmì àti ìyanu ni Ejibiti,
Zı fironuke hı't'iy ha'as, mang'vee, Zı Misir geed əlaamatbıyiy həşdilqamee g'ıdecuyn karbı he'eyid şol k'ırı alixhxhes deş. Manke Zı Misirılqa xıl alivka'as, yı'q'ı'n əq'übabı g'axıles, Yizın millet, İzrailybı, g'oşunbı xhinne Misirğançe qığaa'as.
4 síbẹ̀ òun kì yóò fi etí sí ọ. Nígbà náà ni Èmi yóò gbé ọwọ́ mi lé Ejibiti, pẹ̀lú agbára ìdájọ́ ńlá mi ni èmi yóò mú àwọn ènìyàn mi Israẹli jáde ní ọ̀wọ̀ọ̀wọ́.
5 Àwọn ará Ejibiti yóò sì mọ̀ pé Èmi ni Olúwa ní ìgbà tí mo bá na ọwọ́ mi jáde lé Ejibiti, tí mo sì mú àwọn ọmọ Israẹli jáde kúrò níbẹ̀.”
Zı xıl alivkav'u İzrailybı manbışde yıq'nençe qığav'umee, Misirbışik'le Zı Rəbb ıxhay ats'axhxhes!
6 Mose àti Aaroni sì ṣe gẹ́gẹ́ bí Olúwa ti pàṣẹ fún wọn.
Mıseeyiy Harunee Rəbbee nəxüdiy uvhu həməxüdud ha'an.
7 Mose jẹ́ ọmọ ọgọ́rin ọdún Aaroni sì jẹ́ ọmọ ọdún mẹ́tàlélọ́gọ́rin ni ìgbà tí wọ́n bá Farao sọ̀rọ̀.
Manbı fironuka yuşan ha'ang'a Mısayka molyts'al, Harunukad molyts'ale xhebılle sen ıxha.
8 Olúwa sọ fún Mose àti Aaroni,
Rəbbee Mısayk'leyiy Harunuk'le eyhen:
9 “Ní ìgbà tí Farao bá sọ fún un yín pé, ‘Ẹ ṣe iṣẹ́ ìyanu kan,’ sọ fún Aaroni ní ìgbà náà pé, ‘Mú ọ̀pá rẹ kí ó sì sọ ọ́ sílẹ̀ níwájú Farao,’ yóò sì di ejò.”
– Fironee şok'le uvhuyng'a: «Əlaamat hagveva», Mısee Harunuk'le eyhecen: «Yiğın əsaa alyaat'u fironne ögiylqa dağetç'e». Əsaa manke xoçelqa sak'alas.
10 Nígbà náà ni Mose àti Aaroni tọ Farao lọ, wọ́n sì ṣe bí Olúwa ti pàṣẹ fún wọn, Aaroni ju ọ̀pá rẹ̀ sílẹ̀ ní iwájú Farao àti àwọn ìjòyè rẹ̀, ọ̀pá náà sì di ejò.
Mısayiy Harun fironusqa abı, Rəbbee uvhuyn xhinne ha'a. Harunee cun əsaa fironneyiy cune insanaaşine ögiylqa dağetçumee, man xoçelqa siyk'al.
11 Farao sì pe àwọn amòye, àwọn oṣó àti àwọn onídán ilẹ̀ Ejibiti jọ, wọ́n sì fi idán wọn ṣe ohun tí Mose àti Aaroni ṣe.
Manke fironee k'oran ək'elynanbıyiy cadu ha'anbı cusqa qoot'al. Misirne cadu ha'anbışisse cadubışika man kar ha'as əxən.
12 Ẹnìkọ̀ọ̀kan wọn sọ ọ̀pá rẹ̀ sílẹ̀, ọ̀pá náà sì di ejò. Ṣùgbọ́n ọ̀pá Aaroni gbé ọ̀pá tiwọn mì.
Gırgıng'vee con əsaabı ç'iyelqa dağa'a. Dağı'iyn əsaabı xoçebışilqa siyk'al. Harunnemee əsaan gırgın əsaabı k'öğənbı.
13 Síbẹ̀ ọkàn Farao sì yigbì, kò si fetí sí wọn gẹ́gẹ́ bí Olúwa ti sọ.
Rəbbe uvhuyn eyxhe, firon hı't'iyra ıxha, mang'vee manbışil k'ırı iliyxhe deş.
14 Nígbà náà ni Olúwa sọ fún Mose pé, “Ọkàn Farao ti di líle, ó kọ̀ láti jẹ́ kí àwọn ènìyàn náà ó lọ.
Rəbbe Mısayk'le eyhen: – Firon hı't'iyra vor, mang'us millet g'aykkas ıkkan deşod.
15 Tọ Farao lọ ni òwúrọ̀ kùtùkùtù bí ó ti ń lọ sí etí odò, dúró ni etí bèbè odò Naili láti pàdé rẹ, mú ọ̀pá rẹ tí ó di ejò ni ọwọ́ rẹ.
G'iyqa miç'eer firon damaysqa ı'qqəmee xoçelqa siyk'alan əsaayid alyaat'u ğu mang'usqa hak'ne. Mana Niline mıglek gozete'e.
16 Sọ fún un pé, ‘Olúwa Ọlọ́run àwọn Heberu rán mi sí ọ láti sọ fún ọ pé, Jẹ́ kí àwọn ènìyàn mi kí ó lọ, kí wọn kí ó lè sìn mi ni aginjù. Ṣùgbọ́n títí di àkókò yìí, ìwọ kò gba.
G'acumee fironuk'le eyhe: «Rəbbee, cühüt'yaaşine Allahee in eyhesva zı vasqa g'axuvu: Cun millet g'aykke sahree Cus ı'bəədat he'ecen! Ğu həşdilqamee k'ırı alixhxhı deş.
17 Èyí ni Olúwa wí, nípa èyí ni ìwọ yóò mọ̀ pé Èmi ni Olúwa. Wò ó, èmi yóò fi ọ̀pá ti ó wà ní ọwọ́ mi, èmi yóò ná omi tí ó wà nínú odò Naili yóò sì di ẹ̀jẹ̀.
Rəbbevud eyhe: Həşde vak'le ats'axhxhesın Mana Rəbb ıxhay. Yizde xılene əsaaka zı Niline xhyanıs ı'xı'mee xhyan ebalqa sak'alas.
18 Àwọn ẹja tí ó wà nínú odò Naili yóò kú, odò náà yóò sì máa rùn, àwọn ará Ejibiti kò sì ni lè mu omi rẹ̀.’”
Nileedın balığar hatt'asınbı, əq'ı'yn eva qales, Misirğançenbışisse mançe xhyan ulyoğas əxəs deş».
19 Olúwa sọ fún Mose, “Sọ fún Aaroni, ‘Mú ọ̀pá rẹ kí ó sì na ọwọ́ rẹ jáde lórí àwọn omi Ejibiti. Lórí àwọn odò kéékèèké àti odò ńlá, lórí àbàtà àti adágún omi, wọn yóò sì di ẹ̀jẹ̀.’ Ẹ̀jẹ̀ yóò wà ni ibi gbogbo ni Ejibiti, àní nínú ọpọ́n àti nínú kete omi àti nínú ìkòkò tí a pọn omi sí nínú ilé.”
Rəbbee meed Mısayk'le eyhen: – Harunuk'le inəxüd eyhe: əsaa alyaat'u, xıl Misirne damabışilqa, arxbışilqa, g'oleeşilqa, gırgıne xhyan havacene cigabışilqa hotkecen. Maadın gırgın xhyan ebalqa sak'alas. Q'uvayned, g'ayeyned g'abbışee gırgınəəng'ə Misir eb vuxhes.
20 Mose àti Aaroni sí ṣe gẹ́gẹ́ bí Olúwa ti pàṣẹ fún wọn. Ó gbé ọ̀pá rẹ̀ sókè ni iwájú Farao àti àwọn ìjòyè rẹ̀, ó sì lu omi odò Naili, omi odò náà sì yípadà sí ẹ̀jẹ̀.
Mıseeyiy Harunee gırgın Rəbbee cok'le uvhuyn xhinne ha'a. Harunee fironneyiy cune insanaaşine ögiyl əsaa ooqa qı'ı Nileene xhines ı'xı'mee, gırgın xhyan ebalqa siyk'al.
21 Ẹja inú odò Naili sì kú, odò náà ń rùn gidigidi tí ó fi jẹ́ pé àwọn ará Ejibiti kò le è mu omi inú rẹ̀. Ẹ̀jẹ̀ sì wà ni ibi gbogbo ni ilẹ̀ Ejibiti.
Nileedın baluğar haat'anbı, mançe məxdun əq'ı'yn eva g'əə giyğal, Misirbışisse mançe xhyan ulyoğas əxə deş. Misir gırgınəəng'ə eb vuxha.
22 Ṣùgbọ́n àwọn apidán ilẹ̀ Ejibiti sì ṣe bákan náà pẹ̀lú agbára òkùnkùn wọn, ọkàn Farao sì yigbì síbẹ̀ kò sì fetí sí wọn gẹ́gẹ́ bí Olúwa ti sọ.
Misirne cadu ha'anbışissed caduyka man kar ha'as əxən. Firon hı't'iyra ıxha, Rəbbee uvhuyn xhinne, mang'vee Mısaylil Harunul k'ırı iliyxhe deş.
23 Dípò bẹ́ẹ̀, ó yíjú padà, ó sì lọ sí ààfin rẹ̀, kò sì jẹ́ kí àwọn nǹkan wọ̀nyí wà ni oókan àyà rẹ̀.
Fironee man yik'eeqa ıkkeka deş, sark'ıl cune sareeqa ayk'an.
24 Nígbà náà ni gbogbo àwọn ará Ejibiti bẹ̀rẹ̀ sí í gbẹ́ etí odò Naili láti wá omi tí wọn yóò mu, nítorí wọn kò le è mu omi tí ó wà nínú odò náà.
Misirbışe Niline hiqiy-alla kahrızbı iliykar ulyoğasın xhyan t'abal ha'a. Manbışisse dameençe ulyoğas əxə deş.
25 Ọjọ́ méje sì kọjá ti Olúwa ti lu odò Naili.
Rəbbee damalqa ver ablyav'uyn yighılle yiğ eyxhe.

< Exodus 7 >