< Exodus 7 >
1 Nígbà náà ni Olúwa sọ fún Mose pé, “Wò ó, Èmi ti ṣe ọ bí Ọlọ́run fún Farao, Aaroni arákùnrin rẹ ni yóò jẹ́ agbẹnusọ rẹ.
I MAI la o Iehova ia Mose, e nana hoi, ua hoonoho wau ia oe i akua no Parao, a o Aarona kou kaikuaana, oia no auanei kou kaula.
2 Ìwọ yóò sì sọ ohun gbogbo tí Èmi ti pàṣẹ fún ọ, Aaroni arákùnrin rẹ yóò sísọ fún Farao kí ó jẹ́ kí àwọn ọmọ Israẹli jáde kúrò ni ilẹ̀ rẹ̀.
O na mea a pau a'u e kauoha aku ai ia oe, oia kau e hai aku ai: a o Aarona kou kaikuaana ke olelo aku ia Parao, e hoouna aku ia i na mamo a Iseraela mai kona aina aku.
3 Ṣùgbọ́n èmi yóò sé Farao lọ́kàn le. Bí Mo tilẹ̀ ṣe ọ̀pọ̀lọpọ̀ iṣẹ́ àmì àti ìyanu ni Ejibiti,
A e hoopaakiki auanei au i ka naau o Parao, a e hana no au i ko'u mau ouli a nui, a me ko'u mau mea mana ma ka aina o Aigupita.
4 síbẹ̀ òun kì yóò fi etí sí ọ. Nígbà náà ni Èmi yóò gbé ọwọ́ mi lé Ejibiti, pẹ̀lú agbára ìdájọ́ ńlá mi ni èmi yóò mú àwọn ènìyàn mi Israẹli jáde ní ọ̀wọ̀ọ̀wọ́.
Aole nae e hoolohe mai o Parao ia olua, i kau aku ai au i ko'u lima maluna o Aigupita, a e lawe mai iwaho i ko'u poe kaua i ka poe kanaka o'u, i na mamo a Iseraela, mai ka aina o Aigupita mai, me ka hoopai nui aku.
5 Àwọn ará Ejibiti yóò sì mọ̀ pé Èmi ni Olúwa ní ìgbà tí mo bá na ọwọ́ mi jáde lé Ejibiti, tí mo sì mú àwọn ọmọ Israẹli jáde kúrò níbẹ̀.”
A e ike auanei ko Aigupita, owau no Iehova, ia'u e hookakauha aku ai i ko'u lima maluna o Aigupita, a e lawe mai i na mamo a Iseraela maiwaena mai o lakou.
6 Mose àti Aaroni sì ṣe gẹ́gẹ́ bí Olúwa ti pàṣẹ fún wọn.
Hana iho la o Mose laua o Aarona, e like me ka Iehova i kauoha mai ai ia laua; pela laua i hana aku ai.
7 Mose jẹ́ ọmọ ọgọ́rin ọdún Aaroni sì jẹ́ ọmọ ọdún mẹ́tàlélọ́gọ́rin ni ìgbà tí wọ́n bá Farao sọ̀rọ̀.
He kanawalu na makahiki o Mose, a he kanawalu na makahiki o Aarona a me kumamakolu, i ka wa a laua i olelo aku ai ia Parao.
8 Olúwa sọ fún Mose àti Aaroni,
Olelo mai la o Iehova ia Mose a me Aarona, i mai la,
9 “Ní ìgbà tí Farao bá sọ fún un yín pé, ‘Ẹ ṣe iṣẹ́ ìyanu kan,’ sọ fún Aaroni ní ìgbà náà pé, ‘Mú ọ̀pá rẹ kí ó sì sọ ọ́ sílẹ̀ níwájú Farao,’ yóò sì di ejò.”
I ka wa e olelo mai ai o Parao ia olua, i ka i ana mai, E hoike mai olua i kekahi hana mana; alaila e olelo ae oe ia Aarona, E lalau i kou kookoo, a e kiola iho imua o Parao, a e lilo ia i nahesa:
10 Nígbà náà ni Mose àti Aaroni tọ Farao lọ, wọ́n sì ṣe bí Olúwa ti pàṣẹ fún wọn, Aaroni ju ọ̀pá rẹ̀ sílẹ̀ ní iwájú Farao àti àwọn ìjòyè rẹ̀, ọ̀pá náà sì di ejò.
Hele aku la o Mose laua o Aarona io Parao la, hana iho la laua e like me ke kauoha ana a Iehova, a kiola iho la o Aarona i kona kookoo imua o Parao, a imua o kana poe kauwa, a lilo iho la ia i nahesa.
11 Farao sì pe àwọn amòye, àwọn oṣó àti àwọn onídán ilẹ̀ Ejibiti jọ, wọ́n sì fi idán wọn ṣe ohun tí Mose àti Aaroni ṣe.
Kii aku la hoi o Parao i na kanaka akamai, a me na kilo; a o na magoi o Aigupita, hana iho la hoi lakou pela, i ko lakou kilokilo ana.
12 Ẹnìkọ̀ọ̀kan wọn sọ ọ̀pá rẹ̀ sílẹ̀, ọ̀pá náà sì di ejò. Ṣùgbọ́n ọ̀pá Aaroni gbé ọ̀pá tiwọn mì.
No ka mea, kiola iho la kela kanaka keia kanaka a pau i kona kookoo iho, i lilo lakou i mau nahesa: aka, o ke kookoo o Aarona, moni iho la ia i ko lakou mau kookoo.
13 Síbẹ̀ ọkàn Farao sì yigbì, kò si fetí sí wọn gẹ́gẹ́ bí Olúwa ti sọ.
A hoopaakikiia mai la ka naau o Parao, i hoolohe ole ai oia ia laua, e like me ka mea a Iehova i olelo mai ai.
14 Nígbà náà ni Olúwa sọ fún Mose pé, “Ọkàn Farao ti di líle, ó kọ̀ láti jẹ́ kí àwọn ènìyàn náà ó lọ.
I mai la o Iehova ia Mose, Ua hoopaakikiia ko Parao naau, i ole ai ia e hookuu mai i ka poe kanaka.
15 Tọ Farao lọ ni òwúrọ̀ kùtùkùtù bí ó ti ń lọ sí etí odò, dúró ni etí bèbè odò Naili láti pàdé rẹ, mú ọ̀pá rẹ tí ó di ejò ni ọwọ́ rẹ.
A kakahiaka ae, e hele oe io Parao la, aia e hele ana no ia i ka wai; e ku oe ma ke kapa o ka muliwai e halawai me ia: a e lawe oe ma kou lima i ke kookoo i lilo ai i nahesa.
16 Sọ fún un pé, ‘Olúwa Ọlọ́run àwọn Heberu rán mi sí ọ láti sọ fún ọ pé, Jẹ́ kí àwọn ènìyàn mi kí ó lọ, kí wọn kí ó lè sìn mi ni aginjù. Ṣùgbọ́n títí di àkókò yìí, ìwọ kò gba.
A e olelo aku oe ia ia, Ua hoouna mai nei ke Akua o ka poe Hebera ia'u ion nei, ua i mai, E hookuu mai oe i ko'u poe kanaka, i hookauwa mai lakou na'u ma ka waonahele: aia hoi, aole oe i manao e hoolohe mamua.
17 Èyí ni Olúwa wí, nípa èyí ni ìwọ yóò mọ̀ pé Èmi ni Olúwa. Wò ó, èmi yóò fi ọ̀pá ti ó wà ní ọwọ́ mi, èmi yóò ná omi tí ó wà nínú odò Naili yóò sì di ẹ̀jẹ̀.
Ke olelo mai nei o Iehova penei, Ma keia mea e ike auanei oe, owau no Iehova: aia hoi, e hahau no wau i keia kookoo ma kuu lima, maluna o ka wai maloko o ka muliwai, a e lilo ia i koko.
18 Àwọn ẹja tí ó wà nínú odò Naili yóò kú, odò náà yóò sì máa rùn, àwọn ará Ejibiti kò sì ni lè mu omi rẹ̀.’”
A e make no ka ia maloko o ka muliwai, a e hoopailua ko Aigupita ke inu i ka wai o ka muliwai.
19 Olúwa sọ fún Mose, “Sọ fún Aaroni, ‘Mú ọ̀pá rẹ kí ó sì na ọwọ́ rẹ jáde lórí àwọn omi Ejibiti. Lórí àwọn odò kéékèèké àti odò ńlá, lórí àbàtà àti adágún omi, wọn yóò sì di ẹ̀jẹ̀.’ Ẹ̀jẹ̀ yóò wà ni ibi gbogbo ni Ejibiti, àní nínú ọpọ́n àti nínú kete omi àti nínú ìkòkò tí a pọn omi sí nínú ilé.”
I mai la o Iehova ia Mose, E olelo aku oe ia Aarona, E lalau oe i kou kookoo, a e o aku kou lima maluna o na wai o Aigupita, ma na kahawai, a ma na muliwai, a ma na loko, a ma na huinawai a pau o lakou, i lilo ai lakou i koko: i hiki mai ke koko ma na aina a pau o Aigupita nei, maloko o ka laau, a maloko o ka pohaku.
20 Mose àti Aaroni sí ṣe gẹ́gẹ́ bí Olúwa ti pàṣẹ fún wọn. Ó gbé ọ̀pá rẹ̀ sókè ni iwájú Farao àti àwọn ìjòyè rẹ̀, ó sì lu omi odò Naili, omi odò náà sì yípadà sí ẹ̀jẹ̀.
A hana iho la o Mose laua o Aarona e like me ka mea a Iehova i olelo mai ai. Hapai ae la ia i ke kookoo a hahau iho la i ka wai maloko o ka muliwai, imua i ke alo o Parao, a imua i ke alo o kana poe kauwa: a lilo ae la ka wai a pau o ka muliwai i koko.
21 Ẹja inú odò Naili sì kú, odò náà ń rùn gidigidi tí ó fi jẹ́ pé àwọn ará Ejibiti kò le è mu omi inú rẹ̀. Ẹ̀jẹ̀ sì wà ni ibi gbogbo ni ilẹ̀ Ejibiti.
A make iho la ka ia maloko o ka muliwai; pilau mai la ka muliwai; aole i hiki i ko Aigupita ke inu i ka wai o ua muliwai la: a he koko no ma ka aina o Aigupita a pau.
22 Ṣùgbọ́n àwọn apidán ilẹ̀ Ejibiti sì ṣe bákan náà pẹ̀lú agbára òkùnkùn wọn, ọkàn Farao sì yigbì síbẹ̀ kò sì fetí sí wọn gẹ́gẹ́ bí Olúwa ti sọ.
Hana iho la no pela na magoi o Aigupita i ko lakou mea e kilokilo ai; a ua hoopaakikiia ka naau o Parao, aole hoi ia i hoolohe mai ia laua, e like no me ka mea a Iehova i olelo mai ai.
23 Dípò bẹ́ẹ̀, ó yíjú padà, ó sì lọ sí ààfin rẹ̀, kò sì jẹ́ kí àwọn nǹkan wọ̀nyí wà ni oókan àyà rẹ̀.
Huli ae la o Parao, a hoi aku la i kona hale; aole hoi ia i kau aku i kona manao ma ia mea.
24 Nígbà náà ni gbogbo àwọn ará Ejibiti bẹ̀rẹ̀ sí í gbẹ́ etí odò Naili láti wá omi tí wọn yóò mu, nítorí wọn kò le è mu omi tí ó wà nínú odò náà.
Kohi iho la ko Aigupita a pau i na wahi e kokoke ana i ka muliwai, i loaa'i ka wai e inu: no ka mea, aole i hiki ia lakou ke inu i ka wai o ka muliwai.
25 Ọjọ́ méje sì kọjá ti Olúwa ti lu odò Naili.
A ua hala ae la na la ehiku mai ka wa mai o ko Iehova hahau ana i ka muliwai.