< Exodus 6 >

1 Nígbà náà ní Olúwa sọ fún Mose pé, “Ní ìsin yìí, ìwọ yóò rí ohun tí èmi yóò ṣe sí Farao pẹ̀lú ọwọ́ agbára ńlá mi ni yóò fi jẹ́ kí wọn lọ; pẹ̀lú ọwọ́ agbára ńlá mi, òun yóò lé wọn jáde kúrò ní orílẹ̀-èdè rẹ̀.”
Hichun Pakaiyin Mose henga aseiyin, “Tua hi keiman Pharoah chung'a ipi ka bol'am namu ding ahi. Aman ka ban thahatna ahin hetdoh teng, aman mipi ho chu ahinsol doh ding ahi. Dih tah a, aman namphu a agamsung dalha dinga ahin soldoh ding'u ahi!”
2 Ọlọ́run sì tún sọ fún Mose pé, “Èmi ni Olúwa.
Chule Pathen in Mose henga aseiyin, “Keima Yahweh - 'Pakai' kahi.
3 Mo fi ara hàn Abrahamu, Isaaki àti Jakọbu bí Ọlọ́run alágbára, ṣùgbọ́n nípa orúkọ mi Olúwa, Èmi kò fi ara mi hàn wọ́n.
Abraham henga, Isaac henga, chule Jacob henga El-Shaddai - 'Hatchungnung Pathen' - aheng uva ka kilah in ahi, hinlah kamin, Yaweh, ahi ti amaho heng'a kaphong doh poi.
4 Èmí sì tún fi ìdí májẹ̀mú mi múlẹ̀ pẹ̀lú wọn láti fún wọn ní ilẹ̀ Kenaani, ilẹ̀ tí wọn gbé gẹ́gẹ́ bí àjèjì.
Chule kholjin miho banga achen nau gam, Canaan gam peh dinga kakitep na keiman amaho toh avel'in namdet na kanei kit in ahi.
5 Èmi sì ti tún gbọ́ kíkùn àwọn ọmọ Israẹli àwọn tí àwọn ará Ejibiti mú gẹ́gẹ́ bí ẹrú, àti pé èmi sì ti rántí májẹ̀mú mi.
Israel mite, tua Egypt mite soh a pang ho thohgim na kaja nai ti hi naginchat mong thei ahi. Chule amaho toh ka kitepna jong phatah in kahe jing nai.
6 “Sọ fún àwọn ará ilé Israẹli, ‘Èmi ni Olúwa, Èmi yóò sọ yín di òmìnira kúrò nínú àjàgà àwọn ará Ejibiti. Èmi yóò sì gbà yín sílẹ̀ kúrò ní oko ẹrú wọn. Èmi yóò dá a yín sílẹ̀ pẹ̀lú apá nínà (àwọn iṣẹ́ ìyanu) àti pẹ̀lú ìdájọ́ ńlá.
“Hijeh chun, Israel mite henga seiyin: 'Keima Pakai kahi. Egypt gam'a nasoh tan nauva kon'a kahuhdoh ding chule nathoh gimnauva kon'a kalha ong ding nahiuve. Keiman nangho ban thahat tah le thutan'a gimnei tah a kalhatdam ding nahiuve.
7 Èmi yóò mú un yín bí ènìyàn mi, èmi yóò sì jẹ́ Ọlọ́run yín. Nígbà náà ni ẹ̀yin yóò mọ̀ pé, èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín, ẹni tí ó mú un yín jáde kúrò nínú àjàgà àwọn ará Ejibiti.
Keima mite nahi mong'uve tia kachu dingu, chule na Pathen'u kahi ding ahi. Chuteng keima hi nangho Pakai na Pathen'u Egypt gamma nathoh gim nauva kon'a nahin lha ong pau chu kahi nahin hetdoh dingu ahi.
8 Èmi yóò mú un yín wá ilẹ̀ náà ti èmi ti búra pẹ̀lú ìgbọ́wọ́sókè láti fi fún Abrahamu. Isaaki àti Jakọbu. Èmi yóò fi fún un yín bí ohun ìní, Èmi ni Olúwa.’”
Keiman Abraham, Isaac, chuleh Jacob heng'a kakihahsel na gam'a chu ka puilut ding na hiuve. Nangho goulo ding mong monga kapeh ding nahiuve. Keima Pakai kahi!'”
9 Mose sì sọ èyí fún àwọn ará Israẹli, ṣùgbọ́n wọn kò fi etí sílẹ̀ sí Mose nítorí ọkàn wọn tó rẹ̀wẹ̀sì àti nítorí ìgbèkùn búburú bí ohun tí ó ti kọ́ sọ kó wọn sí ní oko ẹrú wọn.
Pakaiyin asei bang'in Mose in jong Israel mite heng'a asei peh in, ahinlah amahon avel'in angainom tapouvin ahi. Ajeh chu amaho asoh channauva aki sugim'u chun alungphatmo sah val tauvin ahi.
10 Nígbà náà ni Olúwa sọ fún Mose.
Chuin Pakaiyin Mose heng'a aseiyin,
11 “Lọ, sọ fún Farao ọba Ejibiti pé kí ó jẹ́ kí àwọn ará Israẹli lọ kúrò ní orílẹ̀-èdè rẹ̀.”
“Egypt lengpa Pharaoh heng'a leche in lang, Israel miten nagamsung dalha tauhen tin aheng'a gaseiyin.”
12 Ṣùgbọ́n Mose sọ fún Olúwa pé, “Nígbà ti àwọn ará Israẹli tó jẹ́ ènìyàn mi kó fetí sí ọ̀rọ̀ mi, báwo ni Farao yóò ṣe fetí sí ọ̀rọ̀ mi, nígbà ti mo jẹ́ akólòlò?”
“Ahinlah Pakai!” Mose anompon, “Ka miten kathusei eingaipeh tapouvintin. Iti Pharaoh in ka thu ngai mong nante tia kakinep ding ham? Keima mipaomo kahi.”
13 Olúwa bá ìran Mose àti Aaroni sọ̀rọ̀ nípa àwọn ará Israẹli àti Farao ọba Ejibiti, ó pàṣẹ fún wọn pé kí wọn kó àwọn Israẹli jáde kúrò ni ilẹ̀ Ejibiti.
Ahivangin Pakaiyin Mose leh Aaron heng'a thu aseiyin Israelte ding leh Egypt lengpa Pharaoh ding'a abol lhonding ho ape lhon'in, Pakaiyin Israelte Egypt akon puidoh ding'in Mose leh Aaron thupeh anei tan ahi.
14 Wọ̀nyí ni olórí ìran wọn: àwọn ọmọ Reubeni àkọ́bí Israẹli ni: Hanoku, Pallu, Hesroni àti Karmi. Àwọn wọ̀nyí ni ìdílé Reubeni.
Hichengse hi apu apate'u khang chedol'a Israel insung upa ho ahi: Israel insung'a apeng masapen Reuben chapate se chu: Hanoch, Pallu, Hezron, chule Carmi. Amaho chilhahse hi Reuben insung kon ahitauve.
15 Àwọn ọmọ Simeoni ni: Jemueli, Jamini, Ohadi, Jakini, Sohari àti Saulu ọmọ obìnrin Kenaani. Àwọn wọ̀nyí ni ìran Simeoni.
Simeon chapate se chu: Jemuel, Jamin, Ohad, Jakin, Zohar leh Shaul ahiuve. (Shaul hingnu vangchu Canaan numei ahi.) Amaho chilhahse hi Simeon insung kon ahitauve.
16 Ìwọ̀nyí ni orúkọ àwọn ọmọ Lefi gẹ́gẹ́ bí àkọsílẹ̀ wọn: Gerṣoni, Kohati àti Merari. Lefi lo ẹ̀tàdínlógóje ọdún láyé.
Levi chilhahte se amaho insung minbu dungjuiya achapate chu: Gershon, Kohath leh Merari. (Levi chu kum ja le somthum le sagi ana hing'e).
17 Àwọn ọmọ Gerṣoni ni ìran wọn ni: Libni àti Ṣimei.
Gershon chihahte chu Libni leh Shimei ahi lhonne. Anigel lhonin insung khangguiyin akisim lhon tan ahi.
18 Àwọn ọmọ Kohati ni: Amramu, Isari, Hebroni àti Usieli. Kohati lo ẹ̀tàléláádóje ọdún láyé.
Kohath chilhahte chu Amram, Izhar, Hebron leh Uzziel ahi. (Kohath chu kum ja le somthum le thum ana hing'e.)
19 Àwọn ọmọ Merari ni: Mahili àti Muṣi. Ìwọ̀nyí ni ìran Lefi gẹ́gẹ́ bí àkọsílẹ̀ wọn.
Merari chilhahte chu: Mahli leh Mushi ahi lhon'e. Ama ho chengse hi Levi insung chedol minbua amin cheh uchu ahi.
20 Amramu sì fẹ́ Jokebedi arábìnrin baba rẹ̀ ní ìyàwó. Jokebedi sì bí Aaroni àti Mose fún un. Amramu lo ẹ̀tàdínlógóje ọdún láyé.
Amram chun apa sopinu Jochebed chu jin aneiyin, amanun chapa ahin peh in, Aaron leh Mose ahi lhon'e. (Amram chu kum jale somthum le sagi ana hing'e.)
21 Àwọn ọmọ Isari ni: Kora, Nefegi àti Sikri.
Izhar chapate chu Korah, Nepheg leh Zicri ahiuve.
22 Àwọn ọmọ Usieli ni: Miṣaeli, Elsafani àti Sitiri.
Uzziel chapate chu, Mishael, Elzaphan leh Sithri ahiuve.
23 Aaroni fẹ́ Eliṣeba ọmọbìnrin Amminadabu tí í ṣe arábìnrin Nahiṣoni, ó sì bí Nadabu, Abihu, Eleasari àti Itamari.
Aaron in Elisheba aki chenpin, amachu Amminadab chanu chule Nahson ding'a asopinu ahi. Amanun chapa ahindoh ho chu Nadab, Abihu, Eleazar leh Ithamar ahiuve.
24 Àwọn ọmọ Kora ni: Asiri, Elkana àti Abiasafu. Ìwọ̀nyí ni ìran Kora.
Korah chapate hochu Assir, Elkanah leh Abiasaph ahiuvin, amaho chilhah hi Korah insung mi ahitauve.
25 Eleasari ọmọ Aaroni fẹ́ ọ̀kan lára àwọn ọmọbìnrin Putieli ní ìyàwó, ó sì bí Finehasi fún un. Ìwọ̀nyí ni olórí àwọn Lefi ni ìdílé ìdílé.
Aaron chapa Eleazar chun Putiel chanute lah a khat ji in aneiyin, chuin amanun chapa khat ahing'in Phinehas ahi. Amaho chenghi Levi insung'a pu le pate ho insung bahkai dungjuiya chengse chu ahiuve.
26 Aaroni àti Mose yìí kan náà ni Olúwa sọ fún pé, “Ẹ kó àwọn ará Israẹli jáde kúrò ni ilẹ̀ Ejibiti ní ìsọ̀rí ìsọ̀rí.”
Aaron leh Mose hichelaiya kimin phah teni mama hi ahilhon'e Pakaiyin ajah lhon'a, “Israel mite chu Egypt gamma kon in sepoyte bang'in hin lamkai lhon in,” tia asei chu.
27 Àwọn ni ó bá Farao ọba Ejibiti sọ̀rọ̀ nípa kíkó àwọn ará Israẹli jáde kúrò ni Ejibiti, àní Mose àti Aaroni yìí kan náà ni.
Egypt lengpa, Pharaoh koma Israel mite Egypt gam'a konna puidoh ding'a thu sei chu, Mose leh Aaron ahi lhon'e.
28 Nígbà tí Olúwa bá Mose sọ̀rọ̀ ni Ejibiti,
Egypt gam'a Pakaiyin Mose ahoulimpi achun,
29 Olúwa sì sọ fún Mose pé, “Èmi ni Olúwa. Sọ ohun gbogbo ti mo ti sọ fún ọ fún Farao ọba Ejibiti.”
Aheng'a aseiyin, “Keima Pakai kahi! Egypt lengpa, Pharaoh henga seiyin, keiman naheng'a kasei jouse chu.”
30 Ṣùgbọ́n Mose sì wí ní iwájú Olúwa pé, “Níwọ́n ìgbà ti mo jẹ́ akólòlò, ọ̀nà dà ti Farao yóò ṣe fi etí sí mi?”
Ahinlah Mose in Pakai akinel pin, aseiyin, “Hichu ka bolthei lou ding ahi! ajeh chu keima mipaomo kahi! Ipi jeh a Pharaoh in ka thusei angai ding ham?” ati.

< Exodus 6 >