< Exodus 5 >

1 Lẹ́yìn náà ni Mose àti Aaroni tọ Farao lọ, wọ́n sì wí pé, “Èyí ni ohun tí Olúwa, Ọlọ́run Israẹli sọ, ‘Jẹ́ kí àwọn ènìyàn mi kí ó lọ, kí wọn kí ó lè ṣe àjọ mi ní ijù.’”
Te phoeiah Moses neh Aaron te cet rhoi tih Pharaoh te, “Israel Pathen BOEIPA loh, ‘Ka pilnam he hlah lamtah khosoek kah kamah taengah lam uh saeh,’ a ti,” a ti nah rhoi.
2 Farao dáhùn wí pé, “Ta ni Olúwa, tí èmi yóò fi gbọ́rọ̀ sí i lẹ́nu, tí èmi yóò fi jẹ́ kí Israẹli ó lọ? Èmi kò mọ Olúwa, èmi kò sì ní jẹ́ kí Israẹli ó lọ.”
Tedae Pharaoh loh, “U BOEIPA nim a ol te ngai vetih Israel te ka hlah eh? BOEIPA te ka ming pawt dongah Israel te ka hlah mahpawh,” a ti nah.
3 Lẹ́yìn náà ni wọ́n wí pé, “Ọlọ́run àwọn Heberu tí pàdé wa. Ní ìsinsin yìí, jẹ́ kí a lọ ní ìrìn ọjọ́ mẹ́ta sínú aginjù láti rú ẹbọ sí Olúwa Ọlọ́run wa, kí Ó má ba á fi àjàkálẹ̀-ààrùn tàbí idà bá wa jà.”
Te phoeiah, “Hebrew rhoek kah Pathen loh kaimih te n'doe. Longpuei hnin thum caeh kah khosoek ah ka cet uh mai eh. BOEIPA ka Pathen te ka nawn uh pawn eh. Kaimih he duektahaw neh, cunghang neh n'cuuk tarha ve,” a ti nah rhoi.
4 Ṣùgbọ́n ọba Ejibiti sọ wí pé, “Mose àti Aaroni, èéṣe ti ẹ̀yin fi mú àwọn ènìyàn kúrò lẹ́nu iṣẹ́ wọn? Ẹ padà sẹ́nu iṣẹ́ yín.”
Tedae Egypt manghai loh amih rhoi te, “Moses neh Aaron, balae tih pilnam te a bitat na hlahpham sak, namah bi la cet,” a ti nah.
5 Nígbà náà ni Farao sọ pé, “Ẹ wò ó àwọn ènìyàn náà ti pọ̀ sí ì nílẹ̀ yìí ní ìsinsin yìí, ẹ̀yin sì ń dá wọn dúró láti máa bá iṣẹ́ lọ.”
Te vaengah Pharaoh loh, “Khohmuen pilnam loh yet coeng tih amamih khaw a bitloh lamkah na kangkuen sak ke,” a ti.
6 Ní ọjọ́ yìí kan náà ni Farao pàṣẹ fún àwọn akóniṣiṣẹ́ àti àwọn ti ń ṣe alábojútó iṣẹ́ lórí àwọn ènìyàn.
Te khohnin ah tah Pharaoh loh pilnam sokah aka tueihno rhoek neh a rhoiboei rhoek te a uen.
7 “Ẹ̀yin kò ní láti pèsè koríko gbígbẹ fún bíríkì sísun mọ́ fún àwọn ènìyàn wọ̀nyí; ẹ jẹ́ kí wọn máa wá koríko gbígbẹ fún ara wọn.
“Hlaem hlaemvai kah bangla laiboeng aka saii pilnam te cangkong paek ham vaengah koei pa uh boeh. Amamih cet uh saeh lamtah amamih ham cangkong te coi uh saeh.
8 Ṣùgbọ́n ẹ jẹ́ kí wọn ó ṣe iye bíríkì kan náà bí ì ti àtẹ̀yìnwá, kí ẹ má ṣe dín iye rẹ̀ kú. Ọ̀lẹ ni wọ́n, ìwà ọ̀lẹ yìí náà ló mú wọn pariwo pé, ‘Ẹ jẹ́ kí a lọ, kí a sì rú ẹbọ sí Ọlọ́run wa.’
Tedae laiboeng kah a lan a tang tah amih taengah hlaem hlaemvai kah, a saii bangla khueh uh lamtah yueh pah boeh. A duem uh ham tangloeng ni pang uh tangkhuet tih, ‘Ka Pathen te nawn ham ka cet ni,’ a ti uh.
9 Ẹ mú iṣẹ́ náà le fún wọn, kí wọn bá a le è tẹramọ́ iṣẹ́ wọn, ẹ má fi ààyè gba irọ́ wọn.”
Hlang rhoek ham thohtatnah loh a nan daengah ni te te a saii uh vetih laithae ol taengla a mang uh pawt eh,” a ti nah.
10 Ní ìgbà náà ni àwọn akóniṣiṣẹ́ àti àwọn tí ń ṣe alábojútó iṣẹ́ jáde tọ̀ wọ́n lọ láti sọ fún àwọn ènìyàn náà pé, “Èyí ni ohun tí Farao sọ, ‘Èmi kò ní fún un yín ni koríko gbígbẹ mọ́.
Te phoeiah pilnam aka tueihno neh a rhoiboei rhoek te cet uh tih pilnam te a voek uh. Te vaengah, “Pharaoh loh, ‘Nangmih te cangkong kam pae mahpawh,’ a ti.
11 Ẹ lọ wá koríko gbígbẹ ni ibi tí ẹ bá ti lè rí i, ṣùgbọ́n iṣẹ́ yín kí yóò dínkù.’”
Namamih cet uh lamtah me lamkah a hmuh uh akhaw cangkong te namamih loh vawthaih uh. Tedae ol vanbangla na thohtatnah te hnop boeh,” a ti nah.
12 Gbogbo wọn sí fọ́n káàkiri ni ilẹ̀ Ejibiti láti sa ìdì koríko tí wọn yóò lò bí ì koríko gbígbẹ fún sísun bíríkì.
Te vaengah pilnam te cangkong yueng la divawt coi ham Egypt kho tom ah taekyak uh.
13 Àwọn akóniṣiṣẹ́ sì ń ni wọ́n lára, wọ́n wí pé, “Ẹ parí iṣẹ́ tí ẹ ni láti ṣe fún ọjọ́ kan bí ìgbà ti a ń fún un yin ní koríko gbígbẹ.”
Te vaengah aka tueihno rhoek loh a tanolh uh tih, “Cangkong a om vaengkah bangla hnin at kah na bi tueng hno te amah khohnin ah coeng uh,” a ti nah.
14 Àwọn alábojútó iṣẹ́ tí àwọn akóniṣiṣẹ́ Farao yàn lára ọmọ Israẹli ni wọn ń lù, tí wọn sì ń béèrè lọ́wọ́ wọn pé, “Èéṣe tí ẹ̀yin kò ṣe iye bíríkì ti ẹ̀yin ń ṣe ní àná ní òní bí i tí àtẹ̀yìnwá?”
Amih sokah a khueh Pharaoh kah a tueihno rhoek loh Israel ca rhoek kah rhoiboei te a ngawn uh tih, “Hlaem hlavai kah bangla saii ham khaw hlaem neh tihnin kah khaw balae tih na oltlueh te na coeng uh pawh,” a ti na uh.
15 Nígbà náà ni àwọn alábojútó iṣẹ́ tí a yàn lára àwọn ọmọ Israẹli tọ Farao lọ láti lọ bẹ̀bẹ̀ pé, “Èéṣe tí ìwọ fi ọwọ́ líle mú àwa ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ̀ báyìí?
Te dongah Israel ca rhoek kah rhoiboei rhoek te cet uh tih Pharaoh taengah pang uh tih, “Balae tih na sal rhoek taengah he he na saii.
16 Wọn kò fún àwọn ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ̀ ni koríko gbígbẹ, síbẹ̀ wọn sọ fún wa pé, ‘Ẹ ṣe bíríkì!’ Wọ́n na àwọn ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ, ṣùgbọ́n ẹ̀bi náà wá láti ọ̀dọ̀ àwọn ènìyàn rẹ.”
Na sal rhoek he cangkong m'paek pawt ah kaimih taengah laiboeng saii ham a thui uh. Na pilnam a tholh akhaw na sal rhoek ni n'ngawn uh coeng he,” a ti na uh.
17 Farao sí dáhùn wí pé, “Ọ̀lẹ ni yín, ọ̀lẹ! Èyí ni ó mú kí ẹ̀yin máa sọ ní ìgbà gbogbo pé, ‘Ẹ jẹ́ kí a lọ, kí a sì rú ẹbọ sí Olúwa.’
Tedae, “Nangmih aka duem la aka duem rhoek, nangmih loh BOEIPA taengah hmueih nawn la caeh ham na thui tangkhuet.
18 Nísinsin yìí ẹ padà lọ sí ẹnu iṣẹ́ yín, a kò ní fún un yín ni koríko gbígbẹ, síbẹ̀ ẹ gbọdọ̀ ṣe iye bíríkì tí ó yẹ kí ẹ ṣe.”
Te dongah cet uh lamtah thotat uh laeh. Nangmih te cangkong m'paek pawt akhaw laiboeng tah a rhimong hil pae uh,” a ti nah.
19 Àwọn ọmọ Israẹli tí ó jẹ́ alábojútó iṣẹ́ mọ̀ dájú wí pé àwọn ti wà nínú wàhálà ńlá ní ìgbà tí a sọ fún wọn pé, “Ẹ kò ní láti dín iye bíríkì tí ẹ ń ṣe ni ojoojúmọ́ kù.”
“Amah khohnin ah hnin at kah olka bangla na laiboeng te hnop boeh,” a ti coeng dongah amih loh a yoethae a puei te Israel ca kah rhoiboei rhoek loh a hmuh uh.
20 Ní ìgbà tí wọ́n kúrò ni ọ̀dọ̀ Farao wọ́n rí Mose àti Aaroni tí ó dúró láti pàdé wọn.
Pharaoh taeng lamloh a nong vaengah amih rhoi doe ham aka pai rhoek loh Moses neh Aaron te a doo uh.
21 Wọn sì wí pé, “Kí Olúwa kí ó wò yín, kí ó sì ṣe ìdájọ́! Ẹ̀yin ti mú wa dàbí òórùn búburú fún Farao àti àwọn òṣìṣẹ́ rẹ̀, ẹ sì ti fún wọn ni idà láti fi pa wá.”
Te vaengah amih rhoi te, “BOEIPA loh nangmih te m'hmu saeh lamtah laitloek nawn saeh. Mamih kah hmuehmuei te Pharaoh mik ah bo a rhim sak tih a sal rhoek mikhmuh ah mamih ngawn ham a kut ah cunghang a paek,” a ti rhoi.
22 Mose padà tọ Olúwa lọ, ó sì wí pé, “Olúwa, èéṣe tí ìwọ fi mú ìyọnu wá sí orí àwọn ènìyàn wọ̀nyí? Ṣe torí èyí ni ìwọ fi rán mi?
Te dongah Moses te BOEIPA taengla mael tih, “Ka Boeipa aw, balae tih pilnam soah thae na huet? Balae tih he la kai nan tueih?
23 Láti ìgbà ti mo ti tọ Farao lọ láti bá a sọ̀rọ̀ ni orúkọ rẹ ni ó ti mú ìyọnu wá sí orí àwọn ènìyàn wọ̀nyí, bẹ́ẹ̀ ni ìwọ kò sì gba àwọn ènìyàn rẹ sílẹ̀ rárá.”
Na ming neh thui ham Pharaoh taengla ka pawk lamkah te pilnam he ni thae a huet thil tih, na pilnam te na huul khaw na huul hae moenih,” a ti nah.

< Exodus 5 >