< Exodus 5 >
1 Lẹ́yìn náà ni Mose àti Aaroni tọ Farao lọ, wọ́n sì wí pé, “Èyí ni ohun tí Olúwa, Ọlọ́run Israẹli sọ, ‘Jẹ́ kí àwọn ènìyàn mi kí ó lọ, kí wọn kí ó lè ṣe àjọ mi ní ijù.’”
Amalalu, Mousese amola Elane da Felouma misini, ema amane sia: i, “Hina Gode da amane sia: sa, ‘Na fi dunu ga masa: ne, ilia logo doasima. Ilia da Nama nodone sia: ne gadomusa: , wadela: i hafoga: i soge ganodini hahawane gilisisu hamomu galebe.’”
2 Farao dáhùn wí pé, “Ta ni Olúwa, tí èmi yóò fi gbọ́rọ̀ sí i lẹ́nu, tí èmi yóò fi jẹ́ kí Israẹli ó lọ? Èmi kò mọ Olúwa, èmi kò sì ní jẹ́ kí Israẹli ó lọ.”
Felou da bu adole i, “Hina Gode da nowala: ? Na da abuliba: le Ea sia: nabalu, Isala: ili dunu udigili ahoanoma: ne logo doasima: bela: ? Na da Hina Gode hame dawa: Isala: ili dunu ilia da hame gadili masunu.”
3 Lẹ́yìn náà ni wọ́n wí pé, “Ọlọ́run àwọn Heberu tí pàdé wa. Ní ìsinsin yìí, jẹ́ kí a lọ ní ìrìn ọjọ́ mẹ́ta sínú aginjù láti rú ẹbọ sí Olúwa Ọlọ́run wa, kí Ó má ba á fi àjàkálẹ̀-ààrùn tàbí idà bá wa jà.”
Mousese amola Elane da amane sia: i, “Hibulu dunu ilia Gode da anima misi. Ninia da eso udiana wadela: i soge ganodini asili, Hina Godema gobele salasu hamomu hanai. Agoane hame hamosea, Hina Gode da olo bagade o gegesu bagade amoga nini fanelegemu.”
4 Ṣùgbọ́n ọba Ejibiti sọ wí pé, “Mose àti Aaroni, èéṣe ti ẹ̀yin fi mú àwọn ènìyàn kúrò lẹ́nu iṣẹ́ wọn? Ẹ padà sẹ́nu iṣẹ́ yín.”
Felou da Mousese amola Elane elama amane sia: i, “Ani da abuliba: le, Isala: ili udigili hawa: hamosu dunuma ilia hawa: hamosu fisimusa: sia: sala: ? Ilia bu hawa: hamomusa: sia: ma.
5 Nígbà náà ni Farao sọ pé, “Ẹ wò ó àwọn ènìyàn náà ti pọ̀ sí ì nílẹ̀ yìí ní ìsinsin yìí, ẹ̀yin sì ń dá wọn dúró láti máa bá iṣẹ́ lọ.”
Dilia Isala: ili fi dunu idi da Idibidi dunu ilia idi amo baligi dagoi. Amola wali alia da ilia hawa: hamosu logo damumusa: dawa: lala.”
6 Ní ọjọ́ yìí kan náà ni Farao pàṣẹ fún àwọn akóniṣiṣẹ́ àti àwọn ti ń ṣe alábojútó iṣẹ́ lórí àwọn ènìyàn.
Amo esoha Felou da Idibidi ouligisu dunu amola Isala: ili ouligisu dunu ilima amane sia: i,
7 “Ẹ̀yin kò ní láti pèsè koríko gbígbẹ fún bíríkì sísun mọ́ fún àwọn ènìyàn wọ̀nyí; ẹ jẹ́ kí wọn máa wá koríko gbígbẹ fún ara wọn.
“Dilia Isala: ili dunuma ilia ga: i (osoboga hamoi igi) hamoma: ne gisi mae ima. Ilisu gisi hogola masa: ne sia: ma.
8 Ṣùgbọ́n ẹ jẹ́ kí wọn ó ṣe iye bíríkì kan náà bí ì ti àtẹ̀yìnwá, kí ẹ má ṣe dín iye rẹ̀ kú. Ọ̀lẹ ni wọ́n, ìwà ọ̀lẹ yìí náà ló mú wọn pariwo pé, ‘Ẹ jẹ́ kí a lọ, kí a sì rú ẹbọ sí Ọlọ́run wa.’
Be ilia da osoboga hamoi igi idi da hame fonobomu. Ilia da waha hamosa defele hamomu. Ilia hawa: hamosu da fonobahadi fawane. Ilia da hawa: hamosu higa: iba: le, ilia da gadili ilia Godema gobele salasu hamoma: ne nama adole ba: lala.
9 Ẹ mú iṣẹ́ náà le fún wọn, kí wọn bá a le è tẹramọ́ iṣẹ́ wọn, ẹ má fi ààyè gba irọ́ wọn.”
Hawa: hamosu gasa bagade ilima olelema. Amasea, ilia da ogogosu sia: amo nabimu hamedeiwane ba: mu.”
10 Ní ìgbà náà ni àwọn akóniṣiṣẹ́ àti àwọn tí ń ṣe alábojútó iṣẹ́ jáde tọ̀ wọ́n lọ láti sọ fún àwọn ènìyàn náà pé, “Èyí ni ohun tí Farao sọ, ‘Èmi kò ní fún un yín ni koríko gbígbẹ mọ́.
Idibidi hawa: hamosu ouligisu dunu amola Isala: ili ouligisu dunu da asili, Isala: ili dunuma amane sia: i, “Felou da dilima gisi eno hame imunu sia: i.
11 Ẹ lọ wá koríko gbígbẹ ni ibi tí ẹ bá ti lè rí i, ṣùgbọ́n iṣẹ́ yín kí yóò dínkù.’”
E da dilisu gisi hogoma: ne amola ga: i dilia waha idi defele hamoma: ne sia: sa.”
12 Gbogbo wọn sí fọ́n káàkiri ni ilẹ̀ Ejibiti láti sa ìdì koríko tí wọn yóò lò bí ì koríko gbígbẹ fún sísun bíríkì.
Amaiba: le, Isala: ili dunu da Idibidi soge huluane amoga gisi hogola asi.
13 Àwọn akóniṣiṣẹ́ sì ń ni wọ́n lára, wọ́n wí pé, “Ẹ parí iṣẹ́ tí ẹ ni láti ṣe fún ọjọ́ kan bí ìgbà ti a ń fún un yin ní koríko gbígbẹ.”
Idibidi gasa bagade ouligisu dunu da ili musa: ga: i idi defele hamoma: ne, ilima gasa bagade hamoi.
14 Àwọn alábojútó iṣẹ́ tí àwọn akóniṣiṣẹ́ Farao yàn lára ọmọ Israẹli ni wọn ń lù, tí wọn sì ń béèrè lọ́wọ́ wọn pé, “Èéṣe tí ẹ̀yin kò ṣe iye bíríkì ti ẹ̀yin ń ṣe ní àná ní òní bí i tí àtẹ̀yìnwá?”
Idibidi ouligisu dunu ilia da Isala: ili ouligisu dunu (ilima ilia hawa: hamosu ouligima: ne sia: i) amo bagade fananu. Ilia gasa fili amane sia: i, “Dilia da abuliba: le dilia musa: ga: i (osoboga hamoi igi) idi amo hame hamosala: ?”
15 Nígbà náà ni àwọn alábojútó iṣẹ́ tí a yàn lára àwọn ọmọ Israẹli tọ Farao lọ láti lọ bẹ̀bẹ̀ pé, “Èéṣe tí ìwọ fi ọwọ́ líle mú àwa ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ̀ báyìí?
Amalalu, Isala: ili ouligisu dunu ilia da Felouma asili amane sia: i, “Hina bagade! Di da abuliba: le ninima agoane hamosala: ?
16 Wọn kò fún àwọn ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ̀ ni koríko gbígbẹ, síbẹ̀ wọn sọ fún wa pé, ‘Ẹ ṣe bíríkì!’ Wọ́n na àwọn ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ, ṣùgbọ́n ẹ̀bi náà wá láti ọ̀dọ̀ àwọn ènìyàn rẹ.”
Ilia da ninima gisi hame iaha. Be ninia musa: ga: i idi defele hamoma: ne ilia da gasa fili sia: sa. Amola, wali ilia da nini fanana. Ninia hame, be dia fi dunu da giadofasa.”
17 Farao sí dáhùn wí pé, “Ọ̀lẹ ni yín, ọ̀lẹ! Èyí ni ó mú kí ẹ̀yin máa sọ ní ìgbà gbogbo pé, ‘Ẹ jẹ́ kí a lọ, kí a sì rú ẹbọ sí Olúwa.’
Be Felou bu adole i, “Dilia da hawa: hamosu higa: iba: le, gadili dia Hina Godema gobele salasu hamoma: ne nama adole ba: sa.
18 Nísinsin yìí ẹ padà lọ sí ẹnu iṣẹ́ yín, a kò ní fún un yín ni koríko gbígbẹ, síbẹ̀ ẹ gbọdọ̀ ṣe iye bíríkì tí ó yẹ kí ẹ ṣe.”
Wali hawa: hamomusa: masa! Ninia da gisi dilima hame imunu. Be dilia musa: idi amo defele hamoma.”
19 Àwọn ọmọ Israẹli tí ó jẹ́ alábojútó iṣẹ́ mọ̀ dájú wí pé àwọn ti wà nínú wàhálà ńlá ní ìgbà tí a sọ fún wọn pé, “Ẹ kò ní láti dín iye bíríkì tí ẹ ń ṣe ni ojoojúmọ́ kù.”
Amo sia: nababeba: le, Isala: ili hawa: hamosu ouligisu dunu da bidi hamosu da Isala: ili dunuma doaga: i dagoi dawa: i galu. Bai ilia ouligisu dunu da ilia musa: hamoi defele amo hamoma: ne sia: i dagoi.
20 Ní ìgbà tí wọ́n kúrò ni ọ̀dọ̀ Farao wọ́n rí Mose àti Aaroni tí ó dúró láti pàdé wọn.
Ilia da Felou ea diasu fisili gadili ahoanoba, Mousese amola Elane ili misunu ouesalebe ba: i.
21 Wọn sì wí pé, “Kí Olúwa kí ó wò yín, kí ó sì ṣe ìdájọ́! Ẹ̀yin ti mú wa dàbí òórùn búburú fún Farao àti àwọn òṣìṣẹ́ rẹ̀, ẹ sì ti fún wọn ni idà láti fi pa wá.”
Ilia da Mousese amola Elane elama amane sia: i, “Alia hamobeba: le, Felou amola ea hina ouligisu dunu da nini bagade higasa. Hina Gode da amo hou ba: i dagoi amola E da alima se imunu. Alia da amo hou hamobeba: le, alia da Idibidi dunu nini fanelegema: ne abalosu logo fodoi dagoi.”
22 Mose padà tọ Olúwa lọ, ó sì wí pé, “Olúwa, èéṣe tí ìwọ fi mú ìyọnu wá sí orí àwọn ènìyàn wọ̀nyí? Ṣe torí èyí ni ìwọ fi rán mi?
Amalalu, Mousese da Hina Godema sinidigili amane sia: i, “Hina Gode! Dia da abuliba: le Dia fi dunuma se nabasisala: ? Dia da abuliba: le na guiguda: asunasibala: ?
23 Láti ìgbà ti mo ti tọ Farao lọ láti bá a sọ̀rọ̀ ni orúkọ rẹ ni ó ti mú ìyọnu wá sí orí àwọn ènìyàn wọ̀nyí, bẹ́ẹ̀ ni ìwọ kò sì gba àwọn ènìyàn rẹ sílẹ̀ rárá.”
Na da Dia sia: Felouma olelemusa: asiba: le, e da eso huluane ilima se bagade iaha. Amola Di da ili fidima: ne hamedafa hamoi!”