< Exodus 40 >

1 Olúwa sì wí fún Mose pé,
To pacoengah Angraeng mah Mosi khaeah,
2 “Ní ọjọ́ kìn-ín-ní, oṣù kìn-ín-ní ni kí ó gbé àgọ́ náà, àgọ́ àjọ náà ró.
Kaminawk amkhuenghaih kahni im to, khrah hmaloe koek, ni tangsuek naah sah ah.
3 Gbé àpótí ẹ̀rí sí inú rẹ̀, kí ó sì bo àpótí náà pẹ̀lú aṣọ títa.
Hnukung thingkhong loe, to kahni imthung ah suem ah, to thingkhong loe payang ih kahni hoiah khuk ah.
4 Gbé tábìlì náà wọ ilé, kí o sì to àwọn ohun tí ó jẹ́ tirẹ̀ lé e lórí. Nígbà náà gbé ọ̀pá fìtílà wọlé, kí o sì to àwọn fìtílà rẹ̀.
A thungah caboi suem ah loe, hmuennawk boih caboi nuiah suem ah; to pacoengah hmaithawk paanghaih tung to suem ah loe, hmai to paaang ah.
5 Gbé pẹpẹ wúrà ti tùràrí sí iwájú àpótí ẹ̀rí, kí o sì fi aṣọ títa ẹnu-ọ̀nà sí ara àgọ́ náà.
Hmuihoih thlaekhaih hmaicam to hnukung thingkhong hmaa ah suem ah loe, kahni im akunhaih khongkha ah payang ih kahni hoiah pakaa ah.
6 “Gbé pẹpẹ ẹbọ sísun sí iwájú ẹnu-ọ̀nà àgọ́ náà, àgọ́ àjọ;
Amkhuenghaih kahni im akunhaih khongkha hmaa ah, hmai angbawnhaih hmaicam to suem ah.
7 gbé agbada sí àárín àgọ́ àjọ àti pẹpẹ, kí o sì fi omi sí inú rẹ̀.
Kaminawk amkhuenghaih kahni im hoi hmaicam salakah sabae kathuk to suem ah loe, a thungah tui to lawn ah.
8 Gbé àgbàlá ró yìí ka, kí ó sì fi aṣọ títa sí ẹnu-ọ̀nà àgbàlá náà.
Longhma taeng to paka boih ah loe, longhma akunhaih khongkha taengah kahni to payang ah.
9 “Mú òróró ìtasórí, kí ó sì ta á sára àgọ́ náà àti ohun gbogbo tí ó wà nínú rẹ̀, yà pẹpẹ sí mímọ́ àti gbogbo ọ̀ṣọ́ rẹ̀, yóò sì jẹ́ mímọ́.
Tak bawhhaih situi to la ah loe, kahni im hoi a thungah kaom hmuennawk to nok boih ah; to ih hmuennawk to ciimsak boih ah, to tiah ni kahni im to ciim vop tih.
10 Ta òróró sára pẹpẹ ẹbọ sísun àti gbogbo ohun èlò rẹ̀, ya pẹpẹ náà sí mímọ́, yóò sì jẹ́ mímọ́ jùlọ.
To pacoengah hmai angbawnhaih hmaicam hoi hmuennawk to situi nok boih ah loe, hmaicam to ciimsak ah; to tiah ni kaciim koek hmaicam ah om tih.
11 Ta òróró sára agbada náà àti ẹsẹ̀ rẹ, kí o sì yà wọ́n sí mímọ́.
Kathuk sabae hoi pahnuthaih a khok to situi nok ah loe, ciimsak ah.
12 “Mú Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ wá sí ẹnu-ọ̀nà àgọ́ àjọ, kí o sì wẹ̀ wọ́n pẹ̀lú omi.
Aaron hoi a caanawk to amkhuenghaih kahni im khongkha ah caehhaih ah loe, tui amhlusak ah.
13 Nígbà náà wọ Aaroni ní aṣọ mímọ́, ta òróró sí i ní orí, kí o sì yà á sí mímọ́, nítorí kí ó lè máa sìn mi bí àlùfáà.
Aaron hanah kaciim kahni to angkhuksak ah, qaima toksak thai hanah, situi to nok ah loe ciimsak ah.
14 Mú àwọn ọmọ rẹ̀ kí o sì fi aṣọ àwọ̀tẹ́lẹ̀ wọ̀ wọ́n.
Anih ih caanawk to angzo haih ah loe, laihaw kasawk to angkhuksak ah.
15 Ta òróró sí wọn ní orí gẹ́gẹ́ bí o ti ta òróró sí baba wọn ní orí, nítorí kì wọn lè máa sìn mi bí àlùfáà. Ìtasórí wọn yóò jẹ́ iṣẹ́ àlùfáà ti yóò máa lò fún gbogbo ìrandíran tó ń bọ̀.”
Kai khaeah qaima tok a sak o thai hanah, ampa situi hoi na bawh baktih toengah, a caanawk doeh bawh ah; a caanawk dung khoek to qaima ah oh poe han ih ni nihcae to situi hoiah na bawh, tiah a naa.
16 Mose ṣe ohun gbogbo gẹ́gẹ́ bí Olúwa ti pàṣẹ fún un.
Angraeng mah thuih ih lok baktih toengah, Mosi mah hmuennawk to sak boih.
17 Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n gbé àgọ́ náà ró ní ọjọ́ kìn-ín-ní oṣù kìn-ín-ní ní ọdún kejì.
To pongah saning hnetto haih, khrah tangsuek, ni hmaloe koek ah, Mosi mah kahni im to a sak.
18 Nígbà tí Mose gbé àgọ́ náà ró ó fi ihò ìtẹ̀bọ̀ sí ààyè rẹ̀, ó to pákó rẹ̀, ó fi ọ̀pá rẹ̀ bọ̀ ọ́, ó sì gbé àwọn òpó rẹ̀ ró.
Mosi mah kahni im sak naah, akhok pahnuthaih hmuennawk to kacakah a sak, thingphaeknawk to a sak moe, takraenghaih thingnawk to sak pacoengah, tungnawk to a sak.
19 Ó na aṣọ àgọ́ náà sórí àgọ́, ó sì fi ìbòrí bo orí àgọ́ náà, bí Olúwa ṣe pàṣẹ fún Mose.
To pacoengah kahni im to payuengh moe, Angraeng mah thuih ih lok baktih toengah, kani im ranuih to a khuk.
20 Ó mu ẹ̀rí, ó sì fi sínú àpótí, ó so àwọn òpó mọ́ àpótí náà, ó sì fi àánú bo orí rẹ.
Hnukung thingkhong to a lak moe, to thingkhong nuiah aputhaih thing to a hawt pacoengah, palungnathaih tangkhang to a nuiah suek.
21 Ó sì gbé àpótí náà wá sínú àgọ́; ó sì sọ aṣọ títa, ó sì ta á bo àpótí ẹ̀rí, gẹ́gẹ́ bí Olúwa ti pàṣẹ fún Mose.
Thingkhong to kahni imthung ah a sin moe, Angraeng mah thuih ih lok baktih toengah, hnukung thingkhong to payang ih kahni hoiah a khuk.
22 Mose gbé tábìlì sínú àgọ́ àjọ sí ìhà àríwá àgọ́ náà lẹ́yìn aṣọ títa,
Mosi mah caboi to amkhuenghaih kahni imthung aluek bang, payang ih kahni tasa bangah a suek.
23 ó sì to àkàrà sórí rẹ̀ níwájú Olúwa, gẹ́gẹ́ bí Olúwa ti pàṣẹ fún Mose.
Angraeng mah Mosi khaeah thuih ih lok baktih toengah, Angraeng hmaa ah takaw to a suek pae.
24 Ó gbé ọ̀pá fìtílà sínú àgọ́ àjọ ní òdìkejì tábìlì ní ìhà gúúsù àgọ́ náà.
Hmaithawk paaanghaih tung doeh kahni imthung, kahni im aloih bang ah a suek.
25 Ó sì tan àwọn fìtílà náà níwájú Olúwa, gẹ́gẹ́ bí Olúwa ti pàṣẹ fún Mose.
Angraeng mah thuih ih lok baktih toengah, Angraeng hmaa ah hmaiim to paaang.
26 Mose gbé pẹpẹ wúrà sínú àgọ́ àjọ níwájú aṣọ títa
Mosi mah sui hmaicam to amkhuenghaih kahni imthung, payang ih kahni hmaa ah a suek.
27 ó sì jó tùràrí dídùn lórí rẹ̀, gẹ́gẹ́ bí Olúwa ti pàṣẹ fún Mose.
Angraeng mah thuih ih lok baktih toengah, to ah hmuihoih to a thlaek.
28 Ó sì ta aṣọ títa sí ẹnu-ọ̀nà àgọ́ náà.
To pacoengah kahni im akunhaih thok taengah kahni to payang.
29 Ó gbé pẹpẹ ẹbọ sísun sí ẹ̀gbẹ́ ẹnu-ọ̀nà àgọ́ àjọ, ó sì rú ẹbọ sísun àti ẹbọ oúnjẹ, gẹ́gẹ́ bí Olúwa ti pàṣẹ fún Mose.
Kaminawk amkhuenghaih kahni im akunhaih thok taengah hmai angbawnhaih hmacam to a suek moe, Angraeng mah thuih ih lok baktih toengah, to hmaicam nuiah hmai angbawnhaih hoi cang angbawnhaih to a sak.
30 Ó gbé agbada sí àárín àgọ́ àjọ àti pẹpẹ, ó sì pọn omi sínú rẹ̀ fún wíwẹ̀,
Amkhuenghaih kahni im hoi hmaicam salakah, sabae kathuk to a suek moe, amsaehhaih tui to a lawn.
31 Mose, Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ lò ó láti fi wẹ ọwọ́ àti ẹsẹ̀ wọn.
Mosi, Aaron hoi a caanawk loe to ih tui hoiah khok bannawk to amsaeh o;
32 Wọ́n máa ń wẹ̀ nígbàkígbà tí wọ́n bá wọ àgọ́ àjọ tàbí tí wọ́n bá súnmọ́ pẹpẹ, gẹ́gẹ́ bí Olúwa ti pàṣẹ fún Mose.
amkhuenghaih kahni imthung ah akun o moe, hmaicam taengah a caeh o naah, Angraeng mah Mosi khaeah thuih ih lok baktih toengah, nihcae loe tui hoiah amsaeh o.
33 Mose sì gbé àgbàlá tí ó yí àgọ́ náà kà ró àti pẹpẹ, ó sì ta aṣọ títa ti ẹnu-ọ̀nà sí àgbàlá náà. Bẹ́ẹ̀ ni Mose ṣe parí iṣẹ́ náà.
To pacoengah Mosi mah hmaicam hoi longhma pakaahaih kahni to payang; longhma akunhaih khongkha taengah kahni to payang. To tiah Mosi mah toksakhaih to pacoeng.
34 Nígbà náà ni àwọsánmọ̀ bo àgọ́ àjọ, ògo Olúwa bo àgọ́ náà.
To naah amkhuenghaih kahni im to tamai mah khuk, kahni im loe Angraeng lensawkhaih hoiah koi.
35 Mose kò sì lè wọ inú àgọ́ àjọ, nítorí àwọsánmọ̀ wà ní orí àgọ́, ògo Olúwa sì ti kún inú àgọ́ náà.
Amkhuenghaih kahni im to tamai mah khuk khoep pongah, Mosi loe kahni imthung ah akun thai ai; to naah kahni im loe Angraeng lensawkhaih hoiah koi.
36 Ní gbogbo ìrìnàjò àwọn ọmọ Israẹli nígbàkígbà tí a bá ti fa ìkùùkuu àwọsánmọ̀ náà sókè kúrò lórí àgọ́, wọ́n máa ń jáde lọ;
Israel kaminawk kholong caeh o naah, kahni im nui hoiah tamai angkhoeng pacoengah ni a caeh o vop;
37 ṣùgbọ́n tí àwọsánmọ̀ kò bá gòkè wọn kò ní jáde títí di ọjọ́ tí ó bá gòkè.
tamai angkhoeng tahang ai nahaeloe, tamai angkhoeng tahang ai karoek to, kholong caeh o ai.
38 Nítorí náà àwọsánmọ̀ Olúwa wà lórí àgọ́ ní ọ̀sán, iná sì wà nínú àwọsánmọ̀ ní alẹ́, ní ojú gbogbo ilé Israẹli ní gbogbo ìrìnàjò wọn.
Israel kaminawk kholong caeh o nathung, nihcae boih mikhnuk ah, athun naah Angraeng ih tamai to kahni im nuiah oh, khoving naah loe tamai nuiah hmai to oh.

< Exodus 40 >