< Exodus 4 >

1 Mose dáhùn ó sì wí pé, “Ṣùgbọ́n bí wọn kò bá gbà mí gbọ́ ń kọ́? Tàbí tí wọn kò fi etí sílẹ̀ láti gbọ́ ọ̀rọ̀ ẹnu mi, tí wọn sì wí pé, ‘Olúwa kò farahàn ọ́’?”
Tedae Moses loh a doo tih, “Kai he n'tangnah uh pawt koinih kai ol he hnatun pawt vetih, ‘Nang taengah BOEIPA a phoe moenih,’ a ti uh ni,” a ti nah.
2 Ní ìgbà náà ni Olúwa sọ fún un pé, “Kí ni ó wà ní ọwọ́ rẹ n nì?” Ó sì dáhùn pé, “Ọ̀pá ni.”
Te dongah amah te BOEIPA loh, “Na kut dongkah te balae?” a ti nah hatah, “Conghol,” a ti nah.
3 Olúwa sì sọ pé, “Sọ ọ̀pá náà sílẹ̀.” Mose sì sọ ọ̀pá náà sílẹ̀, lọ́gán ni ọ̀pá náà di ejò, ó sì sá fún un.
Te phoeiah, “Te te diklai la voei lah,” a ti nah tih diklai la a voeih. Te vaengah rhul la a poeh pah dongah Moses khaw a taeng lamloh rhaelrham.
4 Nígbà náà ni Olúwa wá sọ fún un pé, “Na ọwọ́ rẹ, kí o sì mú un ni ìrù.” Mose sì na ọwọ́ rẹ̀, ó sì mu ejò náà, ejò náà sì padà di ọ̀pá tí ó wà ni ọwọ́ rẹ̀.
Tedae BOEIPA loh Moses te, “Na kut yueng lamtah a mai ah tu,” a ti nah. A kut a yueng tangloeng tih a tuuk vaengah tah a kut dongah conghol la poeh.
5 Olúwa sì wí pé, “Èyí rí bẹ́ẹ̀ kí wọn bá à le è gbàgbọ́ pé, Olúwa Ọlọ́run àwọn baba wọn, Ọlọ́run Abrahamu, Ọlọ́run Isaaki, àti Ọlọ́run Jakọbu; tí farahàn ọ́.”
Te dongah a napa rhoek kah Pathen BOEIPA, Abraham Pathen, Isaak Pathen, Jakob Pathen tah nang taengah phoe tila a tangnah uh bitni.
6 Ní ìgbà náà ni Olúwa wí pé, “Ti ọwọ́ rẹ bọ inú aṣọ ní igbá àyà rẹ̀.” Mose sì ti ọwọ́ rẹ̀ bọ inú aṣọ ní igbá àyà rẹ̀, ní ìgbà ti ó sì yọ ọ́ jáde, ọwọ́ rẹ̀ ti dẹ́tẹ̀, ó sì ti funfun bí ẹ̀gbọ̀n òwú.
Te phoeiah BOEIPA loh anih te, “Na kut te na rhang ah puei bal dae,” a ti nah. A kut te a rhang ah a puei tangloeng tih a yueh vaengah tah a kut te vuelsong bangla a pahuk pah.
7 Ó sì wí pé, “Nísinsin yìí, fi ọwọ́ náà padà sí abẹ́ aṣọ ní igbá àyà rẹ.” Mose sì ṣe bẹ́ẹ̀, ọwọ́ rẹ̀ sì padà bọ́ sípò bí àwọn ẹ̀yà ara rẹ̀ tókù.
Te phoeiah, “Na kut te na rhang ah koep puei lah,” a ti nah. A kut te a rhang ah a puei tangloeng tih a rhang lamloh a yueh vaengah tah a saa thim la tarha a om pah.
8 Ní ìgbà náà ni Olúwa wí pé, “Bí wọn kò bá gbà ọ́ gbọ́ tàbí kọ ibi ara sí iṣẹ́ ìyanu àkọ́kọ́, wọ́n le è ti ipasẹ̀ iṣẹ́ ìyanu kejì gbàgbọ́.
“Nang te n'tangnah uh pawt akhaw ana om ngawn saeh. Lamhma kah miknoek ol te a yaak pawt atah a pabae kah miknoek ol te tangnah uh saeh.
9 Ṣùgbọ́n bí wọn kò bá gba àmì méjèèjì wọ̀nyí gbọ́, tí wọn kò sì fetí sí ọ̀rọ̀ rẹ, bu omi díẹ̀ láti inú odò Naili kí o si dà á sí orí ìyàngbẹ ilẹ̀, omi tí ìwọ bù láti inú odò yìí yóò sì di ẹ̀jẹ̀.”
Tedae miknoek rhoi dongkah he khaw tangnah uh pawt tih na ol te a yaak uh pawt akhaw ana om saeh. Sokko lamkah tui te lo lamtah laiphuei te bueih pah. Sokko lamkah na loh tui te poehlip vetih laikoeng dongah thii la poeh ni,” a ti nah.
10 Mose sì sọ fún Olúwa pé, “Èmi jẹ́ akólòlò, èmi kì í ṣe ẹni tó lè sọ̀rọ̀ já gaara láti ìgbà àtijọ́ wá tàbí láti ìgbà ti o ti ń bá ìránṣẹ́ rẹ sọ̀rọ̀, mo jẹ́ ẹni ti ahọ́n rẹ̀ lọ́, tí ó sì ń lọ́ra àti sọ̀rọ̀.”
Te vaengah Moses loh BOEIPA te, “Aw ka Boeipa, hlaem ah khaw, hlaemvai ah khaw na sal taengah na thui vaeng lamlong mah kai he olka dongah ka hlang voel moenih. Te dongah ka ka tonga tih ka ol khol,” a ti nah.
11 Olúwa sì sọ fún un pé, “Ta ni ó fún ènìyàn ni ẹnu? Ta ni ó mú un ya odi tàbí adití? Ta ni ó mú un ríran, tàbí mú un fọ́jú? Ǹjẹ́ kì í ṣe èmi Olúwa?
Tedae BOEIPA loh amah te, “Hlang ham ka aka khueh pah te unim? Olmueh neh hnapang, miktueng neh mikdael aka khueh te unim? BOEIPA kamah moenih a?
12 Lọ nísinsin yìí, Èmi yóò ràn ọ́ lọ́wọ́ láti sọ̀rọ̀. Èmi yóò sì kọ́ ọ ni ohun ti ìwọ yóò sọ.”
Te dongah cet laeh lamtah na hmuilai dongah kamah ka om vetih na thui ham te kan thuinuet bitni,” a ti nah.
13 Mose dáhùn ó wí pé, “Olúwa jọ̀wọ́ rán ẹlòmíràn láti lọ ṣe iṣẹ́ yìí.”
Tedae, “Aw ka Boeipa, na tueih akhaw kuttoem mah tueih laeh,” a ti nah.
14 Ìbínú Olúwa ru sókè sí Mose, ó sì sọ pé, “Aaroni ará Lefi arákùnrin rẹ ń kọ́? Mo mọ̀ pé ó lè sọ̀rọ̀ já gaara, ó ti wà ní ọ̀nà rẹ̀ báyìí láti pàdé e rẹ. Inú rẹ̀ yóò sì dùn ti ó bá rí ọ.
Te vaengah BOEIPA kah thintoek te Moses taengah sai tih, “Na manuca Aaron te Levi moenih a? Ka ming ta, thui ham koi te anih loh a thui ta. Te dongah anih khaw nang doe ham ha lo coeng. Te vaengah nang m'hmuh vetih a lungbuei ah a kohoe bitni.
15 Ìwọ yóò sọ̀rọ̀ fún un, ìwọ yóò sì fi ọ̀rọ̀ sí i lẹ́nu, èmi yóò ràn yín lọ́wọ́ láti sọ̀rọ̀. Èmi yóò kọ́ ọ yín ni ohun ti ẹ ó ṣe.
Anih te voek tangloeng lamtah olka he a hmuilai ah khueh pah. Kai he nang kah hmuilai dongah khaw anih kah hmuilai dongah khaw ka om vetih na saii ham te nang kan thuinuet bitni.
16 Òun yóò bá ọ sọ̀rọ̀ sí àwọn ènìyàn, yóò sì dàbí i pé ẹnu un rẹ ni a gbà sọ ọ̀rọ̀ náà, ìwọ yóò sì dàbí Ọlọ́run ní iwájú rẹ̀.
Te phoeiah anih te pilnam taengah nang yueng la cal saeh lamtah nang kah hmuilai la om rhoe om saeh. Nang ngawn tah anih taengah Pathen bangla na om ni.
17 Ṣùgbọ́n mú ọ̀pá yìí ni ọwọ́ rẹ kí ìwọ bá à lè fi ṣe àwọn iṣẹ́ àmì ìyanu pẹ̀lú rẹ̀.”
Tedae he conghol he na kut dongah pom lamtah te nen te miknoek saii,” a ti nah.
18 Mose padà sí ọ̀dọ̀ Jetro baba ìyàwó rẹ̀, ó sì sọ fún un pé, “Jọ̀wọ́ jẹ́ kí n padà tọ àwọn ènìyàn mi lọ ni ilẹ̀ Ejibiti láti wò bóyá wọ́n ṣì wà láààyè síbẹ̀.” Jetro sì dáhùn, ó wí pé, “Máa lọ ni àlàáfíà.”
Te daengah Moses te cet tih a masae Jether taengla mael. Te phoeiah a masae taengah, “Ka cet pawn saeh lamtah Egypt kah ka manuca rhoek taengah ka mael mai eh. Amih kah hingnah khaw ka hmuh pueng khaming,” a ti nah. Te vaengah Jethro loh Moses te, “Sading la cet ne,” a ti nah.
19 Nísinsin yìí, Olúwa ti sọ fún Mose ni ilẹ̀ Midiani pé, “Máa padà lọ sí Ejibiti, nítorí àwọn ti ó fẹ́ pa ọ ti kú.”
Te vaengah BOEIPA loh Midian kah Moses te, “Cet lamtah Egypt la mael laeh, nang kah hinglu aka mae hlang khaw boeih duek uh coeng,” a ti nah.
20 Mose mú ìyàwó rẹ̀ àti àwọn ọmọ rẹ̀, ó kó wọn lé orí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́, ó sì bẹ̀rẹ̀ ìrìnàjò rẹ̀ padà sí Ejibiti. Ó sì mú ọ̀pá Ọlọ́run sí ọwọ́ rẹ̀.
Te dongah Moses loh a yuu neh a ca rhoek te a loh tih laak dongah a ngol sak. Tedae Egypt kho la a mael vaengah Moses loh Pathen kah conghol ni a kut dongah a pom.
21 Olúwa sì sọ fún Mose pé, “Ní ìgbà tí ìwọ bá padà sí Ejibiti rí i pé ìwọ ṣe iṣẹ́ ìyanu ni iwájú Farao. Èmi ti fún ọ lágbára láti ṣe é. Èmi yóò sì sé àyà rẹ̀ le, òun kì yóò jẹ́ kí àwọn ènìyàn náà kí ó lọ.
Te vaengah BOEIPA loh Moses te, “Na caeh vaengah Egypt la mael. Na kut dongah kopoekrhai cungkuem kam paek te tueng. Te te Pharaoh mikhmuh ah saii pah. Tedae kai loh a lungbuei ka moem vetih pilnam te hlah mahpawh.
22 Lẹ́yìn náà, kí o sọ fún Farao pé, ‘Èyí ni Olúwa sọ: Israẹli ní àkọ́bí ọmọ mi ọkùnrin,
Tedae Pharaoh te thui pah. BOEIPA loh he ni a thui. Israel tah ka capa neh ka caming ni.
23 mo sọ fún ọ, “Jẹ́ kí ọmọ mi lọ, ki òun kí ó lè máa sìn mí.” Ṣùgbọ́n ìwọ kọ̀ láti jẹ́ kí ó lọ; nítorí náà, èmi yóò pa àkọ́bí ọmọ rẹ ọkùnrin.’”
Te dongah namah taengah khaw ka thui coeng. Ka ca te tueih lamtah kai ham thothueng saeh. Tedae anih hlah ham na aal atah kai loh na capa khuikah na caming te ka ngawn ni ne,” a ti.
24 Ní ọ̀nà ìrìnàjò rẹ, ni ibi tí wọ́n gbé sùn ní ilé èrò ní alẹ́, Olúwa pàdé Mose, ó sì fẹ́ láti pa á.
Longpuei kah rhaehim ah a om vaengah anih te BOEIPA neh hum uh tih ngawn la cai.
25 Ṣùgbọ́n Sippora mú ọ̀bẹ òkúta mímú, ó sì kọ ọmọ rẹ̀ ní ilà abẹ́, ó sì fi awọ rẹ̀ kan ẹsẹ̀ Mose. Sippora sì wí pé, “Ọkọ ẹlẹ́jẹ̀ ni ìwọ jẹ́ sí mi.”
Te vaengah Zipporah loh hmailung a loh tih a capa kah hmuicue te a hlueng pah. Te phoeiah a kho ah a net tih, “Nang tah kai ham thii dongkah yulokung ni,” a ti nah.
26 Nítorí náà Olúwa yọ̀ǹda rẹ láti ìgbà tí ó ti wí pé, “Ẹlẹ́jẹ̀ ni ìwọ í ṣe.” Èyí tó túmọ̀ sí ìkọlà abẹ́.
Te daengah BOEIPA te Moses taeng lamloh nong. [Te vaengah hmuicuerhetnah te ni thii dongkah yulokung la a thui].
27 Olúwa sì sọ fún Aaroni pé, “Lọ sínú aginjù láti lọ pàdé Mose.” Ní ìgbà náà ni ó lọ pàdé Mose ní orí òkè Ọlọ́run, ó sì fi ẹnu kò ó ní ẹnu.
Te phoeiah BOEIPA loh Aaron taengah, “Khosoek la cet lamtah Moses te doe laeh,” a ti nah. A caeh tangloeng vaengah tah amah neh Pathen kah tlang ah hum uh tih a mok.
28 Ní ìgbà náà ni Mose sì sọ ohun gbogbo tí Ọlọ́run ti rán fún Aaroni àti nípa gbogbo iṣẹ́ ìyanu tí Olúwa ti pàṣẹ fún un láti ṣe ní iwájú Farao.
Te phoeiah Moses loh amah a tueih tih miknoek cungkuem neh amah a uen bangla BOEIPA ol boeih te Aaron hma ah a thui pah.
29 Mose àti Aaroni pe gbogbo àwọn àgbàgbà Israẹli jọ.
Moses neh Aaron te cet tih Israel ca a ham boeih te a coi rhoi.
30 Aaroni sọ ohun gbogbo tí Olúwa sọ fún Mose fún wọn, ó sì ṣe iṣẹ́ àmì náà ní ojú àwọn ènìyàn náà.
Te phoeiah BOEIPA loh Moses taengkah a thui ol boeih te Aaron loh a thui pah tih pilnam mikhmuh ah miknoek khaw a tueng sak.
31 Wọ́n sì gbàgbọ́. Nígbà tí wọ́n gbọ́ pé Olúwa ti bẹ àwọn ọmọ Israẹli wò àti pé Olúwa ti gbọ́ nípa ìpọ́njú wọn, wọ́n tẹríba, wọ́n sì sìn ín. Ó sì ṣe àwọn iṣẹ́ àmì náà níwájú àwọn ènìyàn náà.
Pilnam loh a tangnah vaengah tah BOEIPA loh Israel ca a hip tih, amih kah phacipphabaem a hmuh pah te khaw a yaak uh dongah buluk uh tih a bawk uh.

< Exodus 4 >