< Exodus 34 >

1 Olúwa sọ fún Mose pé, “E gé òkúta wàláà méjì jáde bí i ti àkọ́kọ́, Èmi yóò sì kọ àwọn ọ̀rọ̀ ìwé tó wà lára tí àkọ́kọ́ tí ìwọ ti fọ́ sára wọn.
BOEIPA loh Moses taengah, “Namah loh lamhma kah bangla lungto cabael panit saek lamtah te cabael dongah lamhma kah aka rhek cabael dongah aka om ol te ka daek eh.
2 Múra ní òwúrọ̀, kí o sì wá sórí òkè Sinai. Kí o fi ara rẹ hàn mí lórí òkè náà.
Mincang ah sikim la om lamtah mincang neh Sinai tlang la ha luei. Te phoeiah tlang lu ah kamah taengla pahoi pai.
3 Ẹnikẹ́ni kò gbọdọ̀ wá pẹ̀lú rẹ tàbí kí a rí wọn lórí òkè náà; bẹ́ẹ̀ ni agbo àgùntàn tàbí ọwọ́ ẹran kó má ṣe jẹ níwájú òkè náà.”
Tedae na taengah hlang ha luei boel saeh lamtah hlang pakhat pataeng tlang tom ah phoe boel saeh. Boiva neh saelhung khaw tlang dan ah he luem uh boel saeh,” a ti nah.
4 Bẹ́ẹ̀ Mose sì gbẹ́ òkúta wàláà méjì bí ti àkọ́kọ́, ó sì gun orí òkè Sinai lọ ní kùtùkùtù òwúrọ̀, gẹ́gẹ́ bí Olúwa ti pa á láṣẹ fún un; Ó sì gbé òkúta wàláà méjèèjì náà sí ọwọ́ rẹ̀.
Te dongah lungto cabael rhoi te lamhma kah bangla a saek. Mincang ah Moses te thoo tih BOEIPA loh amah a uen bangla Sinai tlang ah yoeng. Te vaengah lungto cabael rhoi te a kut dongah a pom.
5 Nígbà náà ni Olúwa sọ̀kalẹ̀ nínú àwọsánmọ̀, ó sì dúró níbẹ̀ pẹ̀lú rẹ̀, ó sì pòkìkí orúkọ Olúwa.
Te phoeiah BOEIPA te cingmai neh ha rhum tih a taengah pahoi pai. Te vaengah BOEIPA ming neh a doek.
6 Ó sì kọjá níwájú Mose, ó sì ń ké pé, “Olúwa, Olúwa, Ọlọ́run aláàánú àti olóore-ọ̀fẹ́, Ẹni tí ó lọ́ra láti bínú, tí ó pọ̀ ní ìfẹ́ àti olóòtítọ́,
BOEIPA te a hmai ah a pah pah vaengah tah, “YAHWEH, YAHWEH, thinphoei neh lungvatnah Pathen, thintoek a ueh tih sitlohnah neh oltak dongah boeiping coeng.
7 Ẹni tí ó ń pa ìfẹ́ mọ́ fún ẹgbẹ̀rún, ó sì ń dáríjì àwọn ẹni búburú, àwọn ti ń ṣọ̀tẹ̀ àti ẹlẹ́ṣẹ̀. Síbẹ̀ kì í fi àwọn ẹlẹ́bi sílẹ̀ láìjìyà; Ó ń fi ìyà jẹ ọmọ àti àwọn ọmọ wọn fún ẹ̀ṣẹ̀ àwọn baba dé ìran kẹta àti ẹ̀kẹrin.”
Sitlohnah he thawngkhat ham khaw a kueinah dongah thaesainah, boekoeknah neh dumlai khaw a phueih pah. Tedae pa rhoek kah thaesainah a cawh pah te ca rhoek so neh ca kah ca rhoek soah khongthum khongli hil a hmil rhoe a hmil moenih,” tila tamhoe.
8 Mose foríbalẹ̀ lẹ́ẹ̀kan náà ó sì sìn.
Te vaengah Moses tah diklai la koe buluk tih bakop.
9 Ó wí pé, “Olúwa, bí èmi bá rí ojúrere rẹ, nígbà náà jẹ́ kí Olúwa lọ pẹ̀lú wa. Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé, ènìyàn ọlọ́rùn líle ni wọn, dárí búburú àti ẹ̀ṣẹ̀ wa jì, kí o sì gbà wá gẹ́gẹ́ bí ìní rẹ.”
Tedae Moses loh, “Ka Boeipa aw na mik dongah mikdaithen la ka tueng mai khaming. Ka Boeipa kaimih khui ah pongpa laeh. Pilnam he a rhawn mangkhak sitoe cakhaw kaimih kah thaesainah neh kaimih kah tholhnah te khodawkngai lamtah kaimih he m'pang mai,” a ti nah.
10 Nígbà náà ni Olúwa wí pé, “Èmi dá májẹ̀mú kan pẹ̀lú yín. Níwájú gbogbo ènìyàn rẹ Èmi yóò ṣe ìyanu, tí a kò tí ì ṣe ní orílẹ̀-èdè ní gbogbo ayé rí. Àwọn ènìyàn tí ìwọ ń gbé láàrín wọn yóò rí i bí iṣẹ́ tí Èmi Olúwa yóò ṣe fún ọ ti ní ẹ̀rù tó.
Boeipa loh, “Kai loh na pilnam pum hmai ah paipi ka saii ne. Diklai pum neh namtom boeih taengah a suen pawh khobaerhambae te ka saii ni. Te vaengah a khui kah na pilnam boeih loh BOEIPA kah khoboe te hmuh saeh. Nang taengah ka saii te rhih pai saeh.
11 Ṣe ohun tí Èmi pàṣẹ fún ọ lónìí. Èmi lé àwọn ará Amori, àwọn ará Kenaani, àwọn ará Peresi, àwọn ará Hiti, àwọn ará Hifi àti àwọn ará Jebusi jáde níwájú rẹ.
Tihnin ah nang kang uen te namah ham ngaithuen. Na mikhmuh lamloh, Amori neh Kanaan khaw, Khitti neh Perizzi khaw, Khivee neh Jebusi ka haek ne.
12 Máa ṣọ́ra kí o má ba à bá àwọn ti ó n gbé ilẹ̀ náà tí ìwọ ń lọ dá májẹ̀mú, nítorí wọn yóò jẹ́ ìdẹwò láàrín rẹ.
Namah khaw ngaithuen, khohmuen khosa rhoek neh paipi na saii ve ne. Namah khaw a khuila na kun vetih namah khui ah hlaeh la poeh ve.
13 Wó pẹpẹ wọn lulẹ̀, fọ́ òkúta mímọ́ wọn, kí o sì gé òpó Aṣerah wọn. (Ère òrìṣà wọn.)
A hmueihtuk te palet pah lamtah a kaam te phaek pah. Anih kah Asherah khaw vung pah.
14 Ẹ má ṣe sin ọlọ́run mìíràn, nítorí Olúwa, orúkọ ẹni ti ń jẹ́ Òjòwú, Ọlọ́run owú ni.
A ming mah thatlai YAHWEH coeng tih Pathen tah a thatlai thai dongah pathen tloe taengah bakop boeh.
15 “Máa ṣọ́ra kí ẹ má ṣe bá àwọn ènìyàn tí ń gbé ilẹ̀ náà dá májẹ̀mú; nígbà tí wọ́n bá ń ṣe àgbèrè tọ òrìṣà wọn, tí wọ́n sì rú ẹbọ sí wọn, wọn yóò pè yín, ẹ̀yin yóò sì jẹ ẹbọ wọn.
A pathen taengkah a cukhalh neh a pathen te a nawn uh dongah a hmueih te caak ham nang n'khue akhaw khohmuen kah khosa taengah moi na bop ve.
16 Nígbà tí ìwọ bá yàn nínú àwọn ọmọbìnrin wọn fún àwọn ọmọkùnrin rẹ ní ìyàwó, àwọn ọmọbìnrin wọ̀nyí yóò ṣe àgbèrè tọ òrìṣà wọn, wọn yóò sì mú kí àwọn ọmọkùnrin yín náà ṣe bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́.
A canu te na capa ham na lo cakhaw a canu khaw a pathen hnukah cukhalh uh. Te dongah na ca rhoek te amih kah pathen taengah cukhalh hae ni.
17 “Ìwọ kò gbọdọ̀ dá ère òrìṣàkórìṣà fún ara rẹ.
Mueihlawn pathen khaw namah ham saii boeh.
18 “Àjọ àkàrà àìwú ni kí ìwọ máa pamọ́. Fún ọjọ́ méje ni ìwọ yóò jẹ àkàrà aláìwú, gẹ́gẹ́ bí Èmi ti pa á láṣẹ fún ọ. Ṣe èyí ní ìgbà tí a yàn nínú oṣù Abibu, nítorí ní oṣù náà ni ẹ jáde láti Ejibiti wá.
Nang kang uen bangla vaidamding khotue te hnin rhih yaeh lamtah vaidamding mah ca. Egypt lamloh Abib hla dongah na thoh dongah Abib hla ah tingtunnah om saeh.
19 “Gbogbo àkọ́bí inú kọ̀ọ̀kan tèmi ní i ṣe, pẹ̀lú àkọ́bí gbogbo ohun ọ̀sìn rẹ, bóyá ti màlúù tàbí ti àgùntàn.
Bung lamkah cacuek boeih, na boiva dongkah vaito neh tu cacuek a tal boeih he kamah kah ni.
20 Àkọ́bí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ni kí ìwọ kí ó fi ọ̀dọ́-àgùntàn rà padà, ṣùgbọ́n bí ìwọ kò bá rà á padà, dá ọrùn rẹ̀. Ra gbogbo àkọ́bí ọkùnrin rẹ padà. “Ẹnikẹ́ni kò gbọdọ̀ wá síwájú mi ní ọwọ́ òfo.
Tedae laak cacuek tah tu neh lat. Na lat pawt bal atah pahoi at laeh. Na capa caming boeih tah lat lamtah ka mikhmuh ah kuttling la phoe boel saeh.
21 “Ọjọ́ mẹ́fà ni ìwọ yóò ṣiṣẹ́, ṣùgbọ́n ní ọjọ́ keje ìwọ yóò sinmi; kódà ní àkókò ìfúnrúgbìn àti ní àkókò ìkórè ìwọ gbọdọ̀ sinmi.
Hnin rhuk khuiah thotat lamtah hnin rhih dongah tah lophoh vaengah khaw duem lamtah cangah vaengah khaw duem.
22 “Ṣe àjọ ọ̀sẹ̀ pẹ̀lú àkọ́so èso alikama àti àjọ ìkórè ní òpin ọdún.
Cang dongkah cangah vaengkah thaihcuek khotue yalh neh kum thoknah cangyom khotue te namah ham saii.
23 Ní ẹ̀ẹ̀mẹ́ta lọ́dún, gbogbo àwọn ọkùnrin ni kí ó farahàn níwájú Olúwa Olódùmarè, Ọlọ́run Israẹli.
Namah khuikah tongpaca boeih tah kum khat ah voei thum Israel Pathen, Boeipa Yahovah mikhmuh ah phoe saeh.
24 Èmi yóò lé orílẹ̀-èdè jáde níwájú rẹ, Èmi yóò sì mú kí ìpín rẹ fẹ̀, ẹnikẹ́ni kì yóò gba ilẹ̀ rẹ nígbà tí ìwọ bá gòkè lọ ní ìgbà mẹ́ta lọ́dún kọ̀ọ̀kan láti farahàn níwájú Olúwa Ọlọ́run rẹ.
Namtom te na mikhmuh lamloh ka haek vetih na khorhi khaw kang aeh ni. BOEIPA na Pathen mikhmuh la kum khat ah voei thum phoe ham na caeh daengah ni na khohmuen te hlang loh ham veet pawt eh.
25 “Má ṣe ta ẹ̀jẹ̀ ẹbọ sí mi pẹ̀lú ohunkóhun tí ó bá ní ìwúkàrà, kí o má sì ṣe jẹ́ kí ẹbọ ìrékọjá kù títí di òwúrọ̀.
“Kai kah hmueih thii te tolrhu neh ngawn boeh. Yoom khotue kah hmueih loh mincang duela rhaeh boel saeh.
26 “Mú àkọ́ká èso ilẹ̀ rẹ tí ó dára jùlọ wá sí ilé Olúwa Ọlọ́run rẹ. “Ìwọ kò gbọdọ̀ bọ ọmọ ewúrẹ́ nínú omi ọmú ìyá rẹ̀.”
Na khohmuen kah tanglue thaihcuek te BOEIPA na Pathen im la khuen. Maae ca te a manu suktui neh thong boeh,” a ti nah.
27 Olúwa sì wí fún Mose pé, “Kọ àwọn ọ̀rọ̀ wọ̀nyí sílẹ̀, nítorí nípa àwọn ọ̀rọ̀ wọ̀nyí ni Èmi bá ìwọ àti Israẹli dá májẹ̀mú.”
Te phoeiah BOEIPA loh Moses te, “He ol he namah ham daek laeh. Kamah ka dongkah ol nen he nang taeng neh Israel taengah paipi ka saii,” a ti nah.
28 Mose wà níbẹ̀ pẹ̀lú Olúwa fún ogójì ọ̀sán àti ogójì òru láìjẹ oúnjẹ tàbí mu omi. Ó sì kọ ọ̀rọ̀ májẹ̀mú náà òfin mẹ́wàá sára wàláà.
BOEIPA neh a om vaengah khothaih hnin sawmli, khoyin hnin sawmli buh khaw ca pawh, tui khaw o pawh. Te vaengah paipi ol te cabael rhoi dongah ol lung rha la a daek.
29 Nígbà tí Mose sọ̀kalẹ̀ láti orí òkè Sinai pẹ̀lú wàláà ẹ̀rí méjì ní ọwọ́ rẹ̀, òun kò mọ̀ pé ojú òun ń dán nítorí ó bá Olúwa sọ̀rọ̀.
Moses te Sinai tlang lamloh a suntlak vaengah Moses kut dongah olphong cabael rhoi khaw om. Tlang lamloh a suntlak neh amah te a voek pueng dongah a maelhmai vin a phii te khaw Moses loh ming pawh.
30 Nígbà tí Aaroni àti gbogbo àwọn ọmọ Israẹli rí Mose, ojú rẹ̀ ń dán, ẹ̀rù sì ń bà wọ́n láti súnmọ́ ọn.
Aaron neh Israel ca boeih loh Moses te a hmuh uh vaengah a maelhmai vin tarha a phii coeng dongah a taengla mop ham a rhih uh.
31 Ṣùgbọ́n Mose pè wọn; Aaroni àti gbogbo àwọn olórí àjọ padà wá bá a, ó sì bá wọn sọ̀rọ̀.
Tedae Moses loh amih te a khue dongah Aaron neh rhaengpuei kah khoboei boeih tah anih taengla mael uh tih Moses loh amih te a voek.
32 Lẹ́yìn èyí gbogbo àwọn ọmọ Israẹli súnmọ́ ọn, ó sì fún wọn ní gbogbo àṣẹ tí Olúwa fún un lórí òkè Sinai.
Te phoeiah Israel ca rhoek boeih te mop uh. Te vaengah Sinai tlang ah BOEIPA loh anih taengkah a thui boeih te amih a uen.
33 Nígbà tí Mose parí ọ̀rọ̀ sísọ fún wọn. Ó fi ìbòjú bo ojú rẹ̀.
Moses loh amih taengah a thui te a khah van neh a maelhmai te a lumuekhni neh a dah.
34 Ṣùgbọ́n nígbàkígbà tí Mose bá wà níwájú Olúwa láti bá a sọ̀rọ̀, á ṣí ìbòjú náà títí yóò fi jáde. Nígbà tí ó bá sì jáde, á sì sọ fún àwọn ọmọ Israẹli ohun tí a ti pàṣẹ fún un,
Tedae BOEIPA amah te voek ham a mikhmuh la kun tih amah ha pawk daengah lumuekhni a lim pueng. Ha pawk phoeiah tah amah a uen te Israel ca rhoek ham a thui pah.
35 àwọn ọmọ Israẹli sì rí i pé ojú rẹ̀ ń dán. Mose á sì tún fi ìbòjú bo ojú rẹ̀ títí á fi lọ bá Olúwa sọ̀rọ̀.
Israel ca rhoek loh Moses maelhmai te a hmuh vaengah Moses kah maelhmai vin a phii pah. Tedae Boeipa amah te voek ham a kun hil Moses loh lumuekhni neh a maelhmai te a dah.

< Exodus 34 >