< Exodus 33 >
1 Olúwa sọ fún Mose pé, “Fi ìhín yìí sílẹ̀, ìwọ àti àwọn ènìyàn tí o mú gòkè láti Ejibiti wá, kí ẹ sì gòkè lọ sí ilẹ̀ tí Èmi ti pinnu ní ìbúra fún Abrahamu, Isaaki àti Jakọbu wí pé, ‘Èmi yóò fi fún irú-ọmọ rẹ.’
Hina Gode da Mousesema amane sia: i, “Di amola dunu fi amo di da Idibidi sogega gadili masa: ne oule misi. Amo sogebi yolesili, soge amo Na da A: ibalaha: me, Aisage amola Ya: igobe iligaga fi amola ilima imunu ilegele sia: i, amoga masa.
2 Èmi yóò rán angẹli ṣáájú yín, Èmi yóò sì lé àwọn Kenaani, àwọn ará Amori, àwọn ará Hiti, àwọn ará Peresi, àwọn ará Hifi àti àwọn ará Jebusi jáde.
Na da a: igele dunu dilima logo olelemusa: asunasimu. Amola dilia da amo sogega fima: ne, Na da Ga: ina: naide, A:moulaide, Hidaide, Belesaide, Haifaide amola Yebusaide, amo dunu fi huluane sefasimu.
3 Ẹ gòkè lọ sí ilẹ̀ tí ó ń sàn fún wàrà àti oyin. Ṣùgbọ́n èmi kò ní lọ pẹ̀lú yín, nítorí ènìyàn ọlọ́rùn líle ni ẹ̀yin, kí èmi má ba à run yín ní ọ̀nà.”
Dilia da soge noga: idafa, fedege agoane amo ganodini dodo maga: me amola agime hano da hano agoane yogodaha, amoga ahoa. Be Na da dili hame sigi masunu. Bai dilia da dogo gawamaga: i dunu, amola Na da dili logoga dafawanedafa fanelegesa: besa: le, hame masunu.”
4 Nígbà tí àwọn ènìyàn náà gbọ́ ọ̀rọ̀ ìparun wọ̀nyí, wọ́n bẹ̀rẹ̀ sì ní kùn, ẹnìkankan kò sì le è wọ ohun ọ̀ṣọ́ rẹ̀.
Isala: ili dunu da amo sia: nabaloba, da: i dioiba: le dinanu. Ilia da se nababeba: le, bu hame nina: hamoi.
5 Nítorí Olúwa ti wí fún Mose pé, “Sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé, ‘Ènìyàn Ọlọ́rùn líle ní ẹ̀yin, bí Èmi bá lè wá sí àárín yín ni ìṣẹ́jú kan, Èmi lè pa yín run. Nísìnsinyìí, bọ́ ohun ọ̀ṣọ́ rẹ kúrò, Èmi yóò sì gbèrò ohun tí Èmi yóò ṣe pẹ̀lú rẹ.’”
Bai Hina Gode da Mousesema amane sia: i, “Isala: ili dunuma adoma, ‘Dilia da hame nabasu dunu. Na da fa: bihadi fawane dili oule ahoa ganiaba, Na da dafawane dili medole legela: loba. Wali dilia nina: hamoi igi noga: i huluane fadegama. Na da fa: no dilima adi hamoma: beyale dawa: ma.”
6 Bẹ́ẹ̀ àwọn ọmọ Israẹli bọ́ ohun ọ̀ṣọ́ wọn kúrò lára wọn ní òkè Horebu.
Amaiba: le, Isala: ili dunu da Sainai Goumi yolesili, fa: no bu hame nina: hamoi.
7 Mose máa ń gbé àgọ́ náà, ó sì pa á sí ìta ibùdó, ó jìnnà díẹ̀ sí ibùdó, ó pè é ni “Àgọ́ àjọ.” Ẹnikẹ́ni tí ó bá ń béèrè Olúwa yóò lọ sí ibi àgọ́ àjọ náà ní ìta ibùdó.
Eso huluane Isala: ili dunu da ilia Abula Diasu gaguloba, Mousese da Gode Ea Abula Diasu (Da: bena: gele) amo abula diasu gilisisu gadili fonobahadi sedagawane gagusu. Ilia da amo Abula Diasu, “Hina Gode Ea amo ganodini Esalebe Diasu” amo dio asuli. Nowa da Hina Godema sia: sa: imusa: dawa: loba, e da amoga ahoasu.
8 Nígbàkígbà tí Mose bá jáde lọ sí ibi àgọ́, gbogbo ènìyàn á dìde, wọ́n á sì dúró sí ẹnu-ọ̀nà àgọ́ wọn, wọn yóò máa wo Mose títí yóò fi wọ inú àgọ́ náà.
Mousese da Gode Ea Abula Diasuga ahoanoba, dunu huluane da ilia abula diasu holeiga lelebe ba: su. Ilia da Mousese ea Gode Ea Abula Diasu ganodini golili dasu ba: su.
9 Bí Mose ṣe wọ inú àgọ́ náà, ọ̀wọ́n àwọsánmọ̀ yóò sọ̀kalẹ̀, yóò sì dúró sí ẹnu ọnà, nígbà tí Olúwa ń sọ̀rọ̀ pẹ̀lú Mose.
Mousese da ganodini golili sa: i dagoi ba: loba, mumobi da gudu sa: ili, Da: bena: gele ea logo holeiga dialebe ba: su. Amalalu, Hina Gode da mumobi haguli amoga Mousesema sia: dalebe ba: su.
10 Nígbàkígbà tí àwọn ènìyàn bá rí i ti ọ̀wọ́n àwọsánmọ̀ bá dúró ní ẹnu-ọ̀nà àgọ́, gbogbo wọn yóò dìde wọn yóò sì sìn, olúkúlùkù ní ẹnu-ọ̀nà àgọ́ rẹ̀.
Dunu huluane da mumobi Gode Ea Abula Diasu logo holei amoga dialebe ba: loba, ilia da hedolowane begudusu.
11 Olúwa máa ń bá Mose sọ̀rọ̀ lójúkojú, gẹ́gẹ́ bí i pé ènìyàn ń bá ọ̀rẹ́ rẹ̀ sọ̀rọ̀. Nígbà náà ni Mose yóò tún padà lọ sí ibùdó, ṣùgbọ́n ọ̀dọ́mọkùnrin Joṣua ìránṣẹ́ rẹ̀ ọmọ Nuni kò fi àgọ́ sílẹ̀.
Hina Gode da Mousesema sisima hodole, dunu da ea na: iyadoma sia: daha amo defele sia: dasu. Amalalu, Mousese da bu Isala: ili abula diasu gilisisu amoga buhagisu. Be Mousese ea ayeligi fidisu, amo Yosiua (Nane egefe) da Gode Ea Abula Diasuga esalusu.
12 Mose sọ fún Olúwa pé, “Ìwọ ti ń sọ fún mi, ‘Darí àwọn ènìyàn wọ̀nyí,’ ṣùgbọ́n ìwọ kò jẹ́ kí ń mọ ẹni tí ìwọ yóò rán pẹ̀lú mi. Ìwọ ti wí pé, ‘Èmi mọ̀ ọ́n nípa orúkọ, ìwọ sì ti rí ojúrere mi pẹ̀lú.’
Mousese da Hina Godema amane sia: i, “Dafawane! Di da nama amo dunu Ga: ina: ne sogega bisili oule masa: ne sia: i. Be nama oule masunu dunu da nowa, amo di nama hame adoi. Di na noga: le dawa: amola na hou hahawane ba: sa, amo Di da adoi dagoi.
13 Bí ìwọ bá ní inú dídùn pẹ̀lú mi, kọ́ mi ní ọ̀nà rẹ, kí èmi kí ó lè mọ̀ ọ́n, kí n sì le máa wá ojúrere rẹ pẹ̀lú. Rántí wí pé orílẹ̀-èdè yìí ènìyàn rẹ ni.”
Amaiba: le, Di da nama hahawane galea, Dia fa: no hamomu hou nama olelema. Na udigili hame adole ba: sa. Be na da Dia hawa: hamosu noga: le hamoma: ne amola, Di da na hahawane ba: ma: ne, adole ba: sa. Amo dunu fi da Dia dunu fidafa hamoma: ne, Di ilegei dagoi. Amo mae gogolema!”
14 Olúwa dáhùn wí pé, “Ojú mi yóò máa bá ọ lọ, Èmi yóò sì fún ọ ní ìsinmi.”
Hina Gode da amane sia: i, “Na da ani masunu. Na da dima hasalasu hou imunu.”
15 Nígbà náà ni, Mose wí fún un pé, “Bí ojú rẹ kò bá bá wa lọ, má ṣe rán wa gòkè láti ìhín lọ.
Mousese da bu adole i, “Di da ninia hame sigi ahoasea, Di da amo sogebi fisimusa: nini gadili mae asunasima.
16 Báwo ni ẹnikẹ́ni yóò ṣe mọ̀ pé inú rẹ dùn pẹ̀lú mi àti pẹ̀lú àwọn ènìyàn rẹ àyàfi ti o bá bá wa lọ? Kí ni yóò lè yà mí àti àwọn ènìyàn rẹ kúrò lára gbogbo ènìyàn tí ó wà ní ayé?”
Di da nini hame sigi ahoasea, Di da nama amola Dia fi ilima hahawane gala, nowa da dawa: ma: bela: ? Be Di da ninima gilisili ahoasea, dunu huluane da ninia da fi hisu, dunu fi huluane eno amoga afafai, dunu huluane da dawa: mu.”
17 Olúwa sì sọ fún Mose pé, “Èmi yóò ṣe ohun gbogbo tí ìwọ ti béèrè, nítorí inú mi dún sí o, Èmi sì mọ̀ ọ́n nípa orúkọ rẹ̀.”
Hina Gode da Mousesema amane sia: i, “Na da di noga: le dawa: , amola Na da dima hahawane gala. Amaiba: le, Na da dia adole ba: i defele hamomu.”
18 Mose sì wí pé, “Nísinsin yìí fi ògo rẹ hàn mí.”
Amalalu, Mousese da Ema amane adole ba: i, “Na da Dia hadigi sinenemegi amo ba: mu hanai galebe.”
19 Olúwa sì wí pé, “Èmi yóò sì mú gbogbo ìre mí kọjá níwájú rẹ, Èmi yóò sì pòkìkí orúkọ Olúwa níwájú rẹ. Èmi yóò ṣàánú fún ẹni tí Èmi yóò ṣàánú fún, Èmi yóò sì ṣoore-ọ̀fẹ́ fún ẹni tí Èmi yóò ṣoore-ọ̀fẹ́ fún.
Hina Gode da bu adole i, “Defea! Na da Na hadigi hou di ba: ma: ne olelemu. Na hadigi Dio amola dima adomu. Na da Gode Hinadafa. Na da nowa dunu gogolema: ne olofomusa: dawa: sea, Na da gogolema: ne olofomu. Nowa dunuma Na da asigima: ne dawa: sea, Na da ema asigimu.
20 Ṣùgbọ́n,” ó wí pé, “Ìwọ kò le è rí ojú mi, nítorí kò sí ènìyàn kan tí ń rí mi, tí ó lè yè.”
Na da Na odagi dima hame olelemu. Bai nowa Na odagi ba: sea, e da bogomu.
21 Olúwa sì wí pé, “Ibìkan wà lẹ́gbẹ̀ẹ́ ọ̀dọ̀ mi, níbi tí o ti lè dúró lórí àpáta.
Be amo gele da Na dafulili diala. Amoga di leloma.
22 Nígbà tí ògo mi bá kọjá, Èmi yóò gbé ọ sínú pàlàpálá àpáta, Èmi yóò sì bò ọ́ pẹ̀lú ọwọ́ mi títí Èmi yóò fi rékọjá.
Amasea, Na hadigi sinenemegi da baligisia, Na da di gele gelabo ganodini sanasili, Na loboga dedebomu. Amasea, Na da baligimu.
23 Nígbà tí Èmi yóò mú ọwọ́ mi kúrò, ìwọ yóò sì rí ẹ̀yìn mi; ṣùgbọ́n ojú mi ni o kò ní rí.”
Amasea, Na da Na lobo bu lalegamu. Di da Na baligi ba: mu be Na odagi ba: mu da sema gala.”