< Exodus 32 >

1 Nígbà tí àwọn ènìyàn rí i pé Mose pẹ́ kí ó tó sọ̀kalẹ̀ láti orí òkè wá, wọn péjọ yí Aaroni ká, wọ́n sì wí pé, “Wá, dá òrìṣà tí yóò máa ṣáájú wa fún wa. Bí ó ṣe ti Mose tí ó mú wa jáde láti Ejibiti wá, àwa kò mọ́ ohun tí ó ti ṣẹlẹ̀ sí i.”
Xelq Musaning taghdin chüshmey hayal bolup qalghinini körüp, Harunning qéshigha yighilip uninggha: — Sen qopup, bizge aldimizda yol bashlap mangidighan bir ilah yasap bergin! Chünki bizni Misir zéminidin chiqirip kelgen Musa dégen héliqi kishige néme bolup ketkenlikini bilmeymiz, — déyishti.
2 Aaroni dá wọn lóhùn pé, “Ẹ bọ́ òrùka wúrà tí ó wà ní etí àwọn ìyàwó yín, tí àwọn ọmọkùnrin yín, àti tí àwọn ọmọbìnrin yín, kí ẹ sì mú wọn wá sí ọ̀dọ̀ mi.”
Harun ulargha: — Xotunliringlar bilen oghul-qizliringlarning qulaqliridiki altun zire halqilarni chiqirip, méning qéshimgha élip kélinglar, dédi.
3 Bẹ́ẹ̀ ni gbogbo àwọn ènìyàn bọ́ òrùka etí wọn, wọn sì kó wọn wá fún Aaroni.
Shuning bilen pütkül xelq öz qulaqliridiki altun zire halqilarni chiqirip Harunning qéshigha élip keldi.
4 Ó sì gbà wọ́n ní ọwọ́ wọn, ó sì fi ṣe ohun ọnà fínfín, ó sì dà á ní àwòrán ẹgbọrọ màlúù. Nígbà náà ni wọn wí pé, “Israẹli, wọ̀nyí ni òrìṣà, ti ó mú un yín jáde wá láti Ejibiti.”
U bularni ularning qolidin élip, iskine bilen quyma bir mozayni yasatquzdi. Shuning bilen ular: — Ey Israil, séni Misir zéminidin chiqirip kelgen Xudayinglar mana budur! — déyishti.
5 Nígbà ti Aaroni rí èyí, ó kọ́ pẹpẹ kan níwájú ẹgbọrọ màlúù náà, ó sì kéde pé, “Lọ́la ni àjọyọ̀ sí Olúwa.”
Harun uni körüp uning aldida bir qurban’gahni yasitip andin: «Ete Perwerdigar üchün bir héyt ötküzülidu», dep élan qildi.
6 Bẹ́ẹ̀ ni àwọn ènìyàn dìde ní kùtùkùtù ọjọ́ kejì, wọ́n sì rú ẹbọ sísun, wọ́n sì mú ẹbọ àlàáfíà wá. Lẹ́yìn náà wọ́n jókòó láti jẹ àti láti mu, wọ́n sì dìde láti ṣeré.
Etisi ular seher qopup, köydürme qurbanliqlarni sunup, inaqliq qurbanliqlirinimu keltürdi; andin xalayiq olturup yep-ichishti, qopup eysh-ishret qilishti.
7 Olúwa sì wí fún Mose pé, “Sọ̀kalẹ̀ lọ, nítorí àwọn ènìyàn rẹ, tí ìwọ mú gòkè wá láti Ejibiti, wọ́n ti dẹ́ṣẹ̀.
Shu chaghda Perwerdigar Musagha: — Ornungdin tur, tézdin peske chüshkin! Chünki sen Misir zéminidin chiqirip kelgen xelqing buzuqchiliqqa bérilip ketti.
8 Wọ́n ti yí kánkán kúrò nípa ọ̀nà tí mo ti mo pàṣẹ fún wọn, wọ́n sì ti dá ère ẹgbọrọ màlúù fún ara wọn. Wọ́n ti foríbalẹ̀ fún un, wọ́n sì ti rú ẹbọ sí i, wọ́n sì ti sọ pé, ‘Israẹli wọ̀nyí ní òrìṣà tí ó mú un yín jáde láti Ejibiti wá.’”
Men ulargha buyrughan yoldin shunche tézla chetnep, özliri üchün bir quyma mozayni yasap, uninggha choqunup qurbanliq keltürüshti hemde: «Ey Israil, séni Misir zéminidin chiqirip kelgen Xudaying mana shudur!», déyishti, — dédi.
9 Olúwa wí fún Mose pé, “Èmi ti rí àwọn ènìyàn wọ̀nyí, wọ́n sì jẹ́ ọlọ́rùn líle ènìyàn.
Andin Perwerdigar Musagha: — Mana, bu xelqni körüp qoydum; mana, ular derweqe boyni qattiq bir xelqtur.
10 Ǹjẹ́ nísinsin yìí fi mí sílẹ̀, nítorí kí ìbínú mi lè gbóná sí wọn, kí Èmi sì lè pa wọ́n run. Nígbà náà ni Èmi yóò sọ ọ́ di orílẹ̀-èdè ńlá.”
Emdi Méni tosma, Men ghezep otumni ularning üstige chüshürüp, ularni yutuwétimen; andin séni ulugh bir el qilimen, — dédi.
11 Ṣùgbọ́n Mose kígbe fún ojúrere Olúwa Ọlọ́run rẹ̀, ó wí pé, “Olúwa, èéṣe tí ìbínú rẹ yóò ṣe gbóná sí àwọn ènìyàn rẹ, tí ìwọ mú jáde láti Ejibiti wá pẹ̀lú agbára ńlá àti ọwọ́ agbára?
Lékin Musa Xudasi Perwerdigardin ötünüp iltija qilip mundaq dédi: — Ey Perwerdigar, némishqa sen ghezep otungni Özüng zor qudret we küchlük qol bilen Misir zéminidin chiqirip kelgen xelqingning üstige chüshürisen?
12 Èéṣe tí àwọn ará Ejibiti yóò ṣe wí pé, ‘Nítorí ibi ni ó ṣe mọ̀ ọ́n mọ̀ mú wọn jáde, láti pa wọ́n ní orí òkè àti láti gbá wọn kúrò lórí ayé’? Yípadà kúrò nínú ìbínú rẹ tí ó múná, yí ọkàn padà, kí o má sì ṣe mú ìparun wá sórí àwọn ènìyàn rẹ.
Misirliqlar mazaq qilip: — Ularning béshigha bala chüshürüsh üchün, ularni taghlarning üstide öltürüp yer yüzidin yoqitish üchün, [ularning Xudasi] ularni élip ketti, — déyishsunmu? Öz otluq ghezipingdin yénip, Öz xelqingge balayi’apet keltürüsh niyitingdin yan’ghaysen!
13 Rántí àwọn ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ Abrahamu, Isaaki àti Israẹli, ẹni tí ìwọ búra fún fúnra rẹ̀, ‘Tí o wí fún wọn pé, Èmi yóò mú irú-ọmọ rẹ pọ̀ bí ìràwọ̀ ojú ọ̀run, Èmi yóò sì fún irú-ọmọ rẹ ní gbogbo ilẹ̀ tí mo ti pinnu fún wọn, yóò sì jẹ́ ogún ìní wọn láéláé.’”
Öz qulliring Ibrahim, Ishaq we Israilni yad qilghin; Sen ulargha qesem bilen wede qilip: «Neslinglarni asmandiki yultuzlardek awutimen, Özüm uning toghrisida sözligen mushu zéminning hemmisini neslinglargha bérimen, ular uninggha menggü igidarchiliq qilidighan bolidu» dégenidingghu, — dédi.
14 Nígbà náà ni Olúwa dáwọ́ ìbínú rẹ̀ dúró, kò sì mú ìparun náà tí ó sọ wá sórí àwọn ènìyàn rẹ̀ mọ́.
Shuning bilen Perwerdigar Öz xelqining üstige: «Balayi’apet chüshürimen» dégen niyitidin yandi.
15 Mose sì yípadà, ó sì sọ̀kalẹ̀ láti orí òkè náà pẹ̀lú òkúta wàláà ẹ̀rí méjì ní ọwọ́ rẹ̀. Wọ́n kọ ìwé síhà méjèèjì, iwájú àti ẹ̀yin.
Musa keynige burulup, ikki höküm-guwahliq taxtiyini qoligha élip taghdin chüshti. Taxtaylarning ikki teripige sözler pütülgenidi; u yüzigimu, bu yüzigimu pütüklük idi.
16 Iṣẹ́ Ọlọ́run sì ni wàláà náà; ìkọ̀wé náà jẹ́ ìkọ̀wé Ọlọ́run, a fín in sára àwọn òkúta wàláà náà.
Bu taxtaylar bolsa Xudaning Özining yasighini, pütülgenliri bolsa Xudaning Özining pütkini idi, u taxtaylargha oyulghanidi.
17 Nígbà tí Joṣua gbọ́ ariwo àwọn ènìyàn tí wọ́n ń kígbe, ó sọ fún Mose pé, “Ariwo ogun wà nínú àgọ́.”
Yeshua xelqning kötürgen chuqan-sürenlirini, warqirashlirini anglap Musagha: — Chédirgahdin jengning xitabi chiqiwatidu, dédi.
18 Mose dáhùn pé, “Kì í ṣe ariwo fún ìṣẹ́gun, kì í ṣe ariwo fún aṣẹ́gun; ohùn àwọn tí ń kọrin ni mo gbọ́.”
Lékin u jawab bérip: — Angliniwatqan awaz ne nusret tentenisi emes, ne meghlubiyetning peryadi emes, belki naxsha-küy sadasi! — dédi.
19 Nígbà tí Mose dé àgọ́, ó sì rí ẹgbọrọ màlúù náà àti ijó, ìbínú rẹ gbóná, ó sì sọ wàláà ọwọ́ rẹ̀ sílẹ̀, ó sì fọ́ wọn sí wẹ́wẹ́ ní ìsàlẹ̀ òkè náà.
Musa chédirgahgha yéqin kélip, mozayni we jamaetning ussulgha chüshüp ketkenlikini körüp shundaq derghezep boldiki, taxtaylarni qolidin tashlap taghning tüwide chéqiwetti.
20 Ó sì gbé ẹgbọrọ màlúù tí wọ́n ṣe, ó sì fi iná jó wọn; ó sì lọ̀ wọ́n kúnná, ó dà á sínú omi, ó sì mú àwọn ọmọ Israẹli mu ún.
Andin ular yasighan mozayni otqa sélip köydürüp, uni yanjip kukum-talqan qilip, su üstige chéchip Israillarni ichishke mejburlidi.
21 Mose sọ fún Aaroni pé, “Kí ni àwọn ènìyàn wọ̀nyí ṣe sí ọ, tí ìwọ ṣe mú wọn dá ẹ̀ṣẹ̀ ńlá yìí?”
Andin Musa Harun’gha: Sen ularni shunche éghir gunahqa patquzghudek, mushu xelq sanga néme qildi? — dédi.
22 Aaroni dáhùn wí pé, “Má ṣe bínú olúwa mi. Ìwọ mọ bí àwọn ènìyàn yìí ṣe burú tó.
Harun jawab bérip: — Xojamning ghezep-achchiqi tutashmighay! Bu xelqning qandaq ikenlikini, ularning zezillikke mayil ikenlikini obdan bilisen.
23 Wọ́n sọ fún mi pé, ‘Ṣe òrìṣà fún wa, tí yóò máa ṣáájú wa. Bí ó ṣe ti Mose ẹni tí ó mú wa jáde láti Ejibiti wá àwa kò mọ ohun tí ó ṣẹlẹ̀ sí i.’
Ular manga: — «Bizge aldimizda yol bashlap mangidighan bir ilahni yasap bergin; chünki bizni Misir zéminidin chiqirip kelgen Musa dégen shu ademge néme bolghinini bilmeymiz», dédi.
24 Bẹ́ẹ̀ ni mo sọ fún wọn pé, ‘Ẹnikẹ́ni tí ó ní òrùka wúrà, kí ó bọ́ ọ wá.’ Nígbà náà ni wọ́n fún mi ní wúrà, mo sì jù ú sínú iná, a sì fi ṣe ẹgbọrọ màlúù yìí!”
Men ulargha: «Kimde altun bolsa shuni chiqirip bersun» désem, ular manga tapshurup berdi; men uni otqa tashliwidim, mana, bu mozay chiqti, — dédi.
25 Mose rí pé àwọn ènìyàn náà kò ṣe ṣàkóso àti pé Aaroni ti sọ wọ́n di aláìlákóṣo láàrín àwọn ọ̀tá tí ó dìde sí wọn.
Musa xelqning qandaqsige tizginsiz bolup ketkenlikini kördi; chünki Harun ularni düshmenlirining aldida mesxire obyékti bolushqa öz meylige qoyuwetkenidi.
26 Bẹ́ẹ̀ ni Mose dúró ní ẹnu-ọ̀nà àgọ́, ó sì wí pé, “Ẹnikẹ́ni tí ó bá wà fún Olúwa, kí ó wá sí ọ̀dọ̀ mi.” Gbogbo àwọn ará Lefi sì péjọ yí i ká.
Musa chédirgahning kirish éghizigha bérip, shu yerde turup: — Kimki Perwerdigarning teripide bolsa méning yénimgha kelsun! — dédi. Shuni déwidi, Lawiylarning hemmisi uning qéshigha yighildi.
27 Nígbà náà ni ó sọ fún wọn pé, “Èyí ni Olúwa, Ọlọ́run Israẹli, wí pé, ‘Kí olúkúlùkù ọkùnrin kí ó kọ idà rẹ̀ sí ẹ̀gbẹ́ rẹ̀. Ẹ lọ padà, kí ẹ jà láti àgọ́ kan dé òmíràn, olúkúlùkù kí ó pa arákùnrin rẹ̀ ọ̀rẹ́ rẹ̀ àti aládùúgbò rẹ.’”
U ulargha: — Israilning Xudasi Perwerdigar mundaq deydu: — «Herbir kishi öz qilichini yanpishigha ésip, chédirgahning ichige kirip, bu chétidin u chétigiche kézip yürüp, herbiri öz qérindishini, öz dost-buradirini, öz qoshnisini öltürsun!» — dédi.
28 Àwọn ará Lefi ṣe gẹ́gẹ́ bí Mose ṣe pàṣẹ, àti ní ọjọ́ náà àwọn tí ó kú tó ẹgbẹ̀rún mẹ́ta ènìyàn.
Shuning bilen Lawiylar Musaning buyrughini boyiche ish kördi; shu küni xelqning ichidin üch ming kishi öltürüldi.
29 Nígbà náà ni Mose wí pé, “Ẹ ti ya ara yín sọ́tọ̀ fún Olúwa lónìí, nítorí ìwọ ti dìde sí àwọn ọmọ rẹ àti arákùnrin rẹ, ó sì ti bùkún fún ọ lónìí.”
Andin Musa: — Herbiringlar bügün özünglarni Perwerdigargha xas bolushqa atidinglar; chünki herbiringlar hetta öz oghlunglar hem qérindishinglarnimu ayimidinglar; shuning bilen bügün bext-beriketni üstünglargha chüshürdunglar, dédi.
30 Ní ọjọ́ kejì Mose sọ fún àwọn ènìyàn náà pé, “Ẹ̀yin ti dá ẹ̀ṣẹ̀ tí ó pọ̀. Ṣùgbọ́n nísinsin yìí èmi yóò gòkè lọ bá Olúwa; bóyá èmi lè ṣe ètùtù fún ẹ̀ṣẹ̀ yín.”
Etisi Musa xelqqe söz qilip: — Siler derweqe nahayiti éghir bir gunah sadir qildinglar. Emdi mana, men Perwerdigarning aldigha chiqimen; gunahinglar üchün kafaret keltüreleymenmikin, — dédi.
31 Bẹ́ẹ̀ ni Mose padà tọ Olúwa lọ, ó sì wí pé, “Yé, kí ni ẹ̀ṣẹ̀ ńlá tí àwọn ènìyàn ti dá yìí! Wọ́n ti ṣe òrìṣà wúrà fún ara wọn.
Shuning bilen Musa Perwerdigarning aldigha yénip bérip: — Hey...! Bu xelq derweqe éghir bir gunah sadir qilip, özlirige altundin ilahlarni yasaptu!
32 Ṣùgbọ́n nísinsin yìí, jọ̀wọ́ dárí ẹ̀ṣẹ̀ wọn jì wọ́n ṣùgbọ́n tí kò bá sì ṣe bẹ́ẹ̀, pa orúkọ mi rẹ́ kúrò nínú ìwé tí ìwọ ti kọ.”
Lékin emdi Sen ularning gunahini epu qilishqa unighaysen..., unimisang, ismimni Özüng yazghan deptiringdin öchürüwetkin! — dédi.
33 Olúwa dá Mose lóhùn pé, “Ẹnikẹ́ni tí ó bá dẹ́ṣẹ̀ sí mi, Èmi yóò pa á rẹ́ kúrò nínú ìwé mi.
Perwerdigar Musagha jawab bérip: — Kimki Méning aldimda gunah qilghan bolsa, uning étini Öz deptirimdin öchürüwétimen.
34 Ǹjẹ́ nísinsin yìí lọ, máa darí àwọn ènìyàn yìí lọ sí ibi ti mo sọ, angẹli mi yóò sì máa lọ ṣáájú yín. Ìgbà ń bọ̀ fún mi tì Èmi yóò ṣe ìbẹ̀wò, Èmi yóò fi yà jẹ wọ́n fún ẹ̀ṣẹ̀ wọn.”
Emdi sen bérip, Men sanga éytqan jaygha xelqni bashlap barghin. Mana, Méning Perishtem aldingda mangidu. Lékin ulargha jaza béridighan künüm kelgende, ulargha gunahi üchün jaza bérimen, dédi.
35 Olúwa sì yọ àwọn ènìyàn náà lẹ́nu, pẹ̀lú ààrùn nítorí ohun tí wọ́n ṣe ní ti ẹgbọrọ màlúù tí Aaroni ṣe.
Bu sözdin kéyin Perwerdigar xelqning Harunning qoli bilen mozayni quydurup yasatqini üchün ularni waba bilen jazalidi.

< Exodus 32 >