< Exodus 30 >
1 “Ìwọ yóò sì ṣe pẹpẹ igi kasia kan; máa jó tùràrí lórí rẹ̀.
“Thondeka kĩgongona kĩa mbaũ cia mũgaa gĩa gũcinagĩra ũbumba.
2 Kí igun mẹ́rẹ̀ẹ̀rin rẹ̀ ṣe déédé, kí ó jẹ́ ìdajì mita ní gígùn, ìdajì mita ní fífẹ̀ àti ìgbọ̀nwọ́ méjì ni gíga rẹ̀—kí ìwo rẹ̀ wà pẹ̀lú rẹ̀.
Nĩgĩkorwo kĩiganaine mĩena yothe mũkono ũmwe kũraiha na mũkono ũmwe kwarama na mĩkono ĩĩrĩ kũraiha na igũrũ, hĩa ciakĩo ituĩke kĩndũ o ro kĩmwe na kĩgongona.
3 Ìwọ yóò sì bo òkè rẹ̀, gbogbo ìhà rẹ̀ àti ìwo rẹ̀ pẹ̀lú u kìkì wúrà, ìwọ yóò sì ṣe wúrà gbà á yíká.
Kĩgemie igũrũ, o na mĩena yothe, o na hĩa ciakĩo, na thahabu therie, na ũgĩtirihe na mũcibi wa thahabu ũgĩthiũrũrũkĩrie.
4 Ìwọ yóò sì ṣe òrùka wúrà méjì fún pẹpẹ náà níṣàlẹ̀ ìgbátí méjèèjì ní òdìkejì ìhà rẹ̀—láti gbá àwọn òpó rẹ̀ mú, láti lè máa fi gbé e.
Thondekera kĩgongona kĩu mĩrĩnga ĩĩrĩ, ũmĩoherere thĩ wa mũcibi ũcio, ĩĩrĩ mwena ũmwe, na ĩĩrĩ mwena ũrĩa ũngĩ ĩnyiitagĩrĩre mĩtĩ ĩrĩa mĩraaya ĩtũmagĩrwo gũgĩkuua.
5 Ìwọ yóò sì ṣe òpó igi kasia, ìwọ yóò sì bọ́ wọ́n pẹ̀lú wúrà.
Thondeka mĩtĩ mĩraaya ya mbaũ cia mũgaa, na ũmĩgemie na thahabu.
6 Ìwọ yóò gbé pẹpẹ náà sí iwájú aṣọ ìkélé, èyí tí ó wà níwájú àpótí ẹ̀rí níwájú ìtẹ́ àánú èyí tí ó wà lórí àpótí ẹ̀rí níbi ti èmi yóò ti máa bá ọ pàdé.
Iga kĩgongona kĩu mbere ya gĩtambaya gĩa gũcuurio kĩrĩa kĩrĩ mbere ya ithandũkũ rĩa Ũira, mbere ya gĩtĩ gĩa tha kĩrĩa kĩrĩ igũrũ rĩa ithandũkũ rĩa Ũira, harĩa ngaacemania nawe.
7 “Aaroni yóò sì máa jó tùràrí dídùn lórí pẹpẹ náà ní àràárọ̀, nígbà tí ó tún àwọn fìtílà náà ṣe.
“Harũni no nginya acinĩre ũbumba mũnungi wega hau igũrũ rĩa kĩgongona o rũciinĩ rĩrĩa egũthondeka matawa.
8 Aaroni yóò sì tún jó tùràrí nígbà tí ó bá tan fìtílà ní àṣálẹ́, bẹ́ẹ̀ ní tùràrí yóò máa jó títí láé níwájú Olúwa fún àwọn ìran tó ń bọ̀.
No nginya acine ũbumba rĩngĩ agĩakia matawa hwaĩ-inĩ kũrĩ mairia, nĩgeetha ũbumba ũikarage ũgĩcinagwo mahinda mothe mbere ya Jehova, njiarwa na njiarwa iria igooka.
9 Ẹ̀yin kò gbọdọ̀ mú àjèjì tùràrí wá sórí pẹpẹ yìí tàbí ẹbọ sísun kankan tàbí ọrẹ oúnjẹ, bẹ́ẹ̀ ni ẹ̀yin kò gbọdọ̀ da ẹbọ ohun mímu sórí i rẹ̀.
Ndũkanacinĩre ũbumba wa mũthemba ũngĩ kĩgongona-inĩ gĩkĩ kana ũrutĩre ho iruta rĩa njino, kana rĩa mũtu, na ndũkanaitĩrĩrie iruta rĩa kũnyuuo igũrũ rĩakĩo.
10 Aaroni yóò sì máa ṣe ètùtù sórí àwọn ìwo rẹ̀ lẹ́ẹ̀kan lọ́dún. Òun yóò sì máa ṣe ètùtù ọdọọdún yìí pẹ̀lú ẹ̀jẹ̀ ẹbọ ètùtù fún ìran tó ń bọ̀. Mímọ́ jùlọ ni sí Olúwa.”
Harũni nĩarutage horohio hĩa-inĩ cia kĩgongona kĩu o mwaka riita rĩmwe. Horohio ĩno ya o mwaka no nginya ĩrutagwo na thakame ya iruta rĩa kũhoroheria mehia, nginya njiarwa iria igooka. Horohio ĩyo nĩ igongona itheru mũno harĩ Jehova.”
11 Nígbà náà ni Olúwa wí fún Mose pé,
Hĩndĩ ĩyo Jehova akĩĩra Musa atĩrĩ,
12 “Nígbà tí ìwọ bá ka iye àwọn ọmọ Israẹli láti mọ iye wọn, ẹnìkọ̀ọ̀kan wọn gbọdọ̀ mú ìràpadà ọkàn rẹ̀ wá fún Olúwa ní ìgbà tí o bá ka iye wọn. Nígbà náà ni àjàkálẹ̀-ààrùn kì yóò súnmọ́ wọn, nígbà tí o bá ń ka iye wọn.
“Rĩrĩa ũgũtara andũ a Isiraeli-rĩ, o mũndũ no nginya arutagĩre Jehova kĩndũ gĩa gũkũũra muoyo wake rĩrĩa egũtarwo. Na gũtirĩ mũthiro ũkaamakora ũkĩmatara.
13 Olúkúlùkù ẹrù tí ó bá kọjá lọ sọ́dọ̀ àwọn tí a ti kà yóò san ìdajì ṣékélì, gẹ́gẹ́ bí ṣékélì ibi mímọ́, èyí tí ó wọn ogún gera. Ìdajì ṣékélì yìí ní ọrẹ fún Olúwa.
Mũndũ o wothe ũrĩkĩraga agathiĩ mwena wa andũ arĩa marĩkĩtie gũtarwo, nĩarĩrutaga nuthu ya cekeri kũringana na ũrĩa cekeri ya harĩa haamũre ĩtariĩ ĩrĩa ĩrĩ na ũritũ wa geera mĩrongo ĩĩrĩ. Nuthu ĩyo ya cekeri nĩ iruta kũrĩ Jehova.
14 Gbogbo àwọn tí ó bá kọjá sínú àwọn tí a kà láti ẹni ogún ọdún tàbí jù bẹ́ẹ̀ lọ, ni yóò fi ọrẹ fún Olúwa.
Arĩa othe marĩkĩraga magathiĩ mwena wa arĩa marĩkĩtie gũtarwo, marĩ na ũkũrũ wa mĩaka mĩrongo ĩĩrĩ na makĩria, no nginya maheage Jehova iruta rĩu.
15 Àwọn olówó kì yóò san ju ìdajì ṣékélì lọ, àwọn tálákà kò sì gbọdọ̀ dín ní ìdajì ṣékélì nígbà tí ẹ̀yin bá mú ọrẹ wá fún Olúwa láti ṣe ètùtù fún ọkàn yín.
Arĩa atongu matirĩheanaga makĩria ya nuthu ya cekeri, nao arĩa athĩĩni matirĩheanaga kĩndũ kĩnini gũkĩra nuthu ya cekeri hĩndĩ ya kũrutĩra Jehova horohio ya mĩoyo yao.
16 Ìwọ yóò sì gba owó ètùtù náà lọ́wọ́ àwọn ọmọ Israẹli, ìwọ yóò sì fi lélẹ̀ fún ìsìn àgọ́ àjọ. Yóò jẹ́ ìrántí fún àwọn ọmọ Israẹli níwájú Olúwa, láti ṣe ètùtù fún ọkàn yín.”
Amũkĩra mbeeca cia horohio kuuma kũrĩ andũ a Isiraeli nawe ũcihũthĩre ũtungata-inĩ wa Hema-ya-Gũtũnganwo. Ũguo ũgaatuĩka kĩririkano kĩa andũ a Isiraeli mbere ya Jehova makĩrutĩra mĩoyo yao horohio.”
17 Nígbà náà ni Olúwa wí fún Mose pé,
Ningĩ Jehova akĩĩra Musa atĩrĩ,
18 “Ìwọ yóò sì ṣe agbada idẹ kan, àti ẹsẹ̀ rẹ̀ idẹ, fún wíwẹ̀. Ìwọ yóò sì gbé e sí àárín àgọ́ àjọ àti pẹpẹ náà, ìwọ yóò sì pọn omi sínú rẹ̀.
“Thondeka kĩraĩ gĩa gwĩthambagĩra gĩa gĩcango, kĩrĩ na kĩgũrũ gĩakĩo gĩa gĩcango. Ũkĩige gatagatĩ ka Hema-ya-Gũtũnganwo na kĩgongona, na ũgĩĩkĩre maaĩ.
19 Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ yóò máa wẹ ọwọ́ àti ẹsẹ̀ wọn pẹ̀lú omi tí ó wà nínú rẹ̀.
Harũni na ariũ ake marĩĩthambaga moko mao na nyarĩrĩ na maaĩ macio.
20 Nígbàkígbà tí wọ́n bá wọ inú àgọ́ àjọ, wọ́n yóò wẹ̀ pẹ̀lú omi nítorí kí wọ́n má ba à kú. Bákan náà, nígbà tí wọ́n bá súnmọ́ ibi pẹpẹ láti ṣe ìsìn, láti mú ẹbọ ti a fi iná sun wá fún Olúwa,
Rĩrĩa rĩothe marĩtoonyaga Hema-ya-Gũtũnganwo, marĩĩthambaga na maaĩ nĩgeetha matigakue. O na ningĩ rĩrĩa mathengerera kĩgongona nĩguo marutĩre Jehova iruta rĩa gũcinwo na mwaki,
21 wọn yóò sì wẹ ọwọ́ wọn àti ẹsẹ̀ wọn, nítorí kí wọn máa ba à kú. Èyí ni yóò jẹ́ ìlànà títí láé fún Aaroni àti irú àwọn ọmọ rẹ̀ fún ìrandíran wọn.”
marĩĩthambaga moko na nyarĩrĩ nĩgeetha matigakue. Ũndũ ũcio ũgaatuĩka watho wa kũrũmĩrĩrwo tene na tene nĩ Harũni na njiaro ciake, na njiarwa ciao ciothe iria igooka.”
Ningĩ Jehova akĩĩra Musa atĩrĩ,
23 “Ìwọ yóò mú ààyò tùràrí olóòórùn sí ọ̀dọ̀ rẹ; ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta ṣékélì (kilogiramu mẹ́fà) tí òjìá ṣíṣàn, ìdajì bí ó bá yẹ àádọ́ta lé nígba ṣékélì tí kinamoni dídùn, àti kénì dídùn àádọ́ta lé nígba ṣékélì,
“Oya mahuti maya manungi wega: cekeri 500 cia manemane ĩrĩa ndwekie, nuthu yamo (nacio icio nĩ cekeri 250) cia ndarathini nungi wega, na cekeri 250 cia karamathi nungi wega,
24 kasia ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta ṣékélì gbogbo rẹ̀ ní ìlànà ṣékélì ibi mímọ́ àti hínì òróró olifi kan (lita mẹ́rin).
cekeri 500 cia mwĩnũ, ciothe kũringana na cekeri ya handũ-harĩa-haamũre, na hini ya maguta ma mĩtamaiyũ.
25 Ṣe ìwọ̀nyí ní òróró mímọ́ ìkunra, tí a pò gẹ́gẹ́ bí olùṣe òórùn dídùn tì í ṣe. Yóò jẹ òróró mímọ́ ìtasórí.
Indo ici ũcithondeke ituĩke maguta matheru ma gũitanĩrĩrio matukanĩtio makanunga wega marutĩirwo wĩra nĩ mũthondeki mũũgĩ wa maguta. Macio matuĩke maguta matheru ma gũitanagĩrĩrio.
26 Ìwọ yóò sì lò ó láti ya àgọ́ sí mímọ́ àti àpótí ẹ̀rí náà,
Ningĩ ũhũthĩre maguta macio gũitĩrĩria Hema-ya-Gũtũnganwo, na ithandũkũ rĩa Ũira,
27 tábìlì àti gbogbo ohun èlò rẹ̀, ọ̀pá fìtílà àti ohun èlò rẹ̀, àti pẹpẹ tùràrí,
na metha na indo ciayo ciothe, na mũtĩ wa kũigĩrĩrwo matawa na indo ciaguo, na kĩgongona gĩa gũcinĩra ũbumba, na
28 pẹpẹ ẹbọ sísun àti gbogbo ohun èlò rẹ̀, àti agbada pẹ̀lú ẹsẹ̀ rẹ̀.
kĩgongona kĩa iruta rĩa njino na indo ciakĩo ciothe, na kĩraĩ na kĩgũrũ gĩakĩo.
29 Ìwọ yóò sì sọ wọ́n di mímọ́, nítorí kí wọn lè jẹ́ mímọ́ jùlọ, àti ohunkóhun tí ó bá fi ọwọ́ kàn wọn yóò di mímọ́.
Nĩũgaciamũra nĩgeetha ituĩke theru mũno makĩria, nakĩo kĩrĩa gĩothe gĩgacihutia nĩgĩgatuĩka gĩtheru.
30 “Ìwọ yóò sì ta òróró sí orí Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀, ìwọ yóò sì sọ wọ́n di mímọ́, nítorí kí wọn lè sìn mí bí àlùfáà.
“Itĩrĩria Harũni na ariũ ake maguta ũmaamũre nĩgeetha mandungatagĩre marĩ athĩnjĩri-Ngai.
31 Ìwọ yóò sì sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé, ‘Èyí ni yóò ṣe òróró mímọ́ ìtasórí mi fún ìrandíran tó ń bọ̀.
Ĩra andũ a Isiraeli atĩrĩ, ‘Maya nĩmo maguta makwa marĩa matheru ma gũitanagĩrĩrio ma njiarwa iria igooka.
32 Má ṣe dà á sí ara ènìyàn kí o má sì ṣe ṣe òróró kankan ni irú rẹ̀. Mímọ́ ni, ẹ̀yin sì gbọdọ̀ kà á sí mímọ́.
Ndũkanamaitĩrĩrie mĩĩrĩ ya arũme, na ndũkanathondeke maguta mangĩ na mũthondekere ũcio. Nĩ matheru na nĩ wega ũmatuage atĩ nĩ matheru.
33 Ẹnikẹ́ni tí ó bá po irú rẹ̀, tàbí ẹnikẹ́ni tí ó bá fi sára àlejò yàtọ̀ sí àlùfáà, a ó gé e kúrò nínú àwọn ènìyàn rẹ̀.’”
Mũndũ wothe ũrĩthondekaga maguta manungi wega mahaana ta maya, na mũndũ o wothe ũngĩmaitĩrĩria mũndũ ũtarĩ mũthĩnjĩri-Ngai, nĩakaingatwo kuuma kũrĩ andũ ao.’”
34 Olúwa sọ fún Mose pé, “Mú tùràrí olóòórùn dídùn sọ́dọ̀ rẹ, onika, àti galibanumu àti kìkì tùràrí dáradára, òsùwọ̀n kan fún gbogbo rẹ,
Ningĩ Jehova akĩĩra Musa atĩrĩ, “Oya mahuti manungi wega marĩa metagwo thitakiti, na onuka na garibane, hamwe na ũbani ũrĩa mwega mũno, mothe mathimĩtwo maiganaine,
35 ṣe tùràrí olóòórùn dídùn tí a pò, iṣẹ́ àwọn olóòórùn, tí ó ní iyọ̀, ó dára, ó sì jẹ́ mímọ́.
na ũthondekithie magĩe na mũtararĩko mwega wa ũbumba; wĩra ũcio ũrutwo nĩ mũthondeki mũũgĩ wa maguta. Makorwo mekĩrĩtwo cumbĩ, na marĩ matheru na makaamũrwo.
36 Ìwọ yóò sì lọ díẹ̀ nínú rẹ̀ kúnná, ìwọ yóò sì gbé e síwájú ẹ̀rí ní àgọ́ àjọ, níbi tí èmi yóò ti pàdé yín. Yóò sì jẹ́ mímọ́ jùlọ fún yín.
Thĩithia mahuti mamwe matuĩke mũtu, naguo ũũige mbere ya ithandũkũ rĩa Ũira thĩinĩ wa Hema-ya-Gũtũnganwo, harĩa ndĩĩcemanagia nawe. Ũgaakorwo ũrĩ mũtheru mũno harĩwe.
37 Ẹ má ṣe ṣe tùràrí kankan ní irú èyí fúnra yín; ẹ kà á ní mímọ́ sí Olúwa.
Mũtikanethondekere ũbumba wa mũthemba ũyũ nĩ ũndũ wa inyuĩ ene; ũtuagei mũtheru nĩ ũndũ wa Jehova.
38 Ẹnikẹ́ni tí ó bá ṣe irú rẹ̀ láti máa gbádùn òórùn rẹ̀, òun ni a ó gé kúrò nínú àwọn ènìyàn rẹ̀.”
Mũndũ o na ũrĩkũ ũrĩa ũgathondeka ũngĩ taguo nĩguo ekenagie na mũtararĩko waguo nĩakaingatwo kuuma kũrĩ andũ ao.”