< Exodus 30 >

1 “Ìwọ yóò sì ṣe pẹpẹ igi kasia kan; máa jó tùràrí lórí rẹ̀.
Bo-ul hlupnah hmueihtuk na saii vaengah rhining thing mah saii.
2 Kí igun mẹ́rẹ̀ẹ̀rin rẹ̀ ṣe déédé, kí ó jẹ́ ìdajì mita ní gígùn, ìdajì mita ní fífẹ̀ àti ìgbọ̀nwọ́ méjì ni gíga rẹ̀—kí ìwo rẹ̀ wà pẹ̀lú rẹ̀.
Hmueihtuk te a yun dong khat neh a daang dong khat saeh lamtah hniboeng la om saeh. Amah lamloh a ki hil a sang dong nit lo saeh.
3 Ìwọ yóò sì bo òkè rẹ̀, gbogbo ìhà rẹ̀ àti ìwo rẹ̀ pẹ̀lú u kìkì wúrà, ìwọ yóò sì ṣe wúrà gbà á yíká.
Te te a imphu khaw, a pangbueng neh a ki khaw, sui cilh neh pin ben thil. Te te a khopnah khaw sui neh pin saii.
4 Ìwọ yóò sì ṣe òrùka wúrà méjì fún pẹpẹ náà níṣàlẹ̀ ìgbátí méjèèjì ní òdìkejì ìhà rẹ̀—láti gbá àwọn òpó rẹ̀ mú, láti lè máa fi gbé e.
A vae rhoi kah a khopnah hmui ah sui kutcaeng panit saii pah. A vae rhoi kah na saii phoeiah tah te kah te hmueihtuk aka kawt ham thingpang rholhnah la om saeh.
5 Ìwọ yóò sì ṣe òpó igi kasia, ìwọ yóò sì bọ́ wọ́n pẹ̀lú wúrà.
Thingpang te rhining thing saii lamtah sui neh ben thil.
6 Ìwọ yóò gbé pẹpẹ náà sí iwájú aṣọ ìkélé, èyí tí ó wà níwájú àpótí ẹ̀rí níwájú ìtẹ́ àánú èyí tí ó wà lórí àpótí ẹ̀rí níbi ti èmi yóò ti máa bá ọ pàdé.
Hmueihtuk te olphong sokah a tlaeng hmai, olphong thingkawng taengkah hniyan hmai ah khueh. Te ah ni nang te pahoi kan tuentah eh.
7 “Aaroni yóò sì máa jó tùràrí dídùn lórí pẹpẹ náà ní àràárọ̀, nígbà tí ó tún àwọn fìtílà náà ṣe.
Te dongah te Aaron loh mincang, mincang ah bo-ul botui phum saeh. Te te a rhoekbah vaengah khaw hmaithoi te tok saeh.
8 Aaroni yóò sì tún jó tùràrí nígbà tí ó bá tan fìtílà ní àṣálẹ́, bẹ́ẹ̀ ní tùràrí yóò máa jó títí láé níwájú Olúwa fún àwọn ìran tó ń bọ̀.
Aaron loh hlaemhmah kah hmaithoi a vang vaengah khaw bo-ul te phum saeh. Te te na cadilcahma ham khaw BOEIPA mikhmuh ah saii yoeyah saeh.
9 Ẹ̀yin kò gbọdọ̀ mú àjèjì tùràrí wá sórí pẹpẹ yìí tàbí ẹbọ sísun kankan tàbí ọrẹ oúnjẹ, bẹ́ẹ̀ ni ẹ̀yin kò gbọdọ̀ da ẹbọ ohun mímu sórí i rẹ̀.
Te soah te kholong kah bo-ul neh hmueihhlutnah khaw khocang khaw khuen boeh. Te soah tuisi khaw doeng boeh.
10 Aaroni yóò sì máa ṣe ètùtù sórí àwọn ìwo rẹ̀ lẹ́ẹ̀kan lọ́dún. Òun yóò sì máa ṣe ètùtù ọdọọdún yìí pẹ̀lú ẹ̀jẹ̀ ẹbọ ètùtù fún ìran tó ń bọ̀. Mímọ́ jùlọ ni sí Olúwa.”
Aaron loh kum khat ah vai tah hmueihtuk ki dongah boirhaem thii neh dawth saeh. Kum khat ah vai tah hmueihtuk dongah na cadilcahma ham dawthnah neh dawth pah saeh. Te tah BOEIPA ham a cim kah a cim koek ni.
11 Nígbà náà ni Olúwa wí fún Mose pé,
Te phoeiah BOEIPA loh Moses te a voek tih,
12 “Nígbà tí ìwọ bá ka iye àwọn ọmọ Israẹli láti mọ iye wọn, ẹnìkọ̀ọ̀kan wọn gbọdọ̀ mú ìràpadà ọkàn rẹ̀ wá fún Olúwa ní ìgbà tí o bá ka iye wọn. Nígbà náà ni àjàkálẹ̀-ààrùn kì yóò súnmọ́ wọn, nígbà tí o bá ń ka iye wọn.
Israel ca rhoek kah hlangmi te tae lamtah amih te soep. Te vaengah hlang boeih loh a hinglu kah tlansum te BOEIPA taengah pae uh saeh. Amih te ming a soep daengah ni a soep vanbangla tlohthae loh amih soah a om pawt eh.
13 Olúkúlùkù ẹrù tí ó bá kọjá lọ sọ́dọ̀ àwọn tí a ti kà yóò san ìdajì ṣékélì, gẹ́gẹ́ bí ṣékélì ibi mímọ́, èyí tí ó wọn ogún gera. Ìdajì ṣékélì yìí ní ọrẹ fún Olúwa.
Ming soep ham aka paan boeih loh gerah pakul neh aka tluk hmuencim shekel te shekel ngancawn ah pae uh saeh. Shekel khat dong shekel rhakthuem he BOEIPA kah khosaa ni.
14 Gbogbo àwọn tí ó bá kọjá sínú àwọn tí a kà láti ẹni ogún ọdún tàbí jù bẹ́ẹ̀ lọ, ni yóò fi ọrẹ fún Olúwa.
Ming soep ham aka paan kum kul ca neh a so boeih long tah BOEIPA taengah khosaa pae saeh.
15 Àwọn olówó kì yóò san ju ìdajì ṣékélì lọ, àwọn tálákà kò sì gbọdọ̀ dín ní ìdajì ṣékélì nígbà tí ẹ̀yin bá mú ọrẹ wá fún Olúwa láti ṣe ètùtù fún ọkàn yín.
Na hinglu dawth ham BOEIPA kah khosaa na khueh te shekel pakhat kah rhakthuem lakah hlanglen long khaw pueh boel saeh lamtah tattloel long khaw hnop boel saeh.
16 Ìwọ yóò sì gba owó ètùtù náà lọ́wọ́ àwọn ọmọ Israẹli, ìwọ yóò sì fi lélẹ̀ fún ìsìn àgọ́ àjọ. Yóò jẹ́ ìrántí fún àwọn ọmọ Israẹli níwájú Olúwa, láti ṣe ètùtù fún ọkàn yín.”
Israel ca rhoek taeng lamkah dawthnah tangka na doe te tingtunnah dap ah thothuengnah ham pae. Na hinglu aka dawth ham te BOEIPA mikhmuh ah Israel ca rhoek kah poekkoepnah la om saeh,” a ti nah.
17 Nígbà náà ni Olúwa wí fún Mose pé,
Te phoeiah BOEIPA loh Moses te a voek tih,
18 “Ìwọ yóò sì ṣe agbada idẹ kan, àti ẹsẹ̀ rẹ̀ idẹ, fún wíwẹ̀. Ìwọ yóò sì gbé e sí àárín àgọ́ àjọ àti pẹpẹ náà, ìwọ yóò sì pọn omi sínú rẹ̀.
Silh vaengkah ham rhohum baeldung khaw saii lamtah a kho khaw rhohum saeh. Te te tingtunnah dap laklo neh hmueihtuk laklo ah hol lamtah tui pahoi tawn thil.
19 Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ yóò máa wẹ ọwọ́ àti ẹsẹ̀ wọn pẹ̀lú omi tí ó wà nínú rẹ̀.
Te lamlong te Aaron neh anih koca rhoek loh a kut, a kho sil uh saeh.
20 Nígbàkígbà tí wọ́n bá wọ inú àgọ́ àjọ, wọ́n yóò wẹ̀ pẹ̀lú omi nítorí kí wọ́n má ba à kú. Bákan náà, nígbà tí wọ́n bá súnmọ́ ibi pẹpẹ láti ṣe ìsìn, láti mú ẹbọ ti a fi iná sun wá fún Olúwa,
Tingtunnah dap im khuila a kun uh vaengah tui hlu uh saeh. Te daengah ni BOEIPA taengah hmaihlutnah phum ham neh thohtat ham hmueihtuk la a thoeih vaengah a duek uh pawt eh.
21 wọn yóò sì wẹ ọwọ́ wọn àti ẹsẹ̀ wọn, nítorí kí wọn máa ba à kú. Èyí ni yóò jẹ́ ìlànà títí láé fún Aaroni àti irú àwọn ọmọ rẹ̀ fún ìrandíran wọn.”
A kut a kho te a silh uh daengah ni a duek uh pawt eh. Te dongah amah ham neh a tiingan ham khaw, a cadilcahma ham khaw kumhal kah oltlueh la amih taengah om saeh,” a ti nah.
22 Olúwa sọ fún Mose pé,
BOEIPA loh Moses te a voek bal tih,
23 “Ìwọ yóò mú ààyò tùràrí olóòórùn sí ọ̀dọ̀ rẹ; ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta ṣékélì (kilogiramu mẹ́fà) tí òjìá ṣíṣàn, ìdajì bí ó bá yẹ àádọ́ta lé nígba ṣékélì tí kinamoni dídùn, àti kénì dídùn àádọ́ta lé nígba ṣékélì,
“Namah bal loh namah ham boeilu botui murrah pi ya nga, thingsa botui yahnih sawmnga ngancawn, canhnam botui yahnih sawmnga,
24 kasia ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta ṣékélì gbogbo rẹ̀ ní ìlànà ṣékélì ibi mímọ́ àti hínì òróró olifi kan (lita mẹ́rin).
valaeng khaw hmuencim kah shekel dongah ya nga neh olive situi bunang khat ah lo laeh.
25 Ṣe ìwọ̀nyí ní òróró mímọ́ ìkunra, tí a pò gẹ́gẹ́ bí olùṣe òórùn dídùn tì í ṣe. Yóò jẹ òróró mímọ́ ìtasórí.
Te phoeiah aka thungnom bibi kah yuhnah si bangla hmuencim koelhnah situi he saii lamtah hmuencim kah koelhnah situi la om saeh.
26 Ìwọ yóò sì lò ó láti ya àgọ́ sí mímọ́ àti àpótí ẹ̀rí náà,
Te nen te tingtunnah dap neh olphong thingkawng khaw,
27 tábìlì àti gbogbo ohun èlò rẹ̀, ọ̀pá fìtílà àti ohun èlò rẹ̀, àti pẹpẹ tùràrí,
caboei neh a tubael boeih khaw, hmaitung neh a tubael khaw, bo-ul hmueihtuk khaw,
28 pẹpẹ ẹbọ sísun àti gbogbo ohun èlò rẹ̀, àti agbada pẹ̀lú ẹsẹ̀ rẹ̀.
hmueihhlutnah hmueihtuk neh a hnopai boeih khaw, baeldung neh a kho te koelh pah.
29 Ìwọ yóò sì sọ wọ́n di mímọ́, nítorí kí wọn lè jẹ́ mímọ́ jùlọ, àti ohunkóhun tí ó bá fi ọwọ́ kàn wọn yóò di mímọ́.
Te rhoek te na ciim tangloeng daengah ni a cim kah a cim la a om tih te te aka ben boeih khaw a cimcaih eh.
30 “Ìwọ yóò sì ta òróró sí orí Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀, ìwọ yóò sì sọ wọ́n di mímọ́, nítorí kí wọn lè sìn mí bí àlùfáà.
Aaron neh anih koca rhoek khaw koelh lamtah kamah taengah khosoih sak ham amih te ciim laeh.
31 Ìwọ yóò sì sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé, ‘Èyí ni yóò ṣe òróró mímọ́ ìtasórí mi fún ìrandíran tó ń bọ̀.
Israel ca te khaw thui pah lamtah, “Hmuencim kah koelhnah situi he tah na cadilcahma duela kamah taengah om saeh,”ti nah.
32 Má ṣe dà á sí ara ènìyàn kí o má sì ṣe ṣe òróró kankan ni irú rẹ̀. Mímọ́ ni, ẹ̀yin sì gbọdọ̀ kà á sí mímọ́.
Hlang pum dongah yuh nah boel saeh lamtah te kah a lantang neh te bang te saii boeh. Te kah a cim te nangmih taengah khaw a cim la om saeh.
33 Ẹnikẹ́ni tí ó bá po irú rẹ̀, tàbí ẹnikẹ́ni tí ó bá fi sára àlejò yàtọ̀ sí àlùfáà, a ó gé e kúrò nínú àwọn ènìyàn rẹ̀.’”
Te bang aka thungnom tih kholong taengah te aka pae hlang te tah a pilnam lamloh hnawt saeh,” a ti nah.
34 Olúwa sọ fún Mose pé, “Mú tùràrí olóòórùn dídùn sọ́dọ̀ rẹ, onika, àti galibanumu àti kìkì tùràrí dáradára, òsùwọ̀n kan fún gbogbo rẹ,
Te phoeiah BOEIPA loh Moses te, “Namah ham botui aangpi neh khawphlawp khaw, botui tlangsungsing neh hmueihtui cil lo lamtah amah, amah om saeh.
35 ṣe tùràrí olóòórùn dídùn tí a pò, iṣẹ́ àwọn olóòórùn, tí ó ní iyọ̀, ó dára, ó sì jẹ́ mímọ́.
Te te thungnom kutci loh cilrhik la a thoek, yuhnah bo-ul cim la saii.
36 Ìwọ yóò sì lọ díẹ̀ nínú rẹ̀ kúnná, ìwọ yóò sì gbé e síwájú ẹ̀rí ní àgọ́ àjọ, níbi tí èmi yóò ti pàdé yín. Yóò sì jẹ́ mímọ́ jùlọ fún yín.
Te te a tip la neet lamtah tingtunnah dap khuikah olphong hmai ah khueh. Te ah te nang kan tuentah vetih nangmih ham hmuencim kah hmuencim koek la om ni.
37 Ẹ má ṣe ṣe tùràrí kankan ní irú èyí fúnra yín; ẹ kà á ní mímọ́ sí Olúwa.
Te bo-ul na saii vaengkah a lan a tang neh namah ham saii boeh. BOEIPA ham namah taengah a cim om.
38 Ẹnikẹ́ni tí ó bá ṣe irú rẹ̀ láti máa gbádùn òórùn rẹ̀, òun ni a ó gé kúrò nínú àwọn ènìyàn rẹ̀.”
Te te him ham te bang aka saii hlang te a pilnam lamloh hnawt saeh,” a ti nah.

< Exodus 30 >