< Exodus 30 >

1 “Ìwọ yóò sì ṣe pẹpẹ igi kasia kan; máa jó tùràrí lórí rẹ̀.
Hmuihoih to thlaek hanah, shittim thing hoiah hmaicam maeto sah ah.
2 Kí igun mẹ́rẹ̀ẹ̀rin rẹ̀ ṣe déédé, kí ó jẹ́ ìdajì mita ní gígùn, ìdajì mita ní fífẹ̀ àti ìgbọ̀nwọ́ méjì ni gíga rẹ̀—kí ìwo rẹ̀ wà pẹ̀lú rẹ̀.
To hmaicam loe takii palito om tih; dong maeto sawk ueloe, dong maeto kawk pacoengah, dong hnetto sang tih; takiinawk doeh anghmong boih tih.
3 Ìwọ yóò sì bo òkè rẹ̀, gbogbo ìhà rẹ̀ àti ìwo rẹ̀ pẹ̀lú u kìkì wúrà, ìwọ yóò sì ṣe wúrà gbà á yíká.
Hmaicam ranuih koek, ataeng hoi takiinawk to sui tui pazut ah loe, sui hoiah aqai taeng boih to sah ah.
4 Ìwọ yóò sì ṣe òrùka wúrà méjì fún pẹpẹ náà níṣàlẹ̀ ìgbátí méjèèjì ní òdìkejì ìhà rẹ̀—láti gbá àwọn òpó rẹ̀ mú, láti lè máa fi gbé e.
Sui hoi sak ih aqai tlim hae bang hoi ho bangah kangbuet luet akhaw hnetto sui hoiah sah ah; to kangbuet luet akhaw loe hmaicam aput naah thing hawthaih akhaw ah om tih.
5 Ìwọ yóò sì ṣe òpó igi kasia, ìwọ yóò sì bọ́ wọ́n pẹ̀lú wúrà.
Aputhaih thing loe shittim thing hoiah sah ah loe, sui tui pazut ah.
6 Ìwọ yóò gbé pẹpẹ náà sí iwájú aṣọ ìkélé, èyí tí ó wà níwájú àpótí ẹ̀rí níwájú ìtẹ́ àánú èyí tí ó wà lórí àpótí ẹ̀rí níbi ti èmi yóò ti máa bá ọ pàdé.
Kai mah nang kang tonghhaih ahmuen, hnukung nuiah kaom palungnathaih tangkhang, hnukung thingkhong pakaahaih kahni hmaa ah, to hmaicam to suem ah.
7 “Aaroni yóò sì máa jó tùràrí dídùn lórí pẹpẹ náà ní àràárọ̀, nígbà tí ó tún àwọn fìtílà náà ṣe.
Aaron mah akhawnbang kruek, hmaiim paang han sak naah, to hmaicam nuiah hmuihoih to thlaek tih.
8 Aaroni yóò sì tún jó tùràrí nígbà tí ó bá tan fìtílà ní àṣálẹ́, bẹ́ẹ̀ ní tùràrí yóò máa jó títí láé níwájú Olúwa fún àwọn ìran tó ń bọ̀.
Duembang hmai paang naah doeh, to hmaicam nuiah hmuihoih to thlaek tih; angzo han koi a caanawk dung khoek to Angraeng hmaa ah thlaek koi hmuihoih ah om tih.
9 Ẹ̀yin kò gbọdọ̀ mú àjèjì tùràrí wá sórí pẹpẹ yìí tàbí ẹbọ sísun kankan tàbí ọrẹ oúnjẹ, bẹ́ẹ̀ ni ẹ̀yin kò gbọdọ̀ da ẹbọ ohun mímu sórí i rẹ̀.
To hmaicam nuiah kalah hmuihoih, hmai angbawnhaih, to tih ai boeh loe cang angbawnhaih to sah hmah, naek koi hmuen doeh krai hmah.
10 Aaroni yóò sì máa ṣe ètùtù sórí àwọn ìwo rẹ̀ lẹ́ẹ̀kan lọ́dún. Òun yóò sì máa ṣe ètùtù ọdọọdún yìí pẹ̀lú ẹ̀jẹ̀ ẹbọ ètùtù fún ìran tó ń bọ̀. Mímọ́ jùlọ ni sí Olúwa.”
Aaron mah saningto naah vaito zae loihaih moi thii to sin ueloe, to hmaicam ih takiinawk nuiah zae loih hanah angbawnhaih to sah tih; na caanawk dung khoek to zae loih hanah saning kruek sah ah; hae loe Angraeng hmaa ah ciimcai koek hmaicam ah oh, tiah a naa.
11 Nígbà náà ni Olúwa wí fún Mose pé,
To pacoengah Angraeng mah Mosi khaeah,
12 “Nígbà tí ìwọ bá ka iye àwọn ọmọ Israẹli láti mọ iye wọn, ẹnìkọ̀ọ̀kan wọn gbọdọ̀ mú ìràpadà ọkàn rẹ̀ wá fún Olúwa ní ìgbà tí o bá ka iye wọn. Nígbà náà ni àjàkálẹ̀-ààrùn kì yóò súnmọ́ wọn, nígbà tí o bá ń ka iye wọn.
Israel kaminawk pakoep hanah ahmin na lak naah, kami boih hinghaih to akrang hanah Angraeng khaeah phoisa to paek oh; to tiah na sak nahaeloe nihcae na kroek naah, nihcae salakah nathaih to om mak ai.
13 Olúkúlùkù ẹrù tí ó bá kọjá lọ sọ́dọ̀ àwọn tí a ti kà yóò san ìdajì ṣékélì, gẹ́gẹ́ bí ṣékélì ibi mímọ́, èyí tí ó wọn ogún gera. Ìdajì ṣékélì yìí ní ọrẹ fún Olúwa.
Kroek tangcae ah kaom kaminawk boih loe, hmuenciim ih shekel ahap, (shekel maeto naah, gerah pumphaeto oh) paek tih; shekel ahap loe Angraeng han paek ih hmuen ah om tih.
14 Gbogbo àwọn tí ó bá kọjá sínú àwọn tí a kà láti ẹni ogún ọdún tàbí jù bẹ́ẹ̀ lọ, ni yóò fi ọrẹ fún Olúwa.
Kami kroek naah, saning pumphaeto pacoeng, ranui bang boih Angraeng khae hmuen paekhaih to sak han oh.
15 Àwọn olówó kì yóò san ju ìdajì ṣékélì lọ, àwọn tálákà kò sì gbọdọ̀ dín ní ìdajì ṣékélì nígbà tí ẹ̀yin bá mú ọrẹ wá fún Olúwa láti ṣe ètùtù fún ọkàn yín.
Na hinghaih to akrang hanah, Angraeng khaeah angbawnhaih na sak naah, angraeng kaminawk mah kapop ah paek o mak ai ueloe, kamtang kaminawk mah doeh tamsi ah paek o mak ai; kami boih mah shekel ahap paek o han oh.
16 Ìwọ yóò sì gba owó ètùtù náà lọ́wọ́ àwọn ọmọ Israẹli, ìwọ yóò sì fi lélẹ̀ fún ìsìn àgọ́ àjọ. Yóò jẹ́ ìrántí fún àwọn ọmọ Israẹli níwájú Olúwa, láti ṣe ètùtù fún ọkàn yín.”
Israel kaminawk khae hoi zae loih hanah akranghaih phoisa to la ah loe, amkhuenghaih kahni im toksak hanah patoh ah; hae loe Israel kaminawk mah Angraeng hmaa ah panoek poe hanah, na hinghaih loih thai hanah sak ih akranghaih ah om tih, tiah a naa.
17 Nígbà náà ni Olúwa wí fún Mose pé,
To pacoengah angraeng mah Mosi khaeah,
18 “Ìwọ yóò sì ṣe agbada idẹ kan, àti ẹsẹ̀ rẹ̀ idẹ, fún wíwẹ̀. Ìwọ yóò sì gbé e sí àárín àgọ́ àjọ àti pẹpẹ náà, ìwọ yóò sì pọn omi sínú rẹ̀.
amsaehhaih kathuk sabae maeto sum kamling hoiah sah ah loe, pahnuthaih a khok doeh sum kamling hoiah sah ah; to ih sabae kathuk to amkhuenghaih kahni im hoi hmaicam salakah suem ah loe, tui to lawn ah.
19 Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ yóò máa wẹ ọwọ́ àti ẹsẹ̀ wọn pẹ̀lú omi tí ó wà nínú rẹ̀.
Aaron hoi a caanawk loe to ih tui hoiah ban amsae o tih.
20 Nígbàkígbà tí wọ́n bá wọ inú àgọ́ àjọ, wọ́n yóò wẹ̀ pẹ̀lú omi nítorí kí wọ́n má ba à kú. Bákan náà, nígbà tí wọ́n bá súnmọ́ ibi pẹpẹ láti ṣe ìsìn, láti mú ẹbọ ti a fi iná sun wá fún Olúwa,
Amkhuenghaih kahni imthung ah a caeh o kruek, a duek o han ai ah, to ih tui hoiah amsae o tih; to tih ai boeh loe Angraeng khaeah hmai angbawnhaih sak hanah hmaicam hmaa ah caeh o naah,
21 wọn yóò sì wẹ ọwọ́ wọn àti ẹsẹ̀ wọn, nítorí kí wọn máa ba à kú. Èyí ni yóò jẹ́ ìlànà títí láé fún Aaroni àti irú àwọn ọmọ rẹ̀ fún ìrandíran wọn.”
a duek o han ai ah, nihcae mah khok hoi ban to amsae o tih; hae loe Aaron hoi angzo han koi a caanawk mah sak o poe han ih atawk ah oh.
22 Olúwa sọ fún Mose pé,
To pacoengah Angraeng mah Mosi khaeah,
23 “Ìwọ yóò mú ààyò tùràrí olóòórùn sí ọ̀dọ̀ rẹ; ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta ṣékélì (kilogiramu mẹ́fà) tí òjìá ṣíṣàn, ìdajì bí ó bá yẹ àádọ́ta lé nígba ṣékélì tí kinamoni dídùn, àti kénì dídùn àádọ́ta lé nígba ṣékélì,
kahoih koek hmuihoih to la ah, kaciim myrrh hmuihoih shekel cumvai pangato, cinnamon hmuihoih ahap shekel cumvai hnet, qui pangato,
24 kasia ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta ṣékélì gbogbo rẹ̀ ní ìlànà ṣékélì ibi mímọ́ àti hínì òróró olifi kan (lita mẹ́rin).
hmuenciim ih shekel baktih toengah, kasia shekel cumvai pangato, olive situi hint maeto sin ah;
25 Ṣe ìwọ̀nyí ní òróró mímọ́ ìkunra, tí a pò gẹ́gẹ́ bí olùṣe òórùn dídùn tì í ṣe. Yóò jẹ òróró mímọ́ ìtasórí.
hmuihoih sah kop kami mah sak ih hmuihoih to kaciim angnok ih kaciim situi ah sah ah, to situi loe angnok ih kaciim situi ah om tih.
26 Ìwọ yóò sì lò ó láti ya àgọ́ sí mímọ́ àti àpótí ẹ̀rí náà,
To situi hoiah amkhuenghaih kahni im hoi hnukung thingkhong,
27 tábìlì àti gbogbo ohun èlò rẹ̀, ọ̀pá fìtílà àti ohun èlò rẹ̀, àti pẹpẹ tùràrí,
caboi hoi laom sabaenawk boih, hmaithawk hoi hmaithawk paanghaih tungnawk, hmuihoih thlaekhaih hmaicam,
28 pẹpẹ ẹbọ sísun àti gbogbo ohun èlò rẹ̀, àti agbada pẹ̀lú ẹsẹ̀ rẹ̀.
hmai angbawnhaih hmaicam hoi laom sabaenawk boih, sabae kathuk hoi pahnuthaih a khoknawk to nok boih ah.
29 Ìwọ yóò sì sọ wọ́n di mímọ́, nítorí kí wọn lè jẹ́ mímọ́ jùlọ, àti ohunkóhun tí ó bá fi ọwọ́ kàn wọn yóò di mímọ́.
To hmuennawk kaciim koek ah oh hanah, to tiah ciimsak ah; to hmuen kasui hmuen boih loe ciimcai tih.
30 “Ìwọ yóò sì ta òróró sí orí Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀, ìwọ yóò sì sọ wọ́n di mímọ́, nítorí kí wọn lè sìn mí bí àlùfáà.
Aaron hoi a capanawk to bawh ah loe, kai ih qaima tok a sak o thai hanah, nihcae to pahoe ah.
31 Ìwọ yóò sì sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé, ‘Èyí ni yóò ṣe òróró mímọ́ ìtasórí mi fún ìrandíran tó ń bọ̀.
Israel kaminawk khaeah, Hae loe angzo han koi na caanawk dung khoek to angnok ih kaciim situi ah om tih.
32 Má ṣe dà á sí ara ènìyàn kí o má sì ṣe ṣe òróró kankan ni irú rẹ̀. Mímọ́ ni, ẹ̀yin sì gbọdọ̀ kà á sí mímọ́.
To situi hoiah takpum to bawh hmah loe, to situi hoi kanghmong kalah situi to sah hmah; to situi loe ciimcai pongah, nang hanah kaciim situi ah om tih.
33 Ẹnikẹ́ni tí ó bá po irú rẹ̀, tàbí ẹnikẹ́ni tí ó bá fi sára àlejò yàtọ̀ sí àlùfáà, a ó gé e kúrò nínú àwọn ènìyàn rẹ̀.’”
To situi hoi kanghmong kalah situi sah kami, asaenghaih om ai ah to situi hoi minawk kalah nok kami loe, acaeng thung hoi pahnawt ah, tiah a thuih, tiah thui paeh, tiah a naa.
34 Olúwa sọ fún Mose pé, “Mú tùràrí olóòórùn dídùn sọ́dọ̀ rẹ, onika, àti galibanumu àti kìkì tùràrí dáradára, òsùwọ̀n kan fún gbogbo rẹ,
To pacoengah Angraeng mah Mosi khaeah, Hmuihoih, thing tangpri, hmuihoih onika, hmuihoih kalbanumnawk to la ah loe, to hmuihoih hoi kaciim hmuihoihnawk to kangvan ah noek ah;
35 ṣe tùràrí olóòórùn dídùn tí a pò, iṣẹ́ àwọn olóòórùn, tí ó ní iyọ̀, ó dára, ó sì jẹ́ mímọ́.
to hmuihoih hmuennawk hoiah hmai thlaek koi hmuihoih loe hmuihoih sah kop kami khaeah sahsak ah; paloi thuh ah, to pacoengah loe kathoeng hoi ciimcai hmuihoih ah om tih.
36 Ìwọ yóò sì lọ díẹ̀ nínú rẹ̀ kúnná, ìwọ yóò sì gbé e síwájú ẹ̀rí ní àgọ́ àjọ, níbi tí èmi yóò ti pàdé yín. Yóò sì jẹ́ mímọ́ jùlọ fún yín.
Thoemtonawk to kadip puengah naep ah loe, nang kang hnukhaih, amkhuenghaih kahni im ih hnukung hmaa ah suem ah; hae loe nang hanah ciimcai koek ah om tih.
37 Ẹ má ṣe ṣe tùràrí kankan ní irú èyí fúnra yín; ẹ kà á ní mímọ́ sí Olúwa.
To tiah sak ih hmuihoih hoi kanghmong ah, nangmah han kalah hmuihoih to sah hmah; to loe Angraeng hanah nangcae khaeah ciimcai hmuen ah oh han oh.
38 Ẹnikẹ́ni tí ó bá ṣe irú rẹ̀ láti máa gbádùn òórùn rẹ̀, òun ni a ó gé kúrò nínú àwọn ènìyàn rẹ̀.”
Mi kawbaktih doeh hae baktih hmai thlaek koi hmuihoih to angmah hanah sah moe, patoh kami loe, acaeng thung hoiah pahnawt ah, tiah a naa.

< Exodus 30 >