< Exodus 3 >

1 Ní ọjọ́ kan nígbà tí Mose ń ṣọ́ agbo ẹran Jetro baba ìyàwó rẹ̀, àlùfáà Midiani. Ó da agbo ẹran náà lọ sí ọ̀nà jíjìn nínú aginjù. Ó dé Horebu, òkè Ọlọ́run.
Mısee cune abbatteyn, Midyanaaşine kaahinın syuru uxhiyxhana'a eyxhe. Mang'une abbatteyn düğəlıd İtron eyhe. Sayəqees mang'vee man syuru əq'ənane sahreeqa, Allahne suvaysqa Xorevisqa ıkekka.
2 Níbẹ̀ ni angẹli Olúwa ti yọ sí i nínú ọ̀wọ́-iná tí ń jó láàrín igbó. Mose rí i pé iná ń jó nínú igbó ṣùgbọ́n igbó kò run.
Sayir mang'us gyotxhanne ğıç'eençe Rəbbina malaaik gyagva. Mısayk'le ts'ayın aqqıyn ğı'ç'iy gidyotxhan g'acumee,
3 Nígbà náà ni Mose sọ pé, “Èmi yóò lọ wo ohun ìyanu yìí, ìdí tí iná kò fi jó igbó run.”
mang'vee culed alqa eyhen: – Hinnalan hark'ın mane curayne işiqa ilyakkas, nya'asiy man ğı'ç'iy gyotxhun ç'əvcad dexhe.
4 Nígbà tí Olúwa rí i pe Mose ti lọ láti lọ wò ó, Ọlọ́run ké pè é láti àárín igbó náà, “Mose! Mose!” Mose sì dáhùn ó wí pé, “Èmi nìyìí.”
Rəbbık'le Mısa ilyakasva k'ane qıxha g'acumee, ğıç'eençe mang'ulqa ona'an: – Mısa, Mısa! Mang'veeyir «Hooyva» alidghıniy qele.
5 Olúwa sì wí fún Mose pé, “Má ṣe súnmọ́ ìhín yìí, bọ́ sálúbàtà rẹ kúrò ní ẹsẹ̀ rẹ, nítorí ibi tí ìwọ dúró sí i nì ilẹ̀ mímọ́ ni.”
Allahee eyhen: – K'anyaqa qımexhe. G'ellinbı g'ayşe. Ğu ulyorzulin ciga er ciga vod.
6 Nígbà náà ní ó wí pé, “Èmi ni Ọlọ́run baba rẹ, Ọlọ́run Abrahamu, Ọlọ́run Isaaki àti Ọlọ́run Jakọbu.” Nítorí ìdí èyí, Mose sì pa ojú rẹ̀ mọ́, nítorí ó bẹ̀rù láti bojú wo Ọlọ́run.
Zı, yiğne dekkeyid, İbrahimeeyid, I'saq'eeyid, Yaaq'ubeeyid ı'bəədat hı'ına Allah vor. Man g'ayxhı Mısee aq'va aqqaqqa, Allahıqa ilyakkas qəyq'ənna.
7 Olúwa si wí pé, “Èmí ti rí ìpọ́njú àwọn ènìyàn mi ní ilẹ̀ Ejibiti, mo sì ti gbọ́ ohùn igbe wọn nítorí àwọn akóniṣiṣẹ́ wọn. Ìyà tí ń jẹ wọ́n sì kan mi lára.
Rəbbee eyhen: – Zak'le Yizde milletın Misir opxhanna əq'üba vaats'ana. Manbışil ooqa givxhiyne insanaaşine xıleke höödəxənıd Zak'le ats'an, manbışe kumag heqqad Zak'le g'ayxhin.
8 Èmi sì ti sọ̀kalẹ̀ wá láti gbà wọ́n lọ́wọ́ àwọn ará Ejibiti, àti láti mú wọn gòkè kúrò ní ilẹ̀ náà lọ sí ilẹ̀ tí ó dára tí ó sì ní ààyè, àní ilẹ̀ tí ó ń sàn fún wàrà àti oyin; ibùgbé àwọn ará Kenaani, ará Hiti, Amori, Peresi, Hifi àti Jebusi.
Zı mançil-alla inyaqa arı. Həşde Zı manbı Misirbışde xılençe g'attivxhan hav'u mane ölkeençe qığaa'asınbı. Qiyğaleb sa xənne, kar geednane, nyakiy itv gyodatstsene cigabışeeqa quvkees. Maa'ab həşde Kana'anbı, Q'etbı, Emorbı, Perizbı, Q'ivbı, Yevusbı aaxva.
9 Ǹjẹ́ nísinsin yìí, wò ó, igbe àwọn ará Israẹli ti dé ọ̀dọ̀ mi, Èmi sì ti rí bí àwọn ará Ejibiti ti ṣe ń gbà ń jẹ wọ́n ní ìyà.
İzrailybışin gyaaşuy Zak'le g'iyxhen. Zak'le Misirbışe manbışis hoolena əq'üba g'oocena.
10 Ǹjẹ́ nísinsin yìí, lọ, èmi yóò rán ọ sí Farao láti kó àwọn ènìyàn Israẹli jáde kúrò ní ilẹ̀ Ejibiti.”
Mançil-allar Zı ğu fironusqa Yizın millet İzrailybı, Misirğançe qığe'eva g'ıxele.
11 Ṣùgbọ́n Mose wí fún Ọlọ́run pé, “Ta ni èmi, tí èmi yóò tọ Farao lọ, ti èmi yóò sì kó àwọn ará Israẹli jáde kúrò ni ilẹ̀ Ejibiti?”
Mısee Allahık'le eyhen: – Nya'a, zı vuşune vor, fironusqa hark'ın İzrailybı Misirğançe qığaa'as?
12 Nígbà náà ni Ọlọ́run wí fún Mose pé, “Èmi yóò wà pẹ̀lú rẹ. Èyí ni yóò jẹ́ àmì fún ọ, tí yóò fihàn pé, èmi ni ó rán ọ lọ, nígbà tí ìwọ bá kó àwọn ènìyàn náà jáde kúrò ní ilẹ̀ Ejibiti, ẹ̀yin yóò sin Ọlọ́run ni orí òkè yìí.”
Allahee eyhen: – Zı vaka ixhes. Zı ğu g'axuvuva inçike ats'axhxhes: ğu millet Misirğançe qığavhuyng'a ine suval şu Zas ı'bəədat ha'as.
13 Mose sì wí fún Ọlọ́run pé, “Bí mo bá tọ àwọn ará Israẹli lọ tí mo sì sọ fún wọn pé, ‘Ọlọ́run àwọn baba yín ni ó rán mi sí i yín,’ tí wọ́n sì béèrè lọ́wọ́ mi pé, ‘Kí ni orúkọ rẹ̀?’ Kí ni èmi yóò sọ fún wọn ní ìgbà náà?”
Mısee Allahık'le eyhen: – Zı İzrailybışisqa hark'ın uvheene «Vuşde dekkaaşe ı'bəədat hı'ıne Allahee zı şosqa g'axuvu», manbışe qiyghanasın: «Mang'un do hucooyiy?» Hucoovane zı manbışis alidghıniy qeles?
14 Ọlọ́run sì sọ fún Mose pé, “èmi ni ti ń jẹ́ èmi ni. Èyí ni ìwọ yóò sọ fún àwọn ará Israẹli: ‘èmi ni ni ó rán mi sí i yín.’”
Allahee mang'us inəxüd cuvab qele: – Zı Vuşuyiy, Manar vorna. İzrailybışik'le eyhe: «Zı Vorna» eyheng'vee vuşde k'anyaqa g'axuvu.
15 Ọlọ́run sì wí fún Mose pẹ̀lú pé, “Báyìí ni kí ìwọ sọ fún àwọn ọmọ Israẹli, ‘Olúwa Ọlọ́run àwọn baba yín; Ọlọ́run Abrahamu, Ọlọ́run Isaaki àti Ọlọ́run Jakọbu; ni ó rán mi sí i yín.’ “Èyí ni orúkọ mi títí ayérayé, orúkọ ti ẹ ó fi máa rántí mi láti ìran dé ìran.
Allahee Mısayk'le meed eyhen: – İzrailybışik'le eyhe: «YAHVE (Rəbb), vuşde dekkaaşee, İbrahimee, I'saq'ee, Yaaq'ubee ı'bəədat hı'ıne Allahee zı şosqa g'axuvu». Yizın gırgıne gahbışil do YAHVE ixhes. Nasılbı nimee badaletxheyid Zalqa məxüd ona'as.
16 “Lọ, kó àwọn àgbàgbà Israẹli jọ, kí o sì wí fún wọn pé, ‘Olúwa Ọlọ́run àwọn baba yín, Ọlọ́run Abrahamu, ti Isaaki, àti ti Jakọbu; ni ó farahàn mi, ó sì wí pé, lóòótọ́ èmi ti ń bojú wò yín, èmi sì ti rí ohun tí wọ́n ṣe sí i yín ni ilẹ̀ Ejibiti.
Hak'ne İzrailin ağsaqqalar sav'u manbışik'le eyhe: «Rəbbee, vuşde dekkaaşee, İbrahimee, I'saq'ee, Yaaq'ubee ı'bəədat hı'ına Allah zas dyagu uvhuyn: «Zı şoqa ilyakkaniy vor, Zak'le g'avcuna şu Misir opxhanna əq'üba.
17 Èmi sì ti ṣe ìlérí láti mú un yín jáde kúrò nínú ìpọ́njú yín ni ilẹ̀ Ejibiti wá sí ilẹ̀ Kenaani, ará Hiti, Amori, Peresi, Hifi àti Jebusi; ilẹ̀ tí ó ń sàn fún wàrà àti oyin.’
Zı şos cuvab hele, şu Misireene əq'übayke g'attivxhan hav'u Kana'anbışde, Q'etbışde, Emorbışde, Perizbışde, Q'ivbışde, Yevusbışde nyakiy itv gyodatstsene cigabışeeqa quvkees“».
18 “Àwọn àgbàgbà Israẹli yóò fetísílẹ̀ sí ohùn rẹ. Nígbà náà ni ìwọ, àti àwọn àgbàgbà yóò jọ tọ ọba Ejibiti lọ, ẹ ó sì wí fún un pé, ‘Olúwa, Ọlọ́run àwọn ará Heberu ti pàdé wa. Jẹ́ kí a lọ ni ìrìn ọjọ́ mẹ́ta sí inú aginjù láti lọ rú ẹbọ sí Olúwa Ọlọ́run.’
İzrailyne ağsaqqalaaşe val k'ırı alixhxhesın. Ğunar manbışika sacigee Misirne paççahısqa hark'ın eyhe: «Cühüt'yaaşina Allah, Rəbb şas dyagu. Şi xhebılle yiğna yəq apk'ın sahree yişde Allahıs, Rəbbis q'urbanbı allya'as».
19 Ṣùgbọ́n èmi mọ̀ pé ọba Ejibiti kò ní jẹ́ kí ẹ lọ bí kò ṣe pé ọwọ́ ńlá Ọlọ́run wà ni ara rẹ̀.
Zak'le ats'an Misirna paççah gucuka ilydekkee mang'vee şu g'avkvas deş.
20 Nítorí náà, èmi yóò na ọwọ́ mí láti lu àwọn ará Ejibiti pẹ̀lú gbogbo ohun ìyanu tí èmi yóò ṣe ni àárín wọn. Lẹ́yìn náà, òun yóò jẹ́ kí ẹ máa lọ.
Mançil-allab Zı Misirılqa xıl alivka'as, həşdilqamee g'idiyxhiyn yiğbı manbışilqa allya'as. Mançile qiyğa mang'vee şu g'avkasınbı.
21 “Èmi yóò sì jẹ́ kí ẹ bá ojúrere àwọn ará Ejibiti pàdé. Tí yóò fi jẹ́ pé ti ẹ̀yin bá ń lọ, ẹ kò ní lọ ní ọwọ́ òfo.
Zı məxüd ha'as şu manbışde ulen avqecen, şu q'ərane xıleka əlyhəəs gimabak'acen.
22 Gbogbo àwọn obìnrin ni ó ní láti béèrè lọ́wọ́ àwọn aládùúgbò wọn àti gbogbo àwọn obìnrin ti ń gbé nínú ilé rẹ fún ohun fàdákà àti wúrà àti fún aṣọ, èyí ti ẹ̀yin yóò wọ̀ sí ọrùn àwọn ọmọ yín ọkùnrin àti obìnrin. Báyìí ni ẹ̀yin yóò sì kó ẹrù àwọn ará Ejibiti.”
Çühüt'yaaşine yedaaşe misirbışde yedaaşike, hasre k'ınəəğəykeyiy nuk'rayke hı'iyn karbıyiy tanalinbı heqqecen. Man karbı şu vuşde dixbışilqayiy yişbışilqa qa'as. Şu məxüb Misirbı q'əra qaa'as.

< Exodus 3 >