< Exodus 3 >

1 Ní ọjọ́ kan nígbà tí Mose ń ṣọ́ agbo ẹran Jetro baba ìyàwó rẹ̀, àlùfáà Midiani. Ó da agbo ẹran náà lọ sí ọ̀nà jíjìn nínú aginjù. Ó dé Horebu, òkè Ọlọ́run.
Kwathi uMosi eselusa izimvu zikayisezala uJethro, umphristi waseMidiyani, waseqhuba izimvu zaya kude ohlangothini lwenkangala wasefika eHorebhi, intaba kaNkulunkulu.
2 Níbẹ̀ ni angẹli Olúwa ti yọ sí i nínú ọ̀wọ́-iná tí ń jó láàrín igbó. Mose rí i pé iná ń jó nínú igbó ṣùgbọ́n igbó kò run.
Lapho-ke ingilosi kaThixo yabonakala kuye iphakathi kwamalangabi omlilo esixukwini. UMosi wabona ukuthi loba isixuku sasibhebha kasizange sitshe.
3 Nígbà náà ni Mose sọ pé, “Èmi yóò lọ wo ohun ìyanu yìí, ìdí tí iná kò fi jó igbó run.”
Ngakho uMosi wacabanga esithi, “Ngizasondela ngiyebona isimanga lesi ukuba kungani isixuku singatshi silothe.”
4 Nígbà tí Olúwa rí i pe Mose ti lọ láti lọ wò ó, Ọlọ́run ké pè é láti àárín igbó náà, “Mose! Mose!” Mose sì dáhùn ó wí pé, “Èmi nìyìí.”
Kwathi uThixo ebona ukuthi usesondele ukuba ayekhangela, uNkulunkulu wasememeza ngelizwi elaliphuma kulesosixuku wathi, “Mosi! Mosi!” UMosi wathi, “Ngilapha.”
5 Olúwa sì wí fún Mose pé, “Má ṣe súnmọ́ ìhín yìí, bọ́ sálúbàtà rẹ kúrò ní ẹsẹ̀ rẹ, nítorí ibi tí ìwọ dúró sí i nì ilẹ̀ mímọ́ ni.”
UNkulunkulu wathi, “Ungasondeli. Khupha amanyathela akho, ngoba indawo omi kuyo ingumhlabathi ongcwele.”
6 Nígbà náà ní ó wí pé, “Èmi ni Ọlọ́run baba rẹ, Ọlọ́run Abrahamu, Ọlọ́run Isaaki àti Ọlọ́run Jakọbu.” Nítorí ìdí èyí, Mose sì pa ojú rẹ̀ mọ́, nítorí ó bẹ̀rù láti bojú wo Ọlọ́run.
Wasesithi njalo, “NginguNkulunkulu kayihlo, uNkulunkulu ka-Abhrahama, uNkulunkulu ka-Isaka loNkulunkulu kaJakhobe.” Ngalokhu, uMosi wafihla ubuso bakhe ngoba wayesesaba ukukhangela uNkulunkulu.
7 Olúwa si wí pé, “Èmí ti rí ìpọ́njú àwọn ènìyàn mi ní ilẹ̀ Ejibiti, mo sì ti gbọ́ ohùn igbe wọn nítorí àwọn akóniṣiṣẹ́ wọn. Ìyà tí ń jẹ wọ́n sì kan mi lára.
UThixo wasesithi, “Impela ngilubonile usizi lwabantu bami eGibhithe. Ngibazwile bekhala ngenxa yezinduna zezigqili ezibancindezelayo, njalo ngiyakhathazeka ngokuhlupheka kwabo.
8 Èmi sì ti sọ̀kalẹ̀ wá láti gbà wọ́n lọ́wọ́ àwọn ará Ejibiti, àti láti mú wọn gòkè kúrò ní ilẹ̀ náà lọ sí ilẹ̀ tí ó dára tí ó sì ní ààyè, àní ilẹ̀ tí ó ń sàn fún wàrà àti oyin; ibùgbé àwọn ará Kenaani, ará Hiti, Amori, Peresi, Hifi àti Jebusi.
Ngakho ngehlile ukuzabakhulula ezandleni zamaGibhithe ngibakhuphe kulelolizwe ngibase elizweni elilendawo enengi, ilizwe eligeleza uchago loluju, endaweni yamaKhenani, amaHithi, ama-Amori, amaPherizi, amaHivi lamaJebusi.
9 Ǹjẹ́ nísinsin yìí, wò ó, igbe àwọn ará Israẹli ti dé ọ̀dọ̀ mi, Èmi sì ti rí bí àwọn ará Ejibiti ti ṣe ń gbà ń jẹ wọ́n ní ìyà.
Ukukhala kwabako-Israyeli sekufikile kimi, njalo sengibonile lendlela amaGibhithe ababahlukuluza ngayo.
10 Ǹjẹ́ nísinsin yìí, lọ, èmi yóò rán ọ sí Farao láti kó àwọn ènìyàn Israẹli jáde kúrò ní ilẹ̀ Ejibiti.”
Ngakho suka uhambe. Ngikuthuma kuFaro ukuthi uyekhupha abantu bami abako-Israyeli elizweni laseGibhithe.”
11 Ṣùgbọ́n Mose wí fún Ọlọ́run pé, “Ta ni èmi, tí èmi yóò tọ Farao lọ, ti èmi yóò sì kó àwọn ará Israẹli jáde kúrò ni ilẹ̀ Ejibiti?”
Kodwa uMosi wathi kuNkulunkulu, “Kambe ngingubani ukuba ngiye kuFaro ukuyakhupha abako-Israyeli elizweni laseGibhithe na?”
12 Nígbà náà ni Ọlọ́run wí fún Mose pé, “Èmi yóò wà pẹ̀lú rẹ. Èyí ni yóò jẹ́ àmì fún ọ, tí yóò fihàn pé, èmi ni ó rán ọ lọ, nígbà tí ìwọ bá kó àwọn ènìyàn náà jáde kúrò ní ilẹ̀ Ejibiti, ẹ̀yin yóò sin Ọlọ́run ni orí òkè yìí.”
UNkulunkulu wasesithi, “Ngizakuba lawe. Lesi sizakuba yisibonakaliso sokuthi yimi engikuthumileyo: Nxa usubakhuphile abantu eGibhithe, lizakhonza uNkulunkulu kuyonale intaba.”
13 Mose sì wí fún Ọlọ́run pé, “Bí mo bá tọ àwọn ará Israẹli lọ tí mo sì sọ fún wọn pé, ‘Ọlọ́run àwọn baba yín ni ó rán mi sí i yín,’ tí wọ́n sì béèrè lọ́wọ́ mi pé, ‘Kí ni orúkọ rẹ̀?’ Kí ni èmi yóò sọ fún wọn ní ìgbà náà?”
UMosi wathi kuNkulunkulu, “Aluba ngifika kwabako-Israyeli ngithi kubo, ‘UNkulunkulu waboyihlo ungithumile kini,’ besebengibuza bathi, ‘Ungubani ibizo lakhe?’ Ngizakuthini kubo?”
14 Ọlọ́run sì sọ fún Mose pé, “èmi ni ti ń jẹ́ èmi ni. Èyí ni ìwọ yóò sọ fún àwọn ará Israẹli: ‘èmi ni ni ó rán mi sí i yín.’”
UNkulunkulu wathi kuMosi, “Nginguye Onguye. Lokhu yikho ozakutsho kwabako-Israyeli ukuthi, ‘Unguye ungithumile kini.’”
15 Ọlọ́run sì wí fún Mose pẹ̀lú pé, “Báyìí ni kí ìwọ sọ fún àwọn ọmọ Israẹli, ‘Olúwa Ọlọ́run àwọn baba yín; Ọlọ́run Abrahamu, Ọlọ́run Isaaki àti Ọlọ́run Jakọbu; ni ó rán mi sí i yín.’ “Èyí ni orúkọ mi títí ayérayé, orúkọ ti ẹ ó fi máa rántí mi láti ìran dé ìran.
UNkulunkulu wabuye wathi kuMosi, “Tshono kwabako-Israyeli uthi, ‘uThixo, uNkulunkulu waboyihlo, uNkulunkulu ka-Abhrahama, uNkulunkulu ka-Isaka, loNkulunkulu kaJakhobe ungithumile kini.’ Leli libizo lami laphakade, ibizo engizakhunjulwa ngalo kusukela kusizukulwane kusiya kwesinye isizukulwane.
16 “Lọ, kó àwọn àgbàgbà Israẹli jọ, kí o sì wí fún wọn pé, ‘Olúwa Ọlọ́run àwọn baba yín, Ọlọ́run Abrahamu, ti Isaaki, àti ti Jakọbu; ni ó farahàn mi, ó sì wí pé, lóòótọ́ èmi ti ń bojú wò yín, èmi sì ti rí ohun tí wọ́n ṣe sí i yín ni ilẹ̀ Ejibiti.
Hamba uyebuthanisa abadala bako-Israyeli uthi kubo, ‘uThixo, uNkulunkulu waboyihlo, uNkulunkulu ka-Abhrahama, ka-Isaka loJakhobe, ubonakele kimi wathi: Bengilikhangele njalo ngikubonile okwenziwe kini eGibhithe.
17 Èmi sì ti ṣe ìlérí láti mú un yín jáde kúrò nínú ìpọ́njú yín ni ilẹ̀ Ejibiti wá sí ilẹ̀ Kenaani, ará Hiti, Amori, Peresi, Hifi àti Jebusi; ilẹ̀ tí ó ń sàn fún wàrà àti oyin.’
Futhi ngithembisile ukulikhupha osizini lwenu elikulo eGibhithe ngilise elizweni lamaKhenani, amaHithi, ama-Amori, amaPherizi, amaHivi lamaJebusi, ilizwe eligeleza uchago loluju.’
18 “Àwọn àgbàgbà Israẹli yóò fetísílẹ̀ sí ohùn rẹ. Nígbà náà ni ìwọ, àti àwọn àgbàgbà yóò jọ tọ ọba Ejibiti lọ, ẹ ó sì wí fún un pé, ‘Olúwa, Ọlọ́run àwọn ará Heberu ti pàdé wa. Jẹ́ kí a lọ ni ìrìn ọjọ́ mẹ́ta sí inú aginjù láti lọ rú ẹbọ sí Olúwa Ọlọ́run.’
Abadala bako-Israyeli bazakulalela. Kuzakuthi wena kanye labadala liye enkosini yaseGibhithe lithi kuyo, ‘uThixo, uNkulunkulu wamaHebheru uhlangane lathi. Sivumele sithathe uhambo lwezinsuku ezintathu siye enkangala ukuyanikela imihlatshelo kuThixo uNkulunkulu wethu.’
19 Ṣùgbọ́n èmi mọ̀ pé ọba Ejibiti kò ní jẹ́ kí ẹ lọ bí kò ṣe pé ọwọ́ ńlá Ọlọ́run wà ni ara rẹ̀.
Kodwa ngiyakwazi ukuthi inkosi yaseGibhithe ayiyikulivumela ukuthi lihambe ngaphandle kokuba incindezelwe yisandla esilamandla.
20 Nítorí náà, èmi yóò na ọwọ́ mí láti lu àwọn ará Ejibiti pẹ̀lú gbogbo ohun ìyanu tí èmi yóò ṣe ni àárín wọn. Lẹ́yìn náà, òun yóò jẹ́ kí ẹ máa lọ.
Ngakho ngizakwelula isandla sami ngiwatshaye amaGibhithe ngazozonke izimanga engizazenza phakathi kwawo. Ngemva kwalokho, izalivumela lihambe.
21 “Èmi yóò sì jẹ́ kí ẹ bá ojúrere àwọn ará Ejibiti pàdé. Tí yóò fi jẹ́ pé ti ẹ̀yin bá ń lọ, ẹ kò ní lọ ní ọwọ́ òfo.
Njalo ngizakwenza amaGibhithe abe lomusa kulababantu, ukuze kuthi mhla lisuka lingahambi lingaphethe lutho.
22 Gbogbo àwọn obìnrin ni ó ní láti béèrè lọ́wọ́ àwọn aládùúgbò wọn àti gbogbo àwọn obìnrin ti ń gbé nínú ilé rẹ fún ohun fàdákà àti wúrà àti fún aṣọ, èyí ti ẹ̀yin yóò wọ̀ sí ọrùn àwọn ọmọ yín ọkùnrin àti obìnrin. Báyìí ni ẹ̀yin yóò sì kó ẹrù àwọn ará Ejibiti.”
Wonke owesifazane kacele kumakhelwane wakhe lakuye wonke owesifazane ohlala endlini yakhe izinto eziligugu ezenziwe ngesiliva legolide kanye lezigqoko ezizagqokwa ngamadodana lamadodakazi enu. Ngaleyondlela lizawemuka impahla amaGibhithe.”

< Exodus 3 >