< Exodus 3 >
1 Ní ọjọ́ kan nígbà tí Mose ń ṣọ́ agbo ẹran Jetro baba ìyàwó rẹ̀, àlùfáà Midiani. Ó da agbo ẹran náà lọ sí ọ̀nà jíjìn nínú aginjù. Ó dé Horebu, òkè Ọlọ́run.
Eso afaega, Mousese da Yedelou (Midia: ne gobele salasu dunu) amo ea sibi amola goudi ouligisa esalu. E da amo lai gebo gilisisu wadela: i hafoga: i soge amoga oule asili, hadigi goumi amo Sainai, amoga doaga: i.
2 Níbẹ̀ ni angẹli Olúwa ti yọ sí i nínú ọ̀wọ́-iná tí ń jó láàrín igbó. Mose rí i pé iná ń jó nínú igbó ṣùgbọ́n igbó kò run.
Amogai, Hina Gode Ea a: igele dunu da lalu gona: su agoane hamoi, ifa fonobahadi ganodini dialebe ba: i. Mousese da amo ifa laluga nenanu be hame nei dagoi ba: i.
3 Nígbà náà ni Mose sọ pé, “Èmi yóò lọ wo ohun ìyanu yìí, ìdí tí iná kò fi jó igbó run.”
E da fofogadigili amane dawa: i “Amo ifa laluga nenanebe abuliba: le nei dagoi hame ba: sala: ? Na da gadenene ba: la masunu.”
4 Nígbà tí Olúwa rí i pe Mose ti lọ láti lọ wò ó, Ọlọ́run ké pè é láti àárín igbó náà, “Mose! Mose!” Mose sì dáhùn ó wí pé, “Èmi nìyìí.”
Hina Gode da Mousese gadenene manebe ba: loba, E da ifa fonobahadi amo ganodini lelu, amoga amane sia: i, “Mousese! Mousese!” Mousese da bu adole i, “Na da wea!”
5 Olúwa sì wí fún Mose pé, “Má ṣe súnmọ́ ìhín yìí, bọ́ sálúbàtà rẹ kúrò ní ẹsẹ̀ rẹ, nítorí ibi tí ìwọ dúró sí i nì ilẹ̀ mímọ́ ni.”
Gode amane sia: i “Bu gadenene mae misa. Dia emo salasu fadegama. Bai di da hadigi osobo amo da: iya lela.
6 Nígbà náà ní ó wí pé, “Èmi ni Ọlọ́run baba rẹ, Ọlọ́run Abrahamu, Ọlọ́run Isaaki àti Ọlọ́run Jakọbu.” Nítorí ìdí èyí, Mose sì pa ojú rẹ̀ mọ́, nítorí ó bẹ̀rù láti bojú wo Ọlọ́run.
Na da dia aowalali amo A: ibalaha: me, Aisage amola Ya: igobe ilia Gode esala.” Amaiba: le, Mousese da Gode Ea odagi ba: mu bagade beda: iba: le, ea odagi dedeboi.
7 Olúwa si wí pé, “Èmí ti rí ìpọ́njú àwọn ènìyàn mi ní ilẹ̀ Ejibiti, mo sì ti gbọ́ ohùn igbe wọn nítorí àwọn akóniṣiṣẹ́ wọn. Ìyà tí ń jẹ wọ́n sì kan mi lára.
Amalalu, Hina Gode da amane sia: i, “Idibidi dunu da mae asigili Na fi dunuma gasa fi hamonana, amo Na da ba: i dagoi. Ilia da ilia hame asigi udigili hawa: hamosu ouligisu dunu iliba: le gaga: ma: ne Nama wesu, Na da nabi dagoi. Na da ilia se nabasu huluane dawa:
8 Èmi sì ti sọ̀kalẹ̀ wá láti gbà wọ́n lọ́wọ́ àwọn ará Ejibiti, àti láti mú wọn gòkè kúrò ní ilẹ̀ náà lọ sí ilẹ̀ tí ó dára tí ó sì ní ààyè, àní ilẹ̀ tí ó ń sàn fún wàrà àti oyin; ibùgbé àwọn ará Kenaani, ará Hiti, Amori, Peresi, Hifi àti Jebusi.
Amaiba: le, Na da ili Idibidi dunuma gaga: musa: misi dagoi. Na da Na fi amo Idibidi soge ganodini esala amo fisili masa: ne gadili hiougili, soge bagade noga: idafa amoga asunasimu. Amo soge ganodini wali dunu fi esala da Ga: ina: ne dunu fi, Hidaide dunu, A:moulaide, Belesaide, Haifaide amola Yebusaide, amo fi esala.
9 Ǹjẹ́ nísinsin yìí, wò ó, igbe àwọn ará Israẹli ti dé ọ̀dọ̀ mi, Èmi sì ti rí bí àwọn ará Ejibiti ti ṣe ń gbà ń jẹ wọ́n ní ìyà.
Na da dafawane Na fi ilia dinana wele sia: be nabi dagoi. Amola Idibidi fi da ilima banenesili hamonana Na da ba: i dagoi.
10 Ǹjẹ́ nísinsin yìí, lọ, èmi yóò rán ọ sí Farao láti kó àwọn ènìyàn Israẹli jáde kúrò ní ilẹ̀ Ejibiti.”
Na da wali di Felouma asunasimu. Bai di da Na fi bisili Idibidi soge fisili masa: ne gadili oule masunu.
11 Ṣùgbọ́n Mose wí fún Ọlọ́run pé, “Ta ni èmi, tí èmi yóò tọ Farao lọ, ti èmi yóò sì kó àwọn ará Israẹli jáde kúrò ni ilẹ̀ Ejibiti?”
Be Mousese da Godema amane sia: i, “Na da hamedei dunu agoane. Na da habodane Felouma asili Isala: ili dunu Idibidi sogega gadili oule masa: bela: ?
12 Nígbà náà ni Ọlọ́run wí fún Mose pé, “Èmi yóò wà pẹ̀lú rẹ. Èyí ni yóò jẹ́ àmì fún ọ, tí yóò fihàn pé, èmi ni ó rán ọ lọ, nígbà tí ìwọ bá kó àwọn ènìyàn náà jáde kúrò ní ilẹ̀ Ejibiti, ẹ̀yin yóò sin Ọlọ́run ni orí òkè yìí.”
Gode da bu adole i, “Na ani esalumu. Di da Na fi dunu Idibidi sogega gadili oule asili, di da guiguda: goumia Nama nodone sia: ne gadomu. Amo hou da Nisu da di asunasi dagoi dawa: digima: ne olelesu dialebe ba: mu.”
13 Mose sì wí fún Ọlọ́run pé, “Bí mo bá tọ àwọn ará Israẹli lọ tí mo sì sọ fún wọn pé, ‘Ọlọ́run àwọn baba yín ni ó rán mi sí i yín,’ tí wọ́n sì béèrè lọ́wọ́ mi pé, ‘Kí ni orúkọ rẹ̀?’ Kí ni èmi yóò sọ fún wọn ní ìgbà náà?”
Be Mousese da bu adole i, “Na da Isala: ili dunu ilima ahoasea amola ilima amane sia: sea, ‘Ninia aowalalia Gode da na asunasi,’ ilia da nama amane adole ba: mu, ‘Ea Dio da nowala: ?’ Amaiba: le, na da ilima adi adole ima: bela: ?”
14 Ọlọ́run sì sọ fún Mose pé, “èmi ni ti ń jẹ́ èmi ni. Èyí ni ìwọ yóò sọ fún àwọn ará Israẹli: ‘èmi ni ni ó rán mi sí i yín.’”
Gode da amane sia: i. “Na da Nisu Esala amola Esalu amola Esalumu. Di Isala: ili dunuma adoma, Dunu Ea Dio da “Na da Na” (dawa: loma: ne da “Na da Esala amola Esalu amola Esalumu”) E da na dilima asunasi dagoi.” Amola Gode da eno amane sia: i,
15 Ọlọ́run sì wí fún Mose pẹ̀lú pé, “Báyìí ni kí ìwọ sọ fún àwọn ọmọ Israẹli, ‘Olúwa Ọlọ́run àwọn baba yín; Ọlọ́run Abrahamu, Ọlọ́run Isaaki àti Ọlọ́run Jakọbu; ni ó rán mi sí i yín.’ “Èyí ni orúkọ mi títí ayérayé, orúkọ ti ẹ ó fi máa rántí mi láti ìran dé ìran.
“Ilima amane adoma, ‘Na, Hina Gode, ilia aowalalia Gode, A:ibalaha: me, Aisage amola Ya: igobe ilia Gode, da di ilima asunasi dagoi. Amo da Na Dio eso huluane mae fisili dialumu. Iligaga fi huluane fa: no lalelegesea da amo Dio Nama sia: mu.
16 “Lọ, kó àwọn àgbàgbà Israẹli jọ, kí o sì wí fún wọn pé, ‘Olúwa Ọlọ́run àwọn baba yín, Ọlọ́run Abrahamu, ti Isaaki, àti ti Jakọbu; ni ó farahàn mi, ó sì wí pé, lóòótọ́ èmi ti ń bojú wò yín, èmi sì ti rí ohun tí wọ́n ṣe sí i yín ni ilẹ̀ Ejibiti.
Masa! Isala: ili dunu fi ouligisu dunu huluane gilisima. Ilima amo Na, Hina Gode, ilia aowalalia Gode, A:ibalaha: me, Aisage amola Ya: igobe ilia Gode, da dima misi dagoi, amo adoma. Ilima amane adoma, Na da ilima misini amola Idibidi fi ilima banenesisu hamosu huluane Na da ba: i dagoi.
17 Èmi sì ti ṣe ìlérí láti mú un yín jáde kúrò nínú ìpọ́njú yín ni ilẹ̀ Ejibiti wá sí ilẹ̀ Kenaani, ará Hiti, Amori, Peresi, Hifi àti Jebusi; ilẹ̀ tí ó ń sàn fún wàrà àti oyin.’
Na da ili Idibidi soge ganodini se nabawane esala, amoga fisili masa: ne gadili hiougimu. Amasea, Na da soge noga: idafa, fedege agoane amo ganodini dodo maga: me amola agime hano da hano agoane a: i ahoa, (amo ganodini wali Ga: ina: ne dunu, Hidaide dunu, A:moulaide dunu, Belesaide dunu, Haifaide dunu amola Yebusaide dunu wali amogai esala), amo sogega Na da Isala: ili dunu fi oule masunu.
18 “Àwọn àgbàgbà Israẹli yóò fetísílẹ̀ sí ohùn rẹ. Nígbà náà ni ìwọ, àti àwọn àgbàgbà yóò jọ tọ ọba Ejibiti lọ, ẹ ó sì wí fún un pé, ‘Olúwa, Ọlọ́run àwọn ará Heberu ti pàdé wa. Jẹ́ kí a lọ ni ìrìn ọjọ́ mẹ́ta sí inú aginjù láti lọ rú ẹbọ sí Olúwa Ọlọ́run.’
Na fi dunu da dia sia: nabimu. Amasea, di da Isala: ili fi ouligisu dunu amo Felouma oule masa. Ema amane sia: ma, ‘Hina Gode, Hibulu dunu ilia Gode, da ninima misi dagoi. Di wali ninia logo doasima. Ninia da wadela: i hafoga: i soge, amoga eso udiana ahoasea, ninia Hina Godema gobele salasu hou hamomusa: gini masunu galebe.
19 Ṣùgbọ́n èmi mọ̀ pé ọba Ejibiti kò ní jẹ́ kí ẹ lọ bí kò ṣe pé ọwọ́ ńlá Ọlọ́run wà ni ara rẹ̀.
Be Idibidi hina bagade (Felou) da dilia logo hame doasimu. Na da ema gasa bagade logebeba: le fawane e da dilia logo doasimu.
20 Nítorí náà, èmi yóò na ọwọ́ mí láti lu àwọn ará Ejibiti pẹ̀lú gbogbo ohun ìyanu tí èmi yóò ṣe ni àárín wọn. Lẹ́yìn náà, òun yóò jẹ́ kí ẹ máa lọ.
Amaiba: le, Na da Idibidi dunuma Na gasa bagade hou olelemu. Na da Idibidi fi ilima se bagade imunu. Musa: hame ba: i beda: su liligi ilima olelemu. Amasea, dilia ga masa: ne, e da dilia logo doasimu.
21 “Èmi yóò sì jẹ́ kí ẹ bá ojúrere àwọn ará Ejibiti pàdé. Tí yóò fi jẹ́ pé ti ẹ̀yin bá ń lọ, ẹ kò ní lọ ní ọwọ́ òfo.
Na da hamobeba: le, Idibidi dunu da dilima nodomu. Amasea, Na fi dunu da gadili ahoasea, ilia da mae gaguiwane hame masunu.
22 Gbogbo àwọn obìnrin ni ó ní láti béèrè lọ́wọ́ àwọn aládùúgbò wọn àti gbogbo àwọn obìnrin ti ń gbé nínú ilé rẹ fún ohun fàdákà àti wúrà àti fún aṣọ, èyí ti ẹ̀yin yóò wọ̀ sí ọrùn àwọn ọmọ yín ọkùnrin àti obìnrin. Báyìí ni ẹ̀yin yóò sì kó ẹrù àwọn ará Ejibiti.”
Be Isala: ili uda huluane da ilia Idibidi gadenene fi amola Idibidi uda ilia diasuganodini esala, amoma asili, abula, gouli amola silifa amo edegemusa: masunu. Amasea, amo liligi ilia da ilia dunu mano amola uda mano ilima imunu. Amasea, ilia da Idibidi ilia noga: i gagui liligi gadili gaguli masunu,” Gode da amane sia: i.