< Exodus 29 >

1 “Èyí ni ohun tí ìwọ yóò ṣe láti yà wọ́n sí mímọ́, kí wọn lè máa ṣe àlùfáà fún mi. Mú ọ̀dọ́ akọ màlúù kan àti àgbò méjì tí kò ní àbùkù.
To też uczynisz im na poświęcenie ich, aby mi odprawowali urząd kapłański: Weźmij cielca jednego młodego, i dwu baranów zupełnych;
2 Láti ara ìyẹ̀fun aláìwú dídùn, ṣe àkàrà àti àkàrà tí a pò pẹ̀lú òróró, àti àkàrà fẹ́lẹ́fẹ́lẹ́ aláìwú tí a da òróró sí.
I chleby przaśne, i placki przaśne z oliwą zaczynione, i kołacze przaśne, namazane oliwą; z przedniej mąki pszenicznej naczynisz ich.
3 Ìwọ yóò sì kó wọn sínú apẹ̀rẹ̀ kan, ìwọ yóò sì mú wọn wà nínú apẹ̀rẹ̀ náà papọ̀ pẹ̀lú akọ màlúù àti àgbò méjì náà.
A włożysz to w jeden kosz, ofiarować je będziesz w tymże koszu, z cielcem, i z dwiema barany.
4 Nígbà náà ni ìwọ yóò mú Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ wá sí ẹnu-ọ̀nà àgọ́ àjọ, ìwọ yóò sì fi omi wẹ̀ wọ́n.
A Aaronowi i synom jego przystąpić każesz do drzwi namiotu zgromadzenia, i omyjesz je wodą,
5 Ìwọ yóò sì fi ẹ̀wù àwọ̀tẹ́lẹ̀ wọ Aaroni, àti aṣọ ìgúnwà efodu, àti efodu, àti ìgbàyà, kí ó sì fi onírúurú ọnà ọ̀já ẹ̀wù efodu dì í.
A wziąwszy szaty, obleczesz Aarona w suknią, i w płaszcz pod naramiennik, i w naramiennik, i napierśnik, i opaszesz go pasem naramiennika;
6 Ìwọ yóò sì fi fìlà dé e ní orí, ìwọ yóò sì ṣe adé mímọ́ sára fìlà náà.
I włożysz czapkę na głowę jego, a wstawisz koronę świętości na czapkę.
7 Nígbà náà ni ìwọ yóò sì mú òróró ìtasórí, ìwọ yóò sì yà á sí mímọ́ nípa dída òróró sí i ní orí.
Na ostatek weźmiesz olejek pomazywania, i wylejesz na głowę jego, a pomażesz go.
8 Ìwọ yóò sì mú àwọn ọmọ rẹ̀ ìwọ yóò sì fi aṣọ àwọ̀tẹ́lẹ̀ wọ̀ wọ́n
Potem synom jego przystąpić każesz, a obleczesz je w szaty;
9 ìwọ yóò sì fi fìlà dé wọn ni orí. Nígbà náà fi ọ̀já àmùrè di Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀. Iṣẹ́ àlùfáà yóò máa jẹ́ tiwọn ní ìlànà títí ayé. “Báyìí ni ìwọ yóò sì ya Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ sí mímọ́.
I opaszesz je pasem, Aarona i syny jego, a włożysz na nie czapki, i będą mieli kapłaństwo ustawą wieczną; poświęcisz też ręce Aaronowe, i ręce synów jego.
10 “Ìwọ yóò sì mú akọ màlúù wá síwájú àgọ́ àjọ, Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ yóò sì fi ọwọ́ wọn lé akọ màlúù ní orí.
Przywiedziesz też cielca przed namiot zgromadzenia, i włoży Aaron i synowie jego ręce swoje na głowę cielca.
11 Ìwọ yóò sì pa àwọn akọ màlúù náà níwájú Olúwa ní ẹnu-ọ̀nà àgọ́ àjọ.
I zabijesz cielca przed Panem, u drzwi namiotu zgromadzenia.
12 Ìwọ yóò sì mú nínú ẹ̀jẹ̀ akọ màlúù náà, ìwọ yóò sì fi ìka rẹ tọ́ ọ sára ìwo pẹpẹ náà, kí o sì da gbogbo ẹ̀jẹ̀ tókù sí ìsàlẹ̀ pẹpẹ náà.
A wziąwszy krwi z cielca pomażesz na rogach ołtarza palcem swym, a ostatek krwi wylejesz ku spodku ołtarza.
13 Kí o mú gbogbo ọ̀rá tí ó yí inú ká, èyí tí ó bo ẹ̀dọ̀ àti ìwé méjèèjì pẹ̀lú ọ̀rá tí ó wà lára wọn, ìwọ yóò sì sun wọ́n lórí pẹpẹ.
Weźmiesz też wszystkę tłustość okrywającą wnętrze, i odzieczkę z wątroby, i dwie nerki z tłustością ich, a zapalisz to na ołtarzu.
14 Ṣùgbọ́n fi iná sun ẹran akọ màlúù, awọ rẹ̀ àti ìgbẹ́ rẹ̀ lẹ́yìn òde. Ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ ni.
A mięso cielca, i skórę jego, i gnój jego, spalisz ogniem za obozem; bo to jest ofiara za grzech.
15 “Ìwọ yóò sì mú àgbò kan, Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ yóò sì gbọ́wọ́ lé orí àgbò náà.
Barana także jednego weźmiesz, na którego głowę Aaron i synowie jego włożą ręce swoje.
16 Ìwọ yóò sì pa àgbò náà, ìwọ yóò sì mú ẹ̀jẹ̀ rẹ̀, ìwọ yóò sì fi wọ́n pẹpẹ náà yíká.
I zabijesz barana tego, a wziąwszy krwi jego, pokropisz wierzch ołtarza w około.
17 Ìwọ yóò sì gé àgbò náà sí wẹ́wẹ́, ìwọ yóò sì fọ inú àti àwọn ẹsẹ̀ rẹ̀, ìwọ yóò sì tò wọ́n pẹ̀lú orí rẹ̀ lé ara wọn.
A barana zrąbiesz na sztuki, i opłuczesz trzewa jego i nogi jego, i włożysz je na sztuki z niego i na głowę jego.
18 Nígbà náà ni ìwọ yóò sun àgbò náà lórí pẹpẹ. Ẹbọ sísun ni sí Olúwa, olóòórùn dídùn ni, ẹbọ ti a fi iná ṣe sí Olúwa ni.
I zapalisz tego całego barana na ołtarzu; całopalenie to jest Panu, wonią przyjemną, ofiarą ognistą jest Panu.
19 “Ìwọ yóò mú àgbò kejì, Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ yóò fi ọwọ́ wọn lé àgbò náà lórí.
Zatem weźmiesz barana drugiego, a włoży Aaron i synowie jego ręce swoje na głowę barana.
20 Ìwọ yóò sì pa àgbò náà, ìwọ yóò mú nínú ẹ̀jẹ̀ rẹ̀, ìwọ yóò sì tọ́ ọ sí etí ọ̀tún Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀, sí àtàǹpàkò ọwọ́ ọ̀tún wọn, àti sí àtàǹpàkò ẹsẹ̀ ọ̀tún wọn. Ìwọ yóò sì fi ẹ̀jẹ̀ wọ́n pẹpẹ náà yíká.
A zabiwszy onego barana weźmiesz ze krwi jego, i pomażesz koniec ucha Aaronowego, i końce ucha prawego synów jego, i wielkie palce ręki ich prawej, także wielkie palce nogi ich prawej, a wylejesz tę krew na ołtarz w około.
21 Ìwọ yóò mú nínú ẹ̀jẹ̀ tí ó wà lórí pẹpẹ àti nínú òróró ìtasórí, ìwọ yóò sì wọ́n ọn sára Aaroni àti sára aṣọ rẹ̀, sára àwọn ọmọ rẹ àti sára aṣọ wọn. Nígbà náà ni òun àti àwọn ọmọ rẹ̀ àti aṣọ wọn yóò di mímọ́.
Wziąwszy zaś ze krwi, która na ołtarzu, także z olejku pomazywania, pokropisz Aarona, i szaty jego, i szaty synów jego z nim; i będzie poświęcony on i szaty jego, i synowie jego, i szaty synów jego z nim.
22 “Ìwọ yóò mú lára ọ̀rá àgbò náà, ìrù tí ó lọ́ràá, ọ̀rá tí ó yí inú ká, èyí ti ó bo ẹ̀dọ̀, ìwé méjèèjì pẹ̀lú ọ̀rá tí ó wà lára wọn àti itan ọ̀tún. (Èyí ni àgbò fún ìyàsímímọ́.)
Potem weźmiesz z barana łój, i ogon, i tłustość, która okrywa wnętrze, i odzieczkę wątroby, i dwie nerki, i łój, który jest na nich, i łopatkę prawą, albowiem jest baran poświęcenia;
23 Láti inú apẹ̀rẹ̀ ìṣù àkàrà aláìwú, èyí tí ó wà níwájú Olúwa, mú ìṣù kan, àkàrà tí a fi òróró dín àti àkàrà fẹ́lẹ́fẹ́lẹ́ kan.
I bochen chleba jeden, i kołacz chleba z oliwą jeden, i placek jeden z kosza przaśników, który jest przed Panem.
24 Ìwọ yóò fi gbogbo rẹ̀ lé Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ lọ́wọ́, ìwọ yóò sì fì wọ́n gẹ́gẹ́ bí ẹbọ fífì níwájú Olúwa.
A położysz to wszystko na ręce Aaronowe, i na ręce synów jego, i obracać to będziesz tam i sam za ofiarę obracania przed Panem;
25 Nígbà náà ni ìwọ yóò sì gbà wọ́n ní ọwọ́ wọn, ìwọ yóò sì sun wọ́n lórí pẹpẹ pẹ̀lú ẹbọ sísun fún òórùn dídùn níwájú Olúwa, ẹbọ ti a fi iná sun sí Olúwa.
A wziąwszy to z ręku ich, zapalisz na ołtarzu, na całopalenie, na wonność wdzięczną przed Panem; ofiara ognista jest Panu.
26 Ìwọ yóò sì mú igẹ̀ àgbò ìyàsímímọ́ Aaroni, ìwọ yóò si fí ì ni ẹbọ fífì níwájú Olúwa; ìpín tìrẹ ni èyí.
Weźmiesz też piersi z barana poświęcenia, które należą Aaronowi, i obracać je będziesz tam i sam za ofiarę obracania przed Panem, a to będzie dział twój,
27 “Ìwọ yóò sì ya igẹ̀ ẹbọ fífì náà sí mímọ́, àti ìtàn ẹbọ à gbé sọ sókè tí a fì, tí a sì gbé sọ sókè nínú àgbò ìyàsímímọ́ náà, àní nínú èyí tí í ṣe Aaroni àti nínú èyí tí ì ṣe tí àwọn ọmọ rẹ̀.
Poświęcisz też piersi obracania i łopatkę podnoszenia, którą obracano, i którą podnoszono, z barana poświęcenia dla Aarona, i dla synów jego.
28 Èyí ni yóò sì máa ṣe ìpín ti Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ láti ọwọ́ àwọn ọmọ Israẹli nígbà gbogbo. Nítorí ẹbọ à gbé sọ sókè ni ẹbọ tí yóò ṣì ṣe èyí ni ẹbọ tí àwọn ọmọ Israẹli yóò máa ṣe sí Olúwa láti inú ẹbọ àlàáfíà wọn.
A to będzie Aaronowi i synom jego ustawą wieczną od synów Izraelskich, gdyż ofiara podnoszenia jest: i ofiara podnoszenia będzie od synów Izraelskich z ofiar ich spokojnych, ofiara podnoszenia ich będzie Panu.
29 “Aṣọ mímọ́ Aaroni yóò jẹ́ ti irú àwọn ọmọ rẹ̀, nítorí kí a lè máa fi òróró yàn wọ́n kí a sì lè máa yà wọ́n sì mímọ́.
A szaty święte, które są Aaronowe, zostaną synom jego po nim, aby pomazywani byli w nich, a były poświęcane w nich ręce ich.
30 Ọmọ rẹ̀ tí ó bá jẹ àlùfáà ní ipò rẹ̀, tí ó bá wọ̀ yóò máa sì wá sí àgọ́ àjọ láti ṣiṣẹ́ ní Ibi Mímọ́, yóò sì máa wọ̀ wọ́n ní ọjọ́ méje.
Siedem dni będzie w nich chodził kapłan, który będzie na jego miejscu z synów jego, który wchodzić będzie do namiotu zgromadzenia, aby służył w świątnicy.
31 “Ìwọ yóò sì mú àgbò fún ìyàsímímọ́, ìwọ yóò sì bọ ẹran rẹ̀ ní ibi mímọ́ kan.
Barana też poświęcenia weźmiesz, i uwarzysz mięso jego na miejscu świętem.
32 Ní ẹnu-ọ̀nà àgọ́ àjọ ni Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ yóò ti jẹ ẹran àgbò náà àti àkàrà náà tí ó wà nínú apẹ̀rẹ̀.
I jeść będą Aaron i synowie jego mięso onego barana, i chleb, który jest w koszu, u drzwi namiotu zgromadzenia.
33 Wọn yóò sì jẹ nǹkan wọ̀nyí èyí tí a fi ṣe ètùtù náà fún ìyàsímímọ́ àti ìsọdimímọ́ wọn. Ṣùgbọ́n àlejò ni kò gbọdọ̀ jẹ nínú rẹ̀, nítorí pé mímọ́ ni.
Będą to jeść ci, za które się oczyszczenie stało, ku poświęceniu rąk ich, aby poświęceni byli; obcy zaś nie będzie jadł z tego, bo święta rzecz jest.
34 Bí ohun kan nínú ẹran àgbò ìyàsímímọ́ tàbí nínú àkàrà náà bá kù di òwúrọ̀, nígbà náà ni kí ìwọ fi iná sun wọn. A kò gbọdọ̀ jẹ ẹ́, nítorí mímọ́ ni.
A zbyłoliby co mięsa poświęcenia, i chleba aż do poranku, spalisz ostatki ogniem: nie będą tego jeść, bo święta rzecz jest.
35 “Báyìí ni ìwọ yóò ṣì ṣe fún Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ bí ohun gbogbo ti mo paláṣẹ fún ọ, ọjọ́ méje ni ìwọ yóò fi yà wọ́n sí mímọ́.
Tak tedy uczynisz Aaronowi, i synom jego, według wszystkiego, com ci przykazał; przez siedem dni poświęcać będziesz ręce ich.
36 Ìwọ yóò sì máa pa akọ màlúù kọ̀ọ̀kan ní ojoojúmọ́ bí ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ láti ṣe ètùtù. Ìwọ yóò sì wẹ pẹpẹ mọ́ nípa ṣíṣe ètùtù fún un, ìwọ yóò sì ta òróró sí i láti sọ ọ́ dí mímọ́.
Cielca też na grzech ofiarować będziesz na każdy dzień na oczyszczenie, i oczyścisz ołtarz, czyniąc oczyszczenie na nim, i pomażesz go ku poświęceniu jego.
37 Ní ọjọ́ méje ni ìwọ yóò ṣe ètùtù sí pẹpẹ náà, ìwọ yóò sì sọ ọ́ di mímọ́. Nígbà náà ni pẹpẹ náà yóò jẹ́ mímọ́ jùlọ, àti ohunkóhun tí ó bá fi ọwọ́ kàn án yóò jẹ́ mímọ́.
Siedem dni będziesz oczyszczał ołtarz, i poświęcisz go, i będzie ten ołtarz najświętszy; cóżkolwiek się dotknie ołtarza, poświęcono będzie,
38 “Èyí ni ìwọ yóò máa fi rú ẹbọ ní orí pẹpẹ náà: Ọ̀dọ́-àgùntàn méjì ọlọ́dún kan ni ojoojúmọ́ láéláé.
A to jest, co ofiarować będziesz na ołtarzu: dwa baranki roczne, dwa na każdy dzień ustawicznie.
39 Ọ̀dọ́-àgùntàn kan ni ìwọ yóò fi rú ẹbọ ní òwúrọ̀ àti ọ̀dọ́-àgùntàn èkejì ní àṣálẹ́.
Baranka jednego ofiarować będziesz rano, a baranka drugiego ofiarować będziesz między dwoma wieczorami.
40 Pẹ̀lú ọ̀dọ́-àgùntàn ti àkọ́kọ́ rú ẹbọ ìdámẹ́wàá òsùwọ̀n ìyẹ̀fun dídára tí a fi ìdámẹ́rin hínì òróró lára olifi tí a gún, àti ìdámẹ́rin hínì wáìnì bí ẹbọ mímu.
Także dziesiątą część efy mąki pszennej, zmieszanej z oliwą wytłoczoną, której by było czwarta część hyn, a do ofiary mokrej czwarta część hyn wina do jednego baranka.
41 Ọ̀dọ́-àgùntàn kejì ni kí ìwọ kí ó pa rú ẹbọ ní àṣálẹ́ ìwọ yóò sì ṣe sí í gẹ́gẹ́ bí ẹbọ jíjẹ àti ẹbọ mímu bí ti òwúrọ̀ fún òórùn dídùn, ẹbọ tí a fi iná ṣe ni sí Olúwa.
Także baranka drugiego ofiarować będziesz między dwoma wieczorami; według obrzędu ofiary porannej i według ofiary mokrej jej, tak przy niej uczynisz nad wonią przyjemną, i ofiarę zapaloną Panu.
42 “Fún ìrandíran tó ń bọ̀, ni ẹ ó máa ṣe ẹbọ sísun nígbà gbogbo ní ẹnu-ọ̀nà àgọ́ àjọ níwájú Olúwa. Níbẹ̀ èmi yóò pàdé yín, èmi yóò sì bá a yín sọ̀rọ̀;
Całopalenie to ustawicznie będzie w narodziech waszych u drzwi namiotu zgromadzenia przed Panem, gdzie się z wami schodzić będę, abym tam z tobą rozmawiał.
43 níbẹ̀ sì tún ni èmi yóò pàdé àwọn ọmọ Israẹli, a ó sì fi ògo mi ya àgọ́ náà sí mímọ́.
Tam się też schodzić będę z synami Izraelskimi, i będzie miejsce to chwałą moją.
44 “Bẹ́ẹ̀ ni èmi yóò ya àgọ́ àjọ náà sí mímọ́ àti pẹpẹ náà, èmi yóò sì ya Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ sí mímọ́ láti máa ṣe iṣẹ́ bí àlùfáà fún mi.
Bo poświęcę namiot zgromadzenia, i ołtarz, i Aarona, i syny jego poświęcę, aby mi urząd kapłański sprawowali.
45 Nígbà náà ni èmi yóò máa gbé láàrín àwọn ọmọ Israẹli, èmi yóò sì máa ṣe Ọlọ́run wọn.
I będę mieszkał w pośrodku synów Izraelskich, i będę im za Boga.
46 Wọn yóò sì mọ̀ pé Èmi ni Olúwa Ọlọ́run wọn, ẹni tí ó mú wọn jáde láti ilẹ̀ Ejibiti wá, nítorí kí èmi lè máa gbé àárín wọn. Èmi ni Olúwa Ọlọ́run wọn.
A poznają, żem Ja Pan Bóg ich, którym je wywiódł z ziemi Egipskiej, abym mieszkał w pośrodku ich, Ja Pan Bóg ich.

< Exodus 29 >