< Exodus 29 >
1 “Èyí ni ohun tí ìwọ yóò ṣe láti yà wọ́n sí mímọ́, kí wọn lè máa ṣe àlùfáà fún mi. Mú ọ̀dọ́ akọ màlúù kan àti àgbò méjì tí kò ní àbùkù.
Hina Gode da eno amane sia: i, “Di da Elane amola egefelali, Nama gobele salasu hawa: hamoma: ne, agoane momogili gagale ilegema. Bulamagau gawali afadafa waha debe amola sibi gawali aduna amo da aiya o eno ledo hamedei, amo lama.
2 Láti ara ìyẹ̀fun aláìwú dídùn, ṣe àkàrà àti àkàrà tí a pò pẹ̀lú òróró, àti àkàrà fẹ́lẹ́fẹ́lẹ́ aláìwú tí a da òróró sí.
Widi falaua noga: idafa (yisidi hame sali) amo lale, mogili olife susuligi gilisili ga: gi hamoma. Mogili olife susuligi mae salawane ga: gi hamoma. Mogili belawagi agoane hamone, olife susuligi amoga ulasima.
3 Ìwọ yóò sì kó wọn sínú apẹ̀rẹ̀ kan, ìwọ yóò sì mú wọn wà nínú apẹ̀rẹ̀ náà papọ̀ pẹ̀lú akọ màlúù àti àgbò méjì náà.
Amo daba ganodini salima. Dilia da bulamagau gawali amola sibi gawali aduna Nama gobele salasu hamosea, amo ga: gi hamoi Nama ima.
4 Nígbà náà ni ìwọ yóò mú Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ wá sí ẹnu-ọ̀nà àgọ́ àjọ, ìwọ yóò sì fi omi wẹ̀ wọ́n.
Elane amola egefelali Na Abula Diasu Holeiga oule misa. Ilia da hanoga ulima: ne sia: ma.
5 Ìwọ yóò sì fi ẹ̀wù àwọ̀tẹ́lẹ̀ wọ Aaroni, àti aṣọ ìgúnwà efodu, àti efodu, àti ìgbàyà, kí ó sì fi onírúurú ọnà ọ̀já ẹ̀wù efodu dì í.
Amasea, Elane amoma gobele salasu abula huluane gasisa: lima. Amo da da: i salasu, abula da ‘ifode’ hagudu sala, ‘ifode’, Bidegi Gaga: su amola bulu.
6 Ìwọ yóò sì fi fìlà dé e ní orí, ìwọ yóò sì ṣe adé mímọ́ sára fìlà náà.
Abula habuga ema figisima amola hadigi nina: hamoi liligi (amoga dedei da “Hina Godema hadigi hamoma: ne mogili gagai dagoi”) amo habuga amoga lala: gilisima.
7 Nígbà náà ni ìwọ yóò sì mú òróró ìtasórí, ìwọ yóò sì yà á sí mímọ́ nípa dída òróró sí i ní orí.
Amasea, olife susuligi (Gobele salasu dunu ilegesu liligi) amo lale, amo ea dialuma da: iya sogadigili, gobele salasu dunu ligiagale ilegema.
8 Ìwọ yóò sì mú àwọn ọmọ rẹ̀ ìwọ yóò sì fi aṣọ àwọ̀tẹ́lẹ̀ wọ̀ wọ́n
Elane egefelali oule misini, ilima da: i salasu gasisa: lima.
9 ìwọ yóò sì fi fìlà dé wọn ni orí. Nígbà náà fi ọ̀já àmùrè di Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀. Iṣẹ́ àlùfáà yóò máa jẹ́ tiwọn ní ìlànà títí ayé. “Báyìí ni ìwọ yóò sì ya Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ sí mímọ́.
Ilia hagomo sisiga: musa: , abula bulu legema amola habuga ilia dialumaga lala: gilisima. Di Elane amola egefelali amola iligaga fi da Nama mae yolesili gobele salasu hawa: hamonanoma: ne, ili momogili gagale ilegema.
10 “Ìwọ yóò sì mú akọ màlúù wá síwájú àgọ́ àjọ, Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ yóò sì fi ọwọ́ wọn lé akọ màlúù ní orí.
Bulamagau gawali amo Abula Diasu ea ba: le gaidiga oule misini, Elane amola egefelali da ea dialuma da: iya ilia lobo ligisima: ne sia: ma.
11 Ìwọ yóò sì pa àwọn akọ màlúù náà níwájú Olúwa ní ẹnu-ọ̀nà àgọ́ àjọ.
Abula Diasu holei gadenene, Na, Hina Gode Na ba: le gaidiga amogai bulamagau gawali fanelegema.
12 Ìwọ yóò sì mú nínú ẹ̀jẹ̀ akọ màlúù náà, ìwọ yóò sì fi ìka rẹ tọ́ ọ sára ìwo pẹpẹ náà, kí o sì da gbogbo ẹ̀jẹ̀ tókù sí ìsàlẹ̀ pẹpẹ náà.
Bulamagau gawali ea maga: me mogili lale, dia lobosogo amoga oloda ea ‘hono’ amoga legema. Maga: me oda huluane amo oloda ea bai amoga sogadigima.
13 Kí o mú gbogbo ọ̀rá tí ó yí inú ká, èyí tí ó bo ẹ̀dọ̀ àti ìwé méjèèjì pẹ̀lú ọ̀rá tí ó wà lára wọn, ìwọ yóò sì sun wọ́n lórí pẹpẹ.
Amasea, bulamagau ea oso sefe amo da iga dedebosa, habe noga: i la: di amola fogome ganumu aduna ela sefe amo lale, oloda da: iya gobesima.
14 Ṣùgbọ́n fi iná sun ẹran akọ màlúù, awọ rẹ̀ àti ìgbẹ́ rẹ̀ lẹ́yìn òde. Ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ ni.
Be bulamagau gawali ea hu, ea gadofo amola ea iga huluane dilia abula diasu gilisisu (fisisu) amoga gadili gaguli asili, gobesima. Amo da gobele salasu Nama iaha amo gobele salasu dunu ilia wadela: i hou fadegale fasima: ne hamosa.
15 “Ìwọ yóò sì mú àgbò kan, Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ yóò sì gbọ́wọ́ lé orí àgbò náà.
Sibi gawali afadafa lale, Elane amola egefelali ilia lobo amo ea dialuma da: iya ligisima: ne sia: ma.
16 Ìwọ yóò sì pa àgbò náà, ìwọ yóò sì mú ẹ̀jẹ̀ rẹ̀, ìwọ yóò sì fi wọ́n pẹpẹ náà yíká.
Amasea, amo sibi medole legele, ea maga: me amo oloda ea la: di biyaduyale gala amoga adagala: ma.
17 Ìwọ yóò sì gé àgbò náà sí wẹ́wẹ́, ìwọ yóò sì fọ inú àti àwọn ẹsẹ̀ rẹ̀, ìwọ yóò sì tò wọ́n pẹ̀lú orí rẹ̀ lé ara wọn.
Sibi gawali amo ea da: i hodo dasega: ma. Ea iga amola baligidu emo dodofelalu, ea hodo dasega: i amola dialuma amo da: iya ligisima.
18 Nígbà náà ni ìwọ yóò sun àgbò náà lórí pẹpẹ. Ẹbọ sísun ni sí Olúwa, olóòórùn dídùn ni, ẹbọ ti a fi iná ṣe sí Olúwa ni.
Amo sibi gawali oloda da: iya gobele salasu Nama iasu hamoma: ne, amo gobesima. Na da amo gobele iasu ea gabusiga: hahawane nabimu.
19 “Ìwọ yóò mú àgbò kejì, Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ yóò fi ọwọ́ wọn lé àgbò náà lórí.
Sibi gawali eno (gobele salasu dunu mogili gagale hamoma: ne sibi) amo lale, Elane amola egefelali ilia lobo amo ea dialuma da: iya ligisima: ne sia: ma.
20 Ìwọ yóò sì pa àgbò náà, ìwọ yóò mú nínú ẹ̀jẹ̀ rẹ̀, ìwọ yóò sì tọ́ ọ sí etí ọ̀tún Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀, sí àtàǹpàkò ọwọ́ ọ̀tún wọn, àti sí àtàǹpàkò ẹsẹ̀ ọ̀tún wọn. Ìwọ yóò sì fi ẹ̀jẹ̀ wọ́n pẹpẹ náà yíká.
Amasea amo sibi medole legele, ea maga: me mogili amo Elane amola egefelali ilia ge hedefo lobodafa la: didili, ilia lobodafa ea bi amola ilia emodafa ea bi amoga legema. Maga: me oda amo oloda ea la: di biyaduyale gala amoga adagala: ma.
21 Ìwọ yóò mú nínú ẹ̀jẹ̀ tí ó wà lórí pẹpẹ àti nínú òróró ìtasórí, ìwọ yóò sì wọ́n ọn sára Aaroni àti sára aṣọ rẹ̀, sára àwọn ọmọ rẹ àti sára aṣọ wọn. Nígbà náà ni òun àti àwọn ọmọ rẹ̀ àti aṣọ wọn yóò di mímọ́.
Maga: me oloda da: iya diala amo mogili lale, ilegesu susuligi mogili lale, amo Elane amola egefelali ilia da: i hodo amola ilia abula amoga adagala: ma. Amasea, e amola egefelali da Nama momogili gagai dagoi ba: mu.
22 “Ìwọ yóò mú lára ọ̀rá àgbò náà, ìrù tí ó lọ́ràá, ọ̀rá tí ó yí inú ká, èyí ti ó bo ẹ̀dọ̀, ìwé méjèèjì pẹ̀lú ọ̀rá tí ó wà lára wọn àti itan ọ̀tún. (Èyí ni àgbò fún ìyàsímímọ́.)
Sibi gawali ea sefe la: go, oso sefe amo da iga dedebosa, habe noga: i la: di, fogome ganumu aduna amola ela sefe dedebosu amola emodafa amo gobiheiga damuni fasima.
23 Láti inú apẹ̀rẹ̀ ìṣù àkàrà aláìwú, èyí tí ó wà níwájú Olúwa, mú ìṣù kan, àkàrà tí a fi òróró dín àti àkàrà fẹ́lẹ́fẹ́lẹ́ kan.
Daba amo ganodini agi ga: gi da Nama iasu diala, amoga agi afae olife susuligi gilisi, agi afae susuligi hame sali amola agi afae belowagi agoane hamoi, amo lama.
24 Ìwọ yóò fi gbogbo rẹ̀ lé Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ lọ́wọ́, ìwọ yóò sì fì wọ́n gẹ́gẹ́ bí ẹbọ fífì níwájú Olúwa.
Amo ha: i manu huluane amo Elane amola egefelali ilia lobo ganodini ligisima. Ilia da amo Nama iasu ida: iwane gala modale ligiagama: ne sia: ma.
25 Nígbà náà ni ìwọ yóò sì gbà wọ́n ní ọwọ́ wọn, ìwọ yóò sì sun wọ́n lórí pẹpẹ pẹ̀lú ẹbọ sísun fún òórùn dídùn níwájú Olúwa, ẹbọ ti a fi iná sun sí Olúwa.
Amasea, amo ha: i manu ilima bu lale, oloda da: iya, musa: gobele iasu amo gadodili gobesima. Amo da Nama ha: i manu gobele iasu. Na da ea gabusiga: hahawane nabimu.
26 Ìwọ yóò sì mú igẹ̀ àgbò ìyàsímímọ́ Aaroni, ìwọ yóò si fí ì ni ẹbọ fífì níwájú Olúwa; ìpín tìrẹ ni èyí.
Amo sibi gawali ea bidegi lale, Nama iasu baligili noga: i hamoma: ne momodale ligiagama. Amo bidegi di moma: ne lama.
27 “Ìwọ yóò sì ya igẹ̀ ẹbọ fífì náà sí mímọ́, àti ìtàn ẹbọ à gbé sọ sókè tí a fì, tí a sì gbé sọ sókè nínú àgbò ìyàsímímọ́ náà, àní nínú èyí tí í ṣe Aaroni àti nínú èyí tí ì ṣe tí àwọn ọmọ rẹ̀.
Dilia da gobele salasu dunu gobele salasu hawa: hamoma: ne momogili gagasea, sibi gawali dilia gobele salasu dunu ilegemusa: gobele sala amo ea bidegi amola ea maseledafa, dilia Nama hahawane ima: ne ilegema. Amasea, gobele salasu dunu ilia da amo moma: ne la: didili ligisima.
28 Èyí ni yóò sì máa ṣe ìpín ti Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ láti ọwọ́ àwọn ọmọ Israẹli nígbà gbogbo. Nítorí ẹbọ à gbé sọ sókè ni ẹbọ tí yóò ṣì ṣe èyí ni ẹbọ tí àwọn ọmọ Israẹli yóò máa ṣe sí Olúwa láti inú ẹbọ àlàáfíà wọn.
Na da Na asigi dawa: su hame afadenemu. Na fi dunu da ilia gobele iasu hamosea, ilia da bidegi amola maseledafa amo gobele salasu dunuma imunu. Amo da Na fi dunu ilia Nama hahawane iasu gala.
29 “Aṣọ mímọ́ Aaroni yóò jẹ́ ti irú àwọn ọmọ rẹ̀, nítorí kí a lè máa fi òróró yàn wọ́n kí a sì lè máa yà wọ́n sì mímọ́.
Elane da bogosea, ea gobele salasu abula amo egefelali ilia gobele salasu ilegesea salima: ne, ilima ima.
30 Ọmọ rẹ̀ tí ó bá jẹ àlùfáà ní ipò rẹ̀, tí ó bá wọ̀ yóò máa sì wá sí àgọ́ àjọ láti ṣiṣẹ́ ní Ibi Mímọ́, yóò sì máa wọ̀ wọ́n ní ọjọ́ méje.
Elane nowa egefe da ea sogebi labeba: le, Abula Diasu Hadigi Malei Sesei amo ganodini hawa: hamomusa: gini golili daha, amo da Elane ea abula eso fesuale salawane esalumu.
31 “Ìwọ yóò sì mú àgbò fún ìyàsímímọ́, ìwọ yóò sì bọ ẹran rẹ̀ ní ibi mímọ́ kan.
Sibi gawali amo Elane amola egefelali ilegemusa: medole legei, amo ea hu lale, hadigi sogebi amoga egema.
32 Ní ẹnu-ọ̀nà àgọ́ àjọ ni Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ yóò ti jẹ ẹran àgbò náà àti àkàrà náà tí ó wà nínú apẹ̀rẹ̀.
Ilia da amo amola agi daba ganodini dialebe, Na Abula Diasu amo ea logo holeiga moma: ne sia: ma.
33 Wọn yóò sì jẹ nǹkan wọ̀nyí èyí tí a fi ṣe ètùtù náà fún ìyàsímímọ́ àti ìsọdimímọ́ wọn. Ṣùgbọ́n àlejò ni kò gbọdọ̀ jẹ nínú rẹ̀, nítorí pé mímọ́ ni.
Ha: i manu amo ilia gobele salasu ilegesu gilisisu ganodini hamoi, amo ilia da manu. Amo ha: i manu da hadigi hamoiba: le, gobele salasu dunu fawane da manu.
34 Bí ohun kan nínú ẹran àgbò ìyàsímímọ́ tàbí nínú àkàrà náà bá kù di òwúrọ̀, nígbà náà ni kí ìwọ fi iná sun wọn. A kò gbọdọ̀ jẹ ẹ́, nítorí mímọ́ ni.
Be aya hahabe doaga: sea, hu o agi mogili hame mai dialebe ba: sea, amo gobele salima. Amo da hadigi hamoiba: le, manu da sema bagade.
35 “Báyìí ni ìwọ yóò ṣì ṣe fún Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ bí ohun gbogbo ti mo paláṣẹ fún ọ, ọjọ́ méje ni ìwọ yóò fi yà wọ́n sí mímọ́.
Elane amola egefelali gobele salasu dunu momogili gagama: ne, amo hou Na sia: i defele eso fesuale amoga noga: le hamoma.
36 Ìwọ yóò sì máa pa akọ màlúù kọ̀ọ̀kan ní ojoojúmọ́ bí ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ láti ṣe ètùtù. Ìwọ yóò sì wẹ pẹpẹ mọ́ nípa ṣíṣe ètùtù fún un, ìwọ yóò sì ta òróró sí i láti sọ ọ́ dí mímọ́.
Amo eso fesuale ganodini, eso afae afae huluane wadela: i hou gogolema: ne olofoma: ne, bulamagau gawali afadafa gobele salasu hamoma: ne medole legema.
37 Ní ọjọ́ méje ni ìwọ yóò ṣe ètùtù sí pẹpẹ náà, ìwọ yóò sì sọ ọ́ di mímọ́. Nígbà náà ni pẹpẹ náà yóò jẹ́ mímọ́ jùlọ, àti ohunkóhun tí ó bá fi ọwọ́ kàn án yóò jẹ́ mímọ́.
Eso afae amo hamoma, amola aya eso eno medole legema, asili eso fesuale hamosea fisima. Amasea, oloda da hadigidafa ledo hamedei agoane ba: mu. Amola ea hadigi da gasa bagadeba: le, nowa dunu o liligi da amo oloda digili ba: sea, e da se nabasu ba: mu.
38 “Èyí ni ìwọ yóò máa fi rú ẹbọ ní orí pẹpẹ náà: Ọ̀dọ́-àgùntàn méjì ọlọ́dún kan ni ojoojúmọ́ láéláé.
Eso huluane mae yolesili, dilia da sibi mano aduna amo da ode afadafa esalu amo medole legele oloda da: iya gobele salima.
39 Ọ̀dọ́-àgùntàn kan ni ìwọ yóò fi rú ẹbọ ní òwúrọ̀ àti ọ̀dọ́-àgùntàn èkejì ní àṣálẹ́.
Sibi mano afadafa amo hahabe gobele salima. Eno da daeya gobele salima.
40 Pẹ̀lú ọ̀dọ́-àgùntàn ti àkọ́kọ́ rú ẹbọ ìdámẹ́wàá òsùwọ̀n ìyẹ̀fun dídára tí a fi ìdámẹ́rin hínì òróró lára olifi tí a gún, àti ìdámẹ́rin hínì wáìnì bí ẹbọ mímu.
Sibi mano hahabe gobele salasea, amo gilisili widi falaua l gilogala: me amola ‘lida’ afae olife susuligi ima. Amola waini ‘lida’ afae amo Hina Godema ima: ne sogadigima.
41 Ọ̀dọ́-àgùntàn kejì ni kí ìwọ kí ó pa rú ẹbọ ní àṣálẹ́ ìwọ yóò sì ṣe sí í gẹ́gẹ́ bí ẹbọ jíjẹ àti ẹbọ mímu bí ti òwúrọ̀ fún òórùn dídùn, ẹbọ tí a fi iná ṣe ni sí Olúwa.
Daeya amo sibi mano eno gobele salasea, hahabe defele widi falaua, olife susuligi amola waini amo gilisili ima. Amo da ha: i manu Na, Hina Godema iasu. Na da amo gabusiga: hahawane naba.
42 “Fún ìrandíran tó ń bọ̀, ni ẹ ó máa ṣe ẹbọ sísun nígbà gbogbo ní ẹnu-ọ̀nà àgọ́ àjọ níwájú Olúwa. Níbẹ̀ èmi yóò pàdé yín, èmi yóò sì bá a yín sọ̀rọ̀;
Amo eso huluane mae yolesili, amo gobele salasu gobei dilia Na Abula Diasu Holeiga Nama iasu hamonanoma. Na da amo Logo Holeiga Na fi dunu gousa: le, ilima sia: sa: imu.
43 níbẹ̀ sì tún ni èmi yóò pàdé àwọn ọmọ Israẹli, a ó sì fi ògo mi ya àgọ́ náà sí mímọ́.
Na da amogai Na fi Isala: ili amo gousa: mu. Amola Na hadigi sinenemegi da amo sogebi hadigi hamomu.
44 “Bẹ́ẹ̀ ni èmi yóò ya àgọ́ àjọ náà sí mímọ́ àti pẹpẹ náà, èmi yóò sì ya Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ sí mímọ́ láti máa ṣe iṣẹ́ bí àlùfáà fún mi.
Na da Abula Diasu amola oloda amo hadigi hamomu. Amola Na da Elane amola egefelali eno dunuma afafane, ilia Na gobele salasu hawa: hamoma: ne, momogili gagale ilegemu.
45 Nígbà náà ni èmi yóò máa gbé láàrín àwọn ọmọ Israẹli, èmi yóò sì máa ṣe Ọlọ́run wọn.
Na da Isala: ili fi dunu ilia gilisisu ganodini esalumu amola Na da ilia Gode esalebe ba: mu.
46 Wọn yóò sì mọ̀ pé Èmi ni Olúwa Ọlọ́run wọn, ẹni tí ó mú wọn jáde láti ilẹ̀ Ejibiti wá, nítorí kí èmi lè máa gbé àárín wọn. Èmi ni Olúwa Ọlọ́run wọn.
Na da ilia Hina Gode amola Na da ilia gilisisu ganodini esalumusa: , Idibidi sogega fisili masa: ne gadili asunasi, amo ilia da dawa: mu. Na da ilia Hina Gode!”