< Exodus 24 >

1 Ní ìgbà náà ni Olúwa sọ fún Mose pé, “Gòkè tọ Olúwa wá, ìwọ àti Aaroni, Nadabu àti Abihu àti àádọ́rin àwọn àgbàgbà Israẹli. Ẹ̀yin kì ó sìn ni òkèèrè réré.
Na ka mea ia ki a Mohi, Piki ake ki a Ihowa koutou ko Arona, ko Natapa, ko Apihu, kia whitu tekau ano hoki o nga kaumatua o Iharaira; a me koropiko mai koutou i tawhiti.
2 Ṣùgbọ́n Mose nìkan ṣoṣo ni yóò súnmọ́ Olúwa; àwọn tókù kò gbọdọ̀ súnmọ́ tòsí ibẹ̀. Bẹ́ẹ̀ ni àwọn ènìyàn kò gbọdọ̀ gòkè wá pẹ̀lú rẹ̀.”
Ko Mohi anake hoki e whakatata mai ki a Ihowa: ko ratou ia, kaua ratou e whakatata mai; me te iwi hoki, kaua ratou e piki tahi ake me ia.
3 Nígbà ti Mose lọ láti sọ fún àwọn ènìyàn, gbogbo ọ̀rọ̀ àti òfin Olúwa, wọ́n wí ní ohùn kan pé, “Gbogbo ohun ti Olúwa wí ni àwa yóò ṣe.”
Na ka haere a Mohi, ka korerotia e ia ki te iwi nga kupu katoa a Ihowa, me nga whakariteritenga katoa: a kotahi ano te reo o te iwi katoa ki te whakahoki, ka ki ratou, Ka meatia e matou nga mea katoa i korerotia mai e Ihowa.
4 Nígbà náà ni Mose kọ gbogbo ohun tí Olúwa sọ sílẹ̀. Ó dìde ní kùtùkùtù òwúrọ̀ ọjọ́ kejì, ó sì mọ pẹpẹ ni ẹsẹ̀ òkè náà. Ó ṣe ọ̀wọ́n òkúta méjìlá. Èyí ti ó dúró fún àwọn ẹ̀yà Israẹli méjìlá.
Na ka tuhituhia e Mohi nga kupu katoa a Ihowa; a ka maranga wawe ia i te ata, a hanga ana e ia tetahi aata ki raro iho i te maunga, me nga pou kotahi tekau ma rua mo nga iwi kotahi tekau ma rua o Iharaira.
5 Nígbà náà ni ó rán àwọn ọ̀dọ́mọkùnrin Israẹli, wọ́n sì rú ẹbọ sísun, wọ́n fi ọ̀dọ́ màlúù rú ẹbọ àlàáfíà si Olúwa.
I unga ano e ia etahi taitama o nga tama a Iharaira, hei whakaeke i nga tahunga tinana, hei patu hoki i nga puru hei patunga mo te pai ki a Ihowa.
6 Mose bu ìlàjì ẹ̀jẹ̀ ẹran sínú abọ́, ó sì fi ìlàjì tókù wọn ara pẹpẹ.
Na, ka tango a Mohi i tetahi wahi o te toto, a maka ana e ia ki roto ki nga peihana; ko tetahi wahi hoki o te toto i taia atu ki te aata.
7 Nígbà náà ni ó sì mú ìwé májẹ̀mú, ó sì kà á sí àwọn ènìyàn. Wọ́n dáhùn pé, “Àwa yóò ṣe gbogbo ohun tí Olúwa wí. Àwa yóò sì gbọ́rọ̀.”
Na ka mau ia ki te pukapuka o te kawenata, a korerotia ana ki nga taringa o te iwi: a ka mea ratou, Ko nga mea katoa i kiia mai na e Ihowa ka meatia e matou, ka rongo ano matou.
8 Nígbà náà ni Mose gbé ẹ̀jẹ̀, ó sì wọn sí àwọn ènìyàn náà lára pé, “Èyí ni ẹ̀jẹ̀ májẹ̀mú tí Olúwa ti ṣe pẹ̀lú yín ni ìbámu pẹ̀lú àwọn ọ̀rọ̀ wọ̀nyí.”
Na ka mau a Mohi ki te toto, a taia atu ana e ia ki te iwi, me te ki ano ia, Nana, te toto nei o te kawenata e whakaritea nei e Ihowa ki a koutou mo enei mea katoa.
9 Mose àti Aaroni, Nadabu àti Abihu àti àádọ́rin àwọn àgbàgbà Israẹli gòkè lọ.
Na ka piki ake a Mohi ratou ko Arona, ko Natapa, ko Apihu, me nga kaumatua e whitu tekau o Iharaira;
10 Wọ́n sì rí Ọlọ́run Israẹli. Ní abẹ́ ẹsẹ̀ rẹ̀ ni ohun kan bí i pèpéle ti a fi òkúta safire ṣe wà. Èyí ti ó mọ́ nigínnigín bí àwọ̀ sánmọ̀ fúnra rẹ̀.
Na ka kite i te Atua o Iharaira: kei raro ano i ona waewae me te mea ko te hapira i hanga hei whariki, he rite tonu ano ki te tino rangi te marama.
11 Ṣùgbọ́n Ọlọ́run kò gbé ọwọ́ rẹ̀ sókè sí àwọn àgbàgbà Israẹli wọ̀nyí; wọ́n ri Ọlọ́run, wọ́n jẹ, wọ́n sì mu.
A kihai i totoro tona ringa ki tetahi o nga rangatira o nga tama a Iharaira: heoi, ka titiro atu ratou ki te Atua, ka kai hoki, ka inu.
12 Olúwa sì sọ fún Mose pé, “Gòkè wá sí ọ̀dọ̀ mi, kí o sì dúró níhìn-ín. Èmi yóò sì fún ọ ní wàláà òkúta pẹ̀lú òfin àti ìlànà tí mo ti kọ sílẹ̀ fún ìtọ́sọ́nà wọn.”
Na ka mea a Ihowa ki a Mohi, Piki ake ki ahau ki te maunga, a hei reira koe noho ai: a ka hoatu e ahau ki a koe nga papa kohatu, me te ture, me te whakahau kua oti nei i ahau te tuhituhi, hei whakaako mau ki a ratou.
13 Nígbà náà ni Mose jáde lọ pẹ̀lú Joṣua arákùnrin rẹ̀. Mose lọ sí orí òkè Ọlọ́run.
Na ko te whakatikanga ake o Mohi, raua ko tana tangata, ko Hohua: ka piki atu a Mohi ki te maunga o te Atua.
14 Ó sì wí fún àwọn àgbàgbà pé, “Ẹ dúró dè wá níhìn-ín yìí, títí àwa yóò fi tún padà tọ̀ yín wá, sì kíyèsi i, Aaroni àti Huri ń bẹ pẹ̀lú yín, bí ẹnìkan bá ni ọ̀ràn kan, kí ó tọ̀ wọ́n lọ.”
I mea ano ia ki nga kaumatua, Taria ake maua i konei, kia hoki mai ra ano maua ki a koutou: na, ko Arona raua ko Huru tena hei hoa mo koutou: ki te whai take tetahi tangata, me haere ia ki a raua.
15 Nígbà tí Mose gun orí òkè lọ, ìkùùkuu bo orí òkè náà.
Na piki ana a Mohi ki te maunga, e taupokina ana hoki te maunga e te kapua:
16 Ògo Olúwa sì wà ní orí òkè Sinai. Ìkùùkuu bo orí òkè náà fún ọjọ́ mẹ́fà, ni ọjọ́ keje ni Olúwa kọ sí Mose láti inú ìkùùkuu náà wá.
A i tau te kororia o Ihowa ki runga ki Maunga Hinai; a e ono nga ra i taupokina ai a reira e te kapua; a i te whitu o nga ra ka karanga ia ki a Mohi i waenganui o te kapua.
17 Ni ojú àwọn ọmọ Israẹli ògo Olúwa náà dàbí iná ajónirun ni orí òkè.
A i rite te ahua o te kororia o Ihowa ki te ahi e kai ana i runga i te tihi o te maunga, i te tirohanga a nga tama a Iharaira.
18 Nígbà náà ni Mose wọ inú ìkùùkuu náà bí ó ti ń lọ ní orí òkè. Ó sì wà ni orí òkè náà ni ogójì ọ̀sán àti ogójì òru.
Na ka haere a Mohi ki waenganui o te kapua, a pikitia ana e ia te maunga: a e wha tekau nga ra o Mohi ki runga ki te maunga, e wha tekau hoki nga po.

< Exodus 24 >