< Exodus 23 >

1 “Ìwọ kò gbọdọ̀ tan ìròyìn èké kalẹ̀. Ìwọ kò gbọdọ̀ ran ènìyàn búburú lọ́wọ́ láti jẹ́rìí èké.
Yalghan gepni yaymighin we ya yalghan guwahliq bérip rezil ademge yan basmighin.
2 “Ìwọ kò gbọdọ̀ tẹ̀lé ọ̀pọ̀ ènìyàn láti ṣe aburú. Nígbà tí ìwọ bá jẹ́rìí sí ẹjọ́, ìwọ kò gbọdọ̀ yí ìdájọ́ po nípa gbígbé lẹ́yìn ọ̀pọ̀ ènìyàn.
Topqa egiship rezil ishta bolma yaki dewa-desturlarda guwahliq bergende topqa egiship heqiqetni burmilima.
3 Bẹ́ẹ̀ ni ìwọ kò gbọdọ̀ ṣe ojúsàájú sí tálákà nínú ẹjọ́ rẹ̀.
Kembeghel dewa qilsa, uninggha yan basma.
4 “Bí ìwọ bá ṣe alábàápàdé akọ màlúù tàbí akọ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ọ̀tá rẹ tí ó ṣìnà lọ, rí i dájú pé o mú un padà wá fún un.
Düshminingning kala ya éshiki ézip kétip, sanga uchrap qalsa, uni élip kélip, igisige choqum tapshurup ber.
5 Bí ìwọ bá rí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ẹnìkan tí ó kórìíra rẹ tí ẹrù ṣubú lé lórí, má ṣe fi í sílẹ̀ bẹ́ẹ̀; rí i dájú pé o ran án lọ́wọ́ nípa rẹ.
Eger sanga öch bolghanning éshiki yükni kötürelmey yükning astida yatqinini körseng, uni yardemsiz tashlimay, belki uninggha yardemliship éshikini qopurushup bérishing zörür.
6 “Ìwọ kò gbọdọ̀ du aláìní ní ìdájọ́ òdodo.
Arangdiki kembeghelning dewasida adaletni burmilima.
7 Má ṣe lọ́wọ́ nínú ẹ̀sùn èké, bẹ́ẹ̀ ni ìwọ kò gbọdọ̀ pa aláìṣẹ̀ tàbí olódodo ènìyàn, nítorí Èmi kò ní dá ẹlẹ́bi láre.
Herqandaq saxta ishtin özüngni néri tart; bigunah adem bilen heqqaniy ademni öltürmigin; chünki Men rezil ademni hergiz adil dep aqlimaymen.
8 “Ìwọ kò gbọdọ̀ gba àbẹ̀tẹ́lẹ̀, nítorí pé àbẹ̀tẹ́lẹ̀ ń fọ́ ojú ọlọ́gbọ́n, ó sì ń ba ọ̀rọ̀ olódodo jẹ́.
Shuningdek héchqandaq para yéme; chünki para közi ochuqlarni kor qilip, heqqaniylarning sözlirini burmilaydu.
9 “Ìwọ kò gbọdọ̀ pọ́n àjèjì kan lójú, ẹ̀yin sa ti mọ inú àjèjì, nítorí ẹ̀yin náà ti jẹ́ àjèjì ní ilẹ̀ Ejibiti.
Musapir kishilerge zulum qilma; chünki özünglar Misir zéminida musapir bolup turghan bolghachqa, musapirning rohiy halini bilisiler.
10 “Ní ọdún mẹ́fà ni ìwọ yóò gbin oko rẹ, ìwọ yóò sì kóre èso rẹ̀.
Alte yil öz yéringni térip, hosullirini al.
11 Ṣùgbọ́n ní ọdún keje, jẹ́ kí ilẹ̀ náà wà ní àìkọ àti ní àìlò, jẹ́ kí ilẹ̀ náà kí ó sinmi. Nígbà náà ni tálákà láàrín yín yóò rí oúnjẹ láti ibẹ̀. Ẹranko igbó yóò sì jẹ èyí tí wọ́n fi sílẹ̀. Ìwọ ṣe bákan náà pẹ̀lú ọgbà àjàrà rẹ àti ọgbà olifi rẹ.
Lékin yettinchi yili yerge aram bérip uni bosh qoy; xelqingning namratliri uningdin yighip yésun, ulardin ashqinini janggaldiki haywanlar yésun; shundaqla üzümzarliqing bilen zeytunzarliqingnimu shundaq qilghin.
12 “Ọjọ́ mẹ́fà ni ìwọ yóò ṣe iṣẹ́ rẹ, ìwọ yóò sì sinmi ní ọjọ́ keje, kí akọ màlúù àti kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ bá à lè ní ìsinmi, kí a sì tú ọmọ ìránṣẹ́bìnrin rẹ àti àlejò ti ń gbé ni ilé rẹ lára.
Alte kün ichide öz ishingni ada qilip, yettinchi küni aram élishing zörür. Buning bilen kala-éshekliring aram tapidu, dédikingning oghli bilen musapir kishimu harduqini chiqiridu.
13 “Ẹ máa ṣọ́ra, kí ẹ sì ṣe ohun gbogbo tí mo wí fún un yín. Ẹ má ṣe pe orúkọ òrìṣà, kí a má ṣe gbọ́ orúkọ wọn ní ẹnu yín.
Men sanga éytqinimning hemmisini köngül bölüp ada qil; bashqa ilahlarning namini tilinggha alma; bular hetta aghzingghimu chiqmisun.
14 “Ní ìgbà mẹ́ta ni ìwọ yóò ṣe àjọ fún mi nínú ọdún.
Her yilda üch qétim méning üchün héyt ötküzgin.
15 “Ṣe àjọ àkàrà àìwú; jẹ àkàrà ti kò ní ìwúkàrà fún ọjọ́ méje, bí mo ṣe pàṣẹ fún ọ. Ṣe èyí ní àkókò tí a ti yàn ní oṣù Abibu, nítorí ni oṣù yìí ni ìwọ jáde kúrò ni ilẹ̀ Ejibiti. “Ẹnikẹ́ni kò gbọdọ̀ wá sí iwájú mi ní ọwọ́ òfo.
Aldi bilen «pétir nan héyti»ni ötküz; sanga emr qilghinimdek Abib éyidiki békitilgen künlerde yette kün pétir nan yégin; chünki shu ayda sen Misirdin chiqqaniding. Shu héytta héchkishi aldimgha quruq qol kelmisun.
16 “Ṣe àjọ ìkórè pẹ̀lú èso àkọ́so ọ̀gbìn oko rẹ. “Ṣe àjọ àkójọ oko rẹ ní òpin ọdún, nígbà tí ìwọ bá kó ìre oko rẹ jọ tan.
Sen ejir qilip térighan étizdiki ziraitingning tunji hosulini orghanda «orma héyti»ni ötküz; shundaqla sen ejir singdürüp yerdin axirqi hosul-mehsulatliringni yil axirida yighqanda «hosul yighish héyti»ni ötküz.
17 “Ní ìgbà mẹ́ta ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ ni àwọn ọkùnrin yín yóò máa wá fi ara hàn ní iwájú Olúwa Olódùmarè.
Yilda üch qétim erkekliringning hemmisi Reb Perwerdigarning huzurigha hazir bolsun.
18 “Ìwọ kò gbọdọ̀ rú ẹbọ ẹ̀jẹ̀ sí mi ti òun ti àkàrà tó ní ìwúkàrà. “Bẹ́ẹ̀ ni ọ̀rá ẹbọ àjọ mi ni kò gbọdọ̀ kù títí di òwúrọ̀.
Sen manga atalghan qurbanliqning qénini xémirturuch sélin’ghan nan bilen sunmighin; héyt qurbanliqining yéghini bolsa kéchiche qondurup etigichige saqlima.
19 “Mú àkọ́ká èso ilẹ̀ rẹ tí ó dára jùlọ wá sí ilé Olúwa Ọlọ́run rẹ. “Ìwọ kò gbọdọ̀ bọ ọmọ ewúrẹ́ nínú omi ọmú ìyá rẹ̀.
Zéminingdiki deslepki hosulning eng yaxshsini Perwerdigar Xudayingning öyige élip kel. Oghlaqni anisining sütide qaynitip pishurma.
20 “Kíyèsi èmi rán angẹli kan lọ ní iwájú rẹ, láti ṣọ́ ọ ni ọ̀nà àti láti mú ọ dé ibi ti mo ti pèsè sílẹ̀ fún.
Mana, Men bir Perishtini yolda séni qoghdap, Men sanga teyyarlighan yerge élip barsun dep, aldingda yürüshke ewetimen.
21 Fi ara balẹ̀, kí o sì fetísílẹ̀ sí i, kí o sì gba ohùn rẹ̀ gbọ́; má ṣe ṣọ̀tẹ̀ sí i, nítorí kò ní fi àìṣedéédéé yín jì yín, orúkọ mi wà lára rẹ̀.
Sen uning aldida özüngge agah bol, uning awazigha qulaq sal. Uning zitigha tegme; bolmisa, u itaetsizlikliringni kechürmeydu; chünki Méning namim uningdidur.
22 Bí ìwọ bá fetísílẹ̀ dáradára sí ohùn rẹ̀ tí ẹ sì ṣe ohun gbogbo ti mo ní kí ẹ ṣe, èmi yóò jẹ́ ọ̀tá àwọn ọ̀tá yín. Èmi yóò sì fóòro àwọn tí ń fóòro yín.
Lékin eger sen uning awazigha qulaq sélip, Méning barliq buyrughanlirimgha emel qilsang, Men düshmenliringge düshmen, küshendiliringge küshende bolimen.
23 Angẹli mi yóò lọ níwájú rẹ, yóò sì mú ọ dé ọ̀dọ̀ àwọn ará: Amori, Hiti, Peresi, Kenaani, Hifi àti Jebusi, èmi a sì gé wọn kúrò.
Chünki Méning Perishtem aldingda yürüp, séni Amoriy, Hittiy, Perizziy, Qanaaniy, Hiwiy we Yebusiylarning zéminigha bashlap kiridu; Men ularni yoqitimen.
24 Ìwọ kò gbọdọ̀ foríbalẹ̀ fún òrìṣà wọn, bẹ́ẹ̀ ni, ìwọ kò gbọdọ̀ sìn wọ́n, tàbí kí ẹ tẹ̀lé ìṣe wọn. Kí ìwọ kí ó si wó wọn lulẹ̀, kí ìwọ kí ó sì fọ́ ère òkúta wọ́n túútúú.
Sen ularning ilahlirigha bash urup ibadet qilma we yaki ular qilghandek qilma; belki ularning [butlirini] üzül-késil chéqiwet, but tüwrüklirini üzül-késil kukum-talghan qiliwet;
25 Ẹ̀yin yóò sí máa sin Olúwa Ọlọ́run yin, òun yóò si bùsi oúnjẹ rẹ. Èmi yóò mú àìsàn kúrò láàrín rẹ.
Lékin Xudayinglar Perwerdigarning ibaditide bolunglar. Shundaq qilsanglar U nan bilen süyünglarni beriketleydu; Men barliq késellikni aranglardin chiqirip tashlaymen.
26 Oyún kò ní bàjẹ́ lára obìnrin kan, bẹ́ẹ̀ ni obìnrin kan kì yóò yàgàn ni ilẹ̀ rẹ. Èmi yóò fún ọ ní ẹ̀mí gígùn.
Buning bilen zéminingda boyidin ajrap kétidighan yaki tughmas héchbir ayal yaki charpay bolmaydu; ömrüngning künlirini toluq qilimen.
27 “Èmi yóò rán ẹ̀rù mi lọ ṣáájú rẹ, ìdàrúdàpọ̀ yóò sì wà láàrín àwọn orílẹ̀-èdè tí ẹ bá da ojú kọ. Èmi yóò mú kí àwọn ọ̀tá rẹ yí ẹ̀yìn padà sí ọ, kí wọn sì sá ní iwájú rẹ.
Men séning aldingda wehimimni ewetimen, qaysi taipige yéqinlashsang shularni parakende qilimen; shuning bilen hemme düshmenliringni keynige yandurup qachurimen.
28 Èmi yóò rán oyin ṣáájú rẹ láti lé àwọn ará: Hifi, Kenaani àti Hiti kúrò ni ọ̀nà rẹ.
Hiwiylar, Qanaaniylar we hittiylarni aldingdin qoghlap chiqiriwétishke sériq herilerni aldingda yürüshke ewetimen.
29 Ṣùgbọ́n, Èmi kò ni lé gbogbo wọn jáde ni ọdún kan ṣoṣo, ki ilẹ̀ náà má ba à di ahoro, àwọn ẹranko búburú yóò sì ti pọ̀jù fún ọ.
Emma zéminning Xarabiliship, dalada wehshiy haywanlar awup sanga xewp bolup qalmasliqi üchün, shu ellerni aldingdin bir yilghiche heydiwetmeymen,
30 Díẹ̀díẹ̀ ni èmi yóò máa lé wọn jáde kúrò ní iwájú rẹ, títí ìwọ yóò fi pọ̀ tó láti gba gbogbo ilẹ̀ náà gẹ́gẹ́ bí ìní.
Belki sen awup, zéminni [pütünley] miras qilip bolghuche, az-azdin heydep turimen.
31 “Èmi yóò fi ìdí òpin ààlà ilẹ̀ rẹ lélẹ̀ láti etí Òkun Pupa títí dé òkun àwọn ara Filistini, láti aṣálẹ̀ títí dé etí odò Eufurate, Èmi yóò fa àwọn ènìyàn ti ń gbé ilẹ̀ náà lé ọ lọ́wọ́, ìwọ yóò sì lé wọn jáde kúrò ní iwájú rẹ.
Séning zéminingning chégrilirini Qizil Déngizdin tartip Filistiylerning déngizighiche, shuningdek chöldin tartip [Efrat] deryasighiche békitimen; chünki zéminda turuwatqanlarni heydiwétip yérini igilishing üchün, ularni qolunggha tapshurimen.
32 Ìwọ kò gbọdọ̀ dá májẹ̀mú kankan pẹ̀lú wọn tàbí pẹ̀lú àwọn òrìṣà wọn.
Sen ular bilen we yaki ilahliri bilen héchqandaq bir ehde tüzme.
33 Ìwọ kò gbọdọ̀ jẹ́ kí wọn gbé ni ilẹ̀ rẹ, bí bẹ́ẹ̀ kọ́, wọn yóò mú ọ dẹ́ṣẹ̀ sí mi: nítorí bí ìwọ bá sin òrìṣà wọn, èyí yóò jẹ́ ìdẹ̀kùn fun ọ nítòótọ́.”
Ularning séni aldimda gunahqa patquzmasliqi üchün ularni zéminingda qet’iy turghuzma. Chünki mubada sen ularning ilahlirining ibaditide bolsang, bu ish sanga tuzaq bolidu.

< Exodus 23 >