< Exodus 23 >

1 “Ìwọ kò gbọdọ̀ tan ìròyìn èké kalẹ̀. Ìwọ kò gbọdọ̀ ran ènìyàn búburú lọ́wọ́ láti jẹ́rìí èké.
Сэ ну рэспындешть звонурь неадевэрате. Сэ ну те унешть ку чел рэу, ка сэ фачь о мэртурисире минчиноасэ пентру ел.
2 “Ìwọ kò gbọdọ̀ tẹ̀lé ọ̀pọ̀ ènìyàn láti ṣe aburú. Nígbà tí ìwọ bá jẹ́rìí sí ẹjọ́, ìwọ kò gbọdọ̀ yí ìdájọ́ po nípa gbígbé lẹ́yìn ọ̀pọ̀ ènìyàn.
Сэ ну те ей дупэ мулциме ка сэ фачь рэу ши ла жудекатэ сэ ну мэртурисешть трекынд де партя челор мулць, ка сэ абаць дрептатя.
3 Bẹ́ẹ̀ ni ìwọ kò gbọdọ̀ ṣe ojúsàájú sí tálákà nínú ẹjọ́ rẹ̀.
Сэ ну пэртинешть пе сэрак ла жудекатэ.
4 “Bí ìwọ bá ṣe alábàápàdé akọ màlúù tàbí akọ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ọ̀tá rẹ tí ó ṣìnà lọ, rí i dájú pé o mú un padà wá fún un.
Дакэ ынтылнешть боул врэжмашулуй тэу сау мэгарул луй рэтэчит, сэ и-л адучь акасэ.
5 Bí ìwọ bá rí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ẹnìkan tí ó kórìíra rẹ tí ẹrù ṣubú lé lórí, má ṣe fi í sílẹ̀ bẹ́ẹ̀; rí i dájú pé o ran án lọ́wọ́ nípa rẹ.
Дакэ везь мэгарул врэжмашулуй тэу кэзут суб повара луй, сэ ну тречь пе лынгэ ел, чи сэ-й ажуць сэ я повара де пе мэгар.
6 “Ìwọ kò gbọdọ̀ du aláìní ní ìdájọ́ òdodo.
Ла жудекатэ, сэ ну те атинӂь де дрептул сэракулуй.
7 Má ṣe lọ́wọ́ nínú ẹ̀sùn èké, bẹ́ẹ̀ ni ìwọ kò gbọdọ̀ pa aláìṣẹ̀ tàbí olódodo ènìyàn, nítorí Èmi kò ní dá ẹlẹ́bi láre.
Фереште-те де о ынвинуире недряптэ ши сэ ну оморь пе чел невиноват ши пе чел дрепт, кэч ну вой ерта пе чел виноват.
8 “Ìwọ kò gbọdọ̀ gba àbẹ̀tẹ́lẹ̀, nítorí pé àbẹ̀tẹ́lẹ̀ ń fọ́ ojú ọlọ́gbọ́n, ó sì ń ba ọ̀rọ̀ olódodo jẹ́.
Сэ ну примешть дарурь, кэч даруриле орбеск пе чей че ау окий дескишь ши суческ хотэрыриле челор дрепць.
9 “Ìwọ kò gbọdọ̀ pọ́n àjèjì kan lójú, ẹ̀yin sa ti mọ inú àjèjì, nítorí ẹ̀yin náà ti jẹ́ àjèjì ní ilẹ̀ Ejibiti.
Сэ ну асупрешть пе стрэин; штиць че симте стрэинул, кэч ши вой аць фост стрэинь ын цара Еӂиптулуй.
10 “Ní ọdún mẹ́fà ni ìwọ yóò gbin oko rẹ, ìwọ yóò sì kóre èso rẹ̀.
Тимп де шасе ань, сэ семень пэмынтул ши сэ-й стрынӂь родул.
11 Ṣùgbọ́n ní ọdún keje, jẹ́ kí ilẹ̀ náà wà ní àìkọ àti ní àìlò, jẹ́ kí ilẹ̀ náà kí ó sinmi. Nígbà náà ni tálákà láàrín yín yóò rí oúnjẹ láti ibẹ̀. Ẹranko igbó yóò sì jẹ èyí tí wọ́n fi sílẹ̀. Ìwọ ṣe bákan náà pẹ̀lú ọgbà àjàrà rẹ àti ọgbà olifi rẹ.
Дар ын ал шаптеля, сэ-й дай рэгаз ши сэ-л лашь сэ се одихняскэ; дин родул луй сэ мэнынче сэрачий попорулуй тэу, яр че ва май рэмыне сэ мэнынче фяреле де пе кымп. Тот аша сэ фачь ку вия ши мэслиний тэй.
12 “Ọjọ́ mẹ́fà ni ìwọ yóò ṣe iṣẹ́ rẹ, ìwọ yóò sì sinmi ní ọjọ́ keje, kí akọ màlúù àti kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ bá à lè ní ìsinmi, kí a sì tú ọmọ ìránṣẹ́bìnrin rẹ àti àlejò ti ń gbé ni ilé rẹ lára.
Тимп де шасе зиле сэ-ць фачь лукраря. Дар ын зиуа а шаптя сэ те одихнешть, пентру ка боул ши мэгарул тэу сэ айбэ одихнэ, пентру ка фиул роабей тале ши стрэинул сэ айбэ рэгаз ши сэ рэсуфле.
13 “Ẹ máa ṣọ́ra, kí ẹ sì ṣe ohun gbogbo tí mo wí fún un yín. Ẹ má ṣe pe orúkọ òrìṣà, kí a má ṣe gbọ́ orúkọ wọn ní ẹnu yín.
Сэ пэзиць тот че в-ам спус ши сэ ну ростиць нумеле алтор думнезей: нумеле лор сэ ну се аудэ ешинд дин гура воастрэ.
14 “Ní ìgbà mẹ́ta ni ìwọ yóò ṣe àjọ fún mi nínú ọdún.
Де трей орь пе ан сэ прэзнуешть сэрбэторь ын чинстя Мя.
15 “Ṣe àjọ àkàrà àìwú; jẹ àkàrà ti kò ní ìwúkàrà fún ọjọ́ méje, bí mo ṣe pàṣẹ fún ọ. Ṣe èyí ní àkókò tí a ti yàn ní oṣù Abibu, nítorí ni oṣù yìí ni ìwọ jáde kúrò ni ilẹ̀ Ejibiti. “Ẹnikẹ́ni kò gbọdọ̀ wá sí iwájú mi ní ọwọ́ òfo.
Сэ ций Сэрбэтоаря Азимилор; тимп де шапте зиле, ла время хотэрытэ, ын луна спичелор, сэ мэнынчь азиме, кум ць-ам порунчит – кэч ын луна ачаста ай ешит дин Еӂипт – ши сэ ну вий ку мыниле гоале ынаинтя Мя.
16 “Ṣe àjọ ìkórè pẹ̀lú èso àkọ́so ọ̀gbìn oko rẹ. “Ṣe àjọ àkójọ oko rẹ ní òpin ọdún, nígbà tí ìwọ bá kó ìre oko rẹ jọ tan.
Сэ ций Сэрбэтоаря Сечеришулуй, а челор динтый роаде дин мунка та, дин чея че вей семэна пе кымп; ши сэ ций Сэрбэтоаря Стрынӂерий Роаделор, ла сфыршитул анулуй, кынд вей стрынӂе де пе кымп родул мунчий тале.
17 “Ní ìgbà mẹ́ta ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ ni àwọn ọkùnrin yín yóò máa wá fi ara hàn ní iwájú Olúwa Olódùmarè.
Де трей орь пе ан, тоатэ партя бэрбэтяскэ сэ се ынфэцишезе ынаинтя Домнулуй Думнезеу.
18 “Ìwọ kò gbọdọ̀ rú ẹbọ ẹ̀jẹ̀ sí mi ti òun ti àkàrà tó ní ìwúkàrà. “Bẹ́ẹ̀ ni ọ̀rá ẹbọ àjọ mi ni kò gbọdọ̀ kù títí di òwúrọ̀.
Сэ н-адучь ку пыне доспитэ сынӂеле жертфей Меле; ши грэсимя празникулуй Меу сэ ну рэмынэ тоатэ ноаптя пынэ диминяца.
19 “Mú àkọ́ká èso ilẹ̀ rẹ tí ó dára jùlọ wá sí ilé Olúwa Ọlọ́run rẹ. “Ìwọ kò gbọdọ̀ bọ ọmọ ewúrẹ́ nínú omi ọmú ìyá rẹ̀.
Сэ адучь ын каса Домнулуй Думнезеулуй тэу пырга челор динтый роаде але пэмынтулуй. Сэ ну фербь ун ед ын лаптеле мамей луй.
20 “Kíyèsi èmi rán angẹli kan lọ ní iwájú rẹ, láti ṣọ́ ọ ni ọ̀nà àti láti mú ọ dé ibi ti mo ti pèsè sílẹ̀ fún.
Ятэ, Еу тримит ун Ынӂер ынаинтя та, ка сэ те окротяскэ пе друм ши сэ те дукэ ын локул пе каре л-ам прегэтит.
21 Fi ara balẹ̀, kí o sì fetísílẹ̀ sí i, kí o sì gba ohùn rẹ̀ gbọ́; má ṣe ṣọ̀tẹ̀ sí i, nítorí kò ní fi àìṣedéédéé yín jì yín, orúkọ mi wà lára rẹ̀.
Фий ку окий ын патру ынаинтя Луй ши аскултэ гласул Луй; сэ ну те ымпотривешть Луй, пентру кэ ну вэ ва ерта пэкателе, кэч Нумеле Меу есте ын Ел.
22 Bí ìwọ bá fetísílẹ̀ dáradára sí ohùn rẹ̀ tí ẹ sì ṣe ohun gbogbo ti mo ní kí ẹ ṣe, èmi yóò jẹ́ ọ̀tá àwọn ọ̀tá yín. Èmi yóò sì fóòro àwọn tí ń fóòro yín.
Дар, дакэ вей аскулта гласул Луй ши дакэ вей фаче тот че-ць вой спуне, Еу вой фи врэжмашул врэжмашилор тэй ши потривникул потривничилор тэй.
23 Angẹli mi yóò lọ níwájú rẹ, yóò sì mú ọ dé ọ̀dọ̀ àwọn ará: Amori, Hiti, Peresi, Kenaani, Hifi àti Jebusi, èmi a sì gé wọn kúrò.
Ынӂерул Меу ва мерӂе ынаинтя та ши те ва дуче ла амориць, хетиць, ферезиць, канааниць, хевиць ши иебусиць ши-й вой нимичи.
24 Ìwọ kò gbọdọ̀ foríbalẹ̀ fún òrìṣà wọn, bẹ́ẹ̀ ni, ìwọ kò gbọdọ̀ sìn wọ́n, tàbí kí ẹ tẹ̀lé ìṣe wọn. Kí ìwọ kí ó si wó wọn lulẹ̀, kí ìwọ kí ó sì fọ́ ère òkúta wọ́n túútúú.
Сэ ну те ынкинь ынаинтя думнезеилор лор ши сэ ну ле служешть; сэ ну те ей дупэ попоареле ачестя ын пуртаря лор, чи сэ ле нимичешть ку десэвыршире ши сэ ле дэрымь капиштиле.
25 Ẹ̀yin yóò sí máa sin Olúwa Ọlọ́run yin, òun yóò si bùsi oúnjẹ rẹ. Èmi yóò mú àìsàn kúrò láàrín rẹ.
Вой сэ служиць Домнулуй Думнезеулуй востру, ши Ел вэ ва бинекувынта пыня ши апеле ши ва депэрта боала дин мижлокул тэу.
26 Oyún kò ní bàjẹ́ lára obìnrin kan, bẹ́ẹ̀ ni obìnrin kan kì yóò yàgàn ni ilẹ̀ rẹ. Èmi yóò fún ọ ní ẹ̀mí gígùn.
Ну ва фи ын цара та нич фемее каре сэ-шь лепеде копилул, нич фемее стярпэ. Нумэрул зилелор тале ыл вой фаче сэ фие деплин.
27 “Èmi yóò rán ẹ̀rù mi lọ ṣáájú rẹ, ìdàrúdàpọ̀ yóò sì wà láàrín àwọn orílẹ̀-èdè tí ẹ bá da ojú kọ. Èmi yóò mú kí àwọn ọ̀tá rẹ yí ẹ̀yìn padà sí ọ, kí wọn sì sá ní iwájú rẹ.
Вой тримите гроаза Мя ынаинтя та, вой пуне пе фугэ пе тоате попоареле ла каре вей ажунӂе ши вой фаче ка тоць врэжмаший тэй сэ дя досул ынаинтя та.
28 Èmi yóò rán oyin ṣáájú rẹ láti lé àwọn ará: Hifi, Kenaani àti Hiti kúrò ni ọ̀nà rẹ.
Вой тримите веспиле бондэрешть ынаинтя та ши вор изгони динаинтя та пе хевиць, канааниць ши хетиць.
29 Ṣùgbọ́n, Èmi kò ni lé gbogbo wọn jáde ni ọdún kan ṣoṣo, ki ilẹ̀ náà má ba à di ahoro, àwọn ẹranko búburú yóò sì ti pọ̀jù fún ọ.
Ну-й вой изгони ынтр-ун сингур ан динаинтя та, пентру ка цара сэ н-ажунгэ ун пустиу ши сэ ну се ынмулцяскэ ымпотрива та фяреле де пе кымп.
30 Díẹ̀díẹ̀ ni èmi yóò máa lé wọn jáde kúrò ní iwájú rẹ, títí ìwọ yóò fi pọ̀ tó láti gba gbogbo ilẹ̀ náà gẹ́gẹ́ bí ìní.
Чи ле вой изгони ынчетул ку ынчетул динаинтя та, пынэ вей креште ла нумэр ши вей путя сэ интри ын стэпыниря цэрий.
31 “Èmi yóò fi ìdí òpin ààlà ilẹ̀ rẹ lélẹ̀ láti etí Òkun Pupa títí dé òkun àwọn ara Filistini, láti aṣálẹ̀ títí dé etí odò Eufurate, Èmi yóò fa àwọn ènìyàn ti ń gbé ilẹ̀ náà lé ọ lọ́wọ́, ìwọ yóò sì lé wọn jáde kúrò ní iwájú rẹ.
Ыць вой ынтинде хотареле де ла Маря Рошие пынэ ла маря филистенилор ши де ла пустиу пынэ ла рыу (Еуфрат). Кэч вой да ын мыниле воастре пе локуиторий цэрий ши-й вей изгони динаинтя та.
32 Ìwọ kò gbọdọ̀ dá májẹ̀mú kankan pẹ̀lú wọn tàbí pẹ̀lú àwọn òrìṣà wọn.
Сэ ну фачь легэмынт ку ей, нич ку думнезеий лор.
33 Ìwọ kò gbọdọ̀ jẹ́ kí wọn gbé ni ilẹ̀ rẹ, bí bẹ́ẹ̀ kọ́, wọn yóò mú ọ dẹ́ṣẹ̀ sí mi: nítorí bí ìwọ bá sin òrìṣà wọn, èyí yóò jẹ́ ìdẹ̀kùn fun ọ nítòótọ́.”
Ей сэ ну локуяскэ ын цара та, ка сэ ну те факэ сэ пэкэтуешть ымпотрива Мя, кэч атунч ай служи думнезеилор лор, ши ачаста ар фи о курсэ пентру тине.”

< Exodus 23 >