< Exodus 16 >

1 Ìjọ àwọn ọmọ Israẹli mú ọ̀nà wọn pọ̀n kúrò ni Elimu, wọ́n dé sí ijù Sini tí ó wà láàrín Elimu àti Sinai, ni ọjọ́ kẹ́ẹ̀dógún oṣù kejì tí wọ́n jáde kúrò ni ilẹ̀ Ejibiti.
Na un mwet Israel nukewa mukuiyak liki acn Elim, ac ke len aksingoul limekosr in malem se akluo tukun elos illa liki Egypt, elos tuku nu ke yen mwesis Sin, su oan inmasrlon Elim ac Sinai.
2 Gbogbo ìjọ àwọn ọmọ Israẹli sì ń kùn sí Mose àti Aaroni ní ijù náà.
Ingo yen mwesis elos nukewa torkaskas nu sel Moses ac Aaron
3 Àwọn ọmọ Israẹli wí fún wọn pé, “Àwa ìbá ti ọwọ́ Olúwa kú ni Ejibiti! Níbi tí àwa ti jókòó ti ìkòkò ẹran ti a sì ń jẹ ohun gbogbo tí a fẹ́ ni àjẹyó, ṣùgbọ́n ẹ̀yin mú wa wá sí inú ijù yìí láti fi ebi pa wá tí a ó fi kú.”
ac fahk nu seltal, “LEUM GOD El funu unikuti na Egypt lukun wona. Kut lukun mutana mongo ikwa ac bread nwe ke na kut kihpi. A komtal uskutme nu in acn mwesis se inge ac oru kut in misa ke masrinsral.”
4 Nígbà náà ni Olúwa sọ fún Mose pé, “Èmi yóò rọ òjò oúnjẹ láti ọ̀run wá fún yín. Àwọn ènìyàn yóò sì máa jáde lọ ni ọjọ́ kọ̀ọ̀kan láti kó ìwọ̀nba oúnjẹ ti ó tó fún oúnjẹ òòjọ́ wọn. Ní ọ̀nà yìí ni, èmi yóò fi dán wọn wò láti mọ bóyá wọn yóò máa tẹ̀lé ìlànà mi.
LEUM GOD El fahk nu sel Moses, “Inge nga ac oru mwe mongo in kahkma inkusrao me nu suwos nukewa. Len nukewa mwet uh ac fah tufoki ac sifani ma fal nu ke len se. In ouiya se inge nga fah srikalos in liye lah elos ac oru oana ma nga sapkin.
5 Ní ọjọ́ kẹfà, ki wọn kó ìlọ́po méjì èyí tiwọn ń ko ni ojoojúmọ́ tẹ́lẹ̀.”
Ke len se akonkosr elos in use sunun len luo ac akmolyela.”
6 Mose àti Aaroni sọ fún gbogbo àwọn ọmọ Israẹli pé, “Ní ìrọ̀lẹ́, ẹ̀yin yóò mọ̀ pé Olúwa ni ó mú un yín jáde láti Ejibiti wá.
Ouinge Moses ac Aaron fahk nu sin mwet Israel nukewa, “Oyeku kowos fah etu lah LEUM GOD pa uskowosme liki Egypt.
7 Ní òwúrọ̀, ẹ̀yin yóò ri ògo Olúwa, nítorí òun ti gbọ́ kíkùn tí ẹ kùn sí i. Ta ni àwa ti ẹ̀yin yóò máa kùn sí wa?”
Lututang kowos ac liye kalem wolana su fahkak lah LEUM GOD El oasr yorosr. El lohng torkaskas lowos lainul — aok lainul ac tia lain kut, mweyen kut oru na ma El sapkin nu sesr uh.”
8 Mose tún wí pé, “Ẹ̀yin yóò mọ pé Olúwa ni, nígbà ti ó bá fún un yín ni ẹran ni ìrọ̀lẹ́ àti gbogbo oúnjẹ ti ẹ̀yin ń fẹ́ ni òwúrọ̀, nítorí kíkùn ti ẹ̀yin ń kùn sí i. Ta ni àwa? Ẹ̀yin kò kùn sí àwa, Olúwa ni ẹ̀yin kùn sí i.”
Na Moses el fahk, “LEUM GOD pa ac sot ikwa nowos ke eku, ac lupan bread ma kowos enenu ke lotutang, tuh El lohng tari lupan torkaskas lowos lainul. Pacl kowos torkaskas lain kut uh, pwayeiya uh kowos torkaskas lain LEUM GOD.”
9 Nígbà náà ni Mose sọ fún Aaroni pe, “Sọ fún gbogbo ìjọ àwọn ọmọ Israẹli pe, ‘Ẹ wá sí iwájú Olúwa, nítorí òun ti gbọ́ kíkùn yín.’”
Moses el fahk nu sel Aaron, “Fahk nu sin sruf nukewa lun mwet Israel elos in tuku ac tu ye mutun LEUM GOD, tuh El lohng tari torkaskas lalos.”
10 Ó sì ṣe bí Aaroni ti ń bá gbogbo ìjọ àwọn ọmọ Israẹli sọ̀rọ̀, wọn si bojú wo ìhà ijù, sì kíyèsi ògo Olúwa si farahàn ni àwọsánmọ̀.
Ke Aaron el kaskas nu sin sruf nukewa, elos ngetla nu yen mwesis, ac in kitin pacl ah na kalem wolana lun LEUM GOD sarmelik in pukunyeng se.
11 Olúwa sọ fún Mose pé,
Na LEUM GOD El fahk nu sel Moses,
12 “Èmi ti gbọ́ kíkùn àwọn ọmọ Israẹli. Sọ fun wọn, ‘Ní àṣálẹ́, ẹ̀yin yóò jẹ ẹran, àti ni òwúrọ̀ ni ẹ̀yin yóò jẹ oúnjẹ. Nígbà náà ni ẹ̀yin yóò mọ̀ pé Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín.’”
“Nga lohng tari torkaskas lun mwet Israel. Fahk nu selos lah ke eku nukewa ac fah oasr ikwa nalos, ac ke lotutang nukewa elos ac fah eis lupan bread ma elos enenu. Na elos ac fah etu lah nga, LEUM GOD, pa God lalos.”
13 Ní àṣálẹ́ ọjọ́ náà ni àwọn àparò fò dé, wọ́n sì bo àgọ́ mọ́lẹ̀, ní òwúrọ̀ ìrì sì sẹ̀ yí gbogbo àgọ́ náà ká.
Ke ekela sie u lulap ke won quail sohkma lucng me, ac afunla acn nukewa ke nien aktuktuk uh, ac ke lotutang aunfong uh nwakla acn mwet uh muta we.
14 Nígbà tí ìrì tí ó sẹ̀ bo ilẹ̀ ti lọ, kíyèsi i, ohun tí ó dì, tí ó sì ń yooru bí i yìnyín wà lórí ilẹ̀.
Ac ke aunfong uh wanginla, oasr ma na minini ac fisrasrsrasr se oan infohk uh yen mwesis uh. Arulana fisrasr in mokutkuti.
15 Nígbà tí àwọn ọmọ Israẹli rí i, wọ́n bi ara wọn léèrè pé, “Kí ni èyí?” Nítorí pé wọn kò mọ ohun tí i ṣe. Mose sì wí fún wọn pé, “Èyí ni oúnjẹ tí Olúwa fi fún un yín láti jẹ.
Ke mwet Israel elos liyauk, elos tiana etu lah mea se, ac elos asiyuki sie sin sie, “Mea se inge?” Moses el fahk nu selos, “Pa inge mwe mongo ma LEUM GOD El sot kowos in mongo kac.
16 Èyí ni ohun tí Olúwa ti pàṣẹ, ‘Kí olúkúlùkù máa kó èyí ti ó tó fún un láti jẹ. Ẹ mú òsùwọ̀n omeri kan fún ẹnìkọ̀ọ̀kan ti ó wà nínú àgọ́ yín.’”
LEUM GOD El sapkin tuh kais sie suwos in sifani lupan na ma el enenu — quart luo nu sin kais sie mwet ke sou se.”
17 Àwọn ọmọ Israẹli sì ṣe bí a ti sọ fún wọn; àwọn kan kó púpọ̀, àwọn kan kó kékeré.
Mwet Israel elos oru ouinge — kutu sifani yohk, ac kutu srik.
18 Nígbà tí wọ́n fi òsùwọ̀n omeri wọ̀n-ọ́n, ẹni tí ó kó púpọ̀ kò ní púpọ̀ jù, bẹ́ẹ̀ ni ẹni tí ó kó ìwọ̀nba kò ní kéré jù. Ẹnìkọ̀ọ̀kan kó ìwọ̀nba ti ó tó fún un.
Ke elos srikeya, mwet ma sifani yohk uh tia alukela ma fal, ac mwet ma sifani srik tia pac srik liki ma fal. Kais sie selos sifani fal na nu ke lupan enenu lalos.
19 Mose sì wí fún wọ́n pé, “Kí ẹnikẹ́ni ó má ṣe kó pamọ́ lára rẹ̀ di òwúrọ̀ ọjọ́ kejì.”
Moses el fahk nu selos, “Wangin sie mwet fah karingin kutu ma inge nu ke len se tok ah.”
20 Ṣùgbọ́n, àwọn kan nínú wọn kò fetí sí Mose, wọ́n kó lára rẹ̀ pamọ́ di òwúrọ̀ ọjọ́ kejì, ohun ti wọ́n kó pamọ́ kún fún ìdin, ó sì ti bẹ̀rẹ̀ sí ní rùn. Nítorí náà Mose bínú sí wọn.
A kutu sin mwet uh tia lohngol Moses ac likiya kutu nu ke len tok ah. Ke lotutang tok ah, ma inge sessesla ke ulac ac pusrosrak, na Moses el kasrkusrak selos.
21 Ní òwúrọ̀, ni ojoojúmọ́ ni ẹnìkọ̀ọ̀kan ń lọ kó ìwọ̀nba ti ó tó fún un láti jẹ, bí oòrùn bá sì mú, a sì yọ́.
Lotutang nukewa kais sie mwet sifauk fal nu ke lupa el enenu; ac ke faht uh foli ma lula fin fohk uh kofelik.
22 Ní ọjọ́ kẹfà, wọ́n kó ìlọ́po méjì èyí tiwọn ń kó tẹ́lẹ̀: òsùwọ̀n omeri méjì fún ẹnìkọ̀ọ̀kan; àwọn olórí ìjọ ènìyàn sì wá, wọ́n sì sọ èyí fún Mose.
Ke len se akonkosr elos sifani mwe mongo pacl luo yohk liki len saya uh — quart akosr nu sin kais sie mwet. Mwet kol ke sruf nukewa lun mwet Israel elos tuku ac srumun ma inge nu sel Moses,
23 Ó sì wí fún wọn pé, “Èyí ni ohun tí Olúwa pàṣẹ: ‘Ọ̀la jẹ́ ọjọ́ ìsinmi, ìsinmi mímọ́ fún Olúwa. Ẹ yan èyí ti ẹ̀yin ní yan, kí ẹ sì bọ èyí ti ẹ̀yin ní bọ̀. Ẹ tọ́jú èyí ti ó kù sílẹ̀, kí ẹ pa á mọ́ di òwúrọ̀.’”
na el fahk nu selos, “LEUM GOD El sapkin tuh lutu sie len in mongla mutal, sriyukla in akfulatyal. Omunla ma kowos lungse umin, ac poeleak ma kowos ke poeli. Kutena ma lula fah orekeni in oan nu lutu.”
24 Wọ́n sì tọ́jú rẹ̀ di òwúrọ̀ bí Mose ti pàṣẹ; kò sì rùn bẹ́ẹ̀ ni kò sì ní ìdin.
Ouinge elos orani ma lula nu ke len tok ah, in oana ma Moses el sapkin, na tiana pusrosrak ku ulauk.
25 Mose sì wí fún wọn pé, “Ẹ jẹ ẹ́ ní òní nítorí òní jẹ́ ọjọ́ ìsinmi Olúwa. Ẹ̀yin kò ni rí i ni orí ilẹ̀ ní ọjọ́ òní.
Moses el fahk, “Kang ma inge misenge mweyen misenge len Sabbath, sie len sriyukla nu sin LEUM GOD, ac kowos ac tia konauk kutena mwe mongo likin acn in aktuktuk uh.
26 Ní ọjọ́ mẹ́fà ni kí ẹ fi kó o, ṣùgbọ́n ni ọjọ́ keje ọjọ́ ìsinmi, kò ní sí i fún un yín ni ọjọ́ náà.”
Kowos enenu in sifani mwe mongo ke len onkosr, tusruktu len se akitkosr len in mongla se, na ac fah wangin mongo sifeyukeni ke len sac.”
27 Síbẹ̀síbẹ̀ àwọn ènìyàn kan jáde lọ ní ọjọ́ keje láti kó o, ṣùgbọ́n wọn kò ri nǹkan kan kó.
Ke len se akitkosr kutu sin mwet uh illa in suk mwe mongo, a wangin ma elos konauk.
28 Olúwa sì sọ fún Mose pé, “Yóò ti pẹ́ tó ti ẹ ó kọ̀ láti pa àṣẹ mi àti ìlànà mi mọ́?
Na LEUM GOD El fahk nu sel Moses, “Putaka pacl kowos mwet uh ac srangesr in akos ma nga sapkin uh?
29 Wò ó? Olúwa ti fún un yín ni ọjọ́ ìsinmi, nítorí náà, ni ọjọ́ kẹfà, ó fún un yín ni oúnjẹ ọjọ́ méjì; kí ẹnìkọ̀ọ̀kan dúró ni ibi tí ó gbé wà; kí ẹ má ṣe kúrò ni ibi tí ẹ wà ni ọjọ́ keje.”
Esam lah nga, LEUM GOD, sot sie len in mongla nu suwos, ac ke sripa se inge ke len akonkosr nukewa nga fah sot mwe mongo ma fal nu ke len luo. Mwet nukewa in mutana yen el muta we ke len se akitkosr ac tia som liki lohm sel.”
30 Nítorí náà, àwọn ènìyàn sinmi ní ọjọ́ keje.
Ouinge mwet uh tia orekma ke len se akitkosr.
31 Àwọn ènìyàn Israẹli sì pe oúnjẹ náà ní manna. Ó funfun bí irúgbìn korianderi, ó sì dùn bí àkàrà fẹ́lẹ́fẹ́lẹ́ ti a fi oyin ṣe.
Mwet Israel elos pangon mwe mongo sac manna. Mwe mongo sac oana fita fasrfasr na srisrik se, ac emah uh oana eman flao minini orekla ke honey.
32 Mose wí pé, “Èyí ni ohun tí Olúwa pàṣẹ, ‘Ẹ mú òsùwọ̀n omeri manna kí ẹ sì pa á mọ́ de àwọn ìran ti ń bọ̀, kí wọn kí ó lè rí oúnjẹ ti èmi fi fún un yín jẹ ní ijù, nígbà tí mo mú un yín jáde ni ilẹ̀ Ejibiti.’”
Moses el fahk, “LEUM GOD El sapkin tuh kut in karinganang kutu manna inge tuh fwilin tulik natusr in ku in liye mwe mongo ma El sang kite kut yen mwesis ke El uskutme liki acn Egypt.”
33 Nígbà náà ni Mose sọ fún Aaroni pe, “Mú ìkòkò kan, kí o sì kó manna tí ó kún òsùwọ̀n omeri kan sí inú rẹ̀, kí o sì gbé e kalẹ̀ ni iwájú Olúwa láti tọ́jú rẹ̀ pamọ́ de àwọn ìran ti ń bọ̀.”
Moses el fahk nu sel Aaron, “Eis sie sufa, ac sang luo quart in manna nu loac, na filiya ye mutun LEUM GOD in karinginyukyang nu sin fwil natusr tok uh.”
34 Bí Olúwa ti pàṣẹ fún Mose, Aaroni gbé manna sí iwájú ẹ̀rí láti pa á mọ́.
Oana ma LEUM GOD El sapkin nu sel Moses, ouinge Aaron el filiya sufa sac mutun Tuptup in Wuleang, tuh in ku in karinginyukyang.
35 Àwọn ará Israẹli jẹ manna fún ogójì ọdún títí wọ́n fi dé ilẹ̀ Kenaani ni ibi ti èso ti wà fún wọn láti jẹ, wọ́n jẹ manna títí tí wọ́n fi dé ilẹ̀ agbègbè Kenaani.
Mwet Israel elos mongo manna ke yac angngaul, nwe ke elos sun sisken facl Canaan, acn elos oakwuki we. (
36 (Òsùwọ̀n omeri kan sì jẹ́ ìdákan nínú ìdámẹ́wàá efa.)
Mwe srikasrak flao in pacl meet pangpang “omer,” na omer se oana quart luo.)

< Exodus 16 >