< Exodus 16 >

1 Ìjọ àwọn ọmọ Israẹli mú ọ̀nà wọn pọ̀n kúrò ni Elimu, wọ́n dé sí ijù Sini tí ó wà láàrín Elimu àti Sinai, ni ọjọ́ kẹ́ẹ̀dógún oṣù kejì tí wọ́n jáde kúrò ni ilẹ̀ Ejibiti.
Israel kaminawk boih, Elim ahmuen hoiah angthawk o moe, Elim hoi Sinai salakah kaom, Sin praezaek ah a caeh o; Izip prae hoi tacawthaih khrah hnetto haih ni hatlai pangato naah to ahmuen to a phak o.
2 Gbogbo ìjọ àwọn ọmọ Israẹli sì ń kùn sí Mose àti Aaroni ní ijù náà.
Praezaek ah kaminawk boih mah Mosi hoi Aaron to laisaep o thuih.
3 Àwọn ọmọ Israẹli wí fún wọn pé, “Àwa ìbá ti ọwọ́ Olúwa kú ni Ejibiti! Níbi tí àwa ti jókòó ti ìkòkò ẹran ti a sì ń jẹ ohun gbogbo tí a fẹ́ ni àjẹyó, ṣùgbọ́n ẹ̀yin mú wa wá sí inú ijù yìí láti fi ebi pa wá tí a ó fi kú.”
Israel kaminawk mah nihnik khaeah, Izip prae ah moi thonghaih laom taengah anghnut moe, zok kamhah ah ka caak o naah, Angraeng ih ban hoi ka duek o nahaeloe hoih kue han to mah! Nanghnik mah haeah amkhueng kaminawk hae zok kamtlam ah dueksak hanah, hae praezaek ah na hoih hoi, tiah a naa o.
4 Nígbà náà ni Olúwa sọ fún Mose pé, “Èmi yóò rọ òjò oúnjẹ láti ọ̀run wá fún yín. Àwọn ènìyàn yóò sì máa jáde lọ ni ọjọ́ kọ̀ọ̀kan láti kó ìwọ̀nba oúnjẹ ti ó tó fún oúnjẹ òòjọ́ wọn. Ní ọ̀nà yìí ni, èmi yóò fi dán wọn wò láti mọ bóyá wọn yóò máa tẹ̀lé ìlànà mi.
To naah Angraeng mah Mosi khaeah, Khenah, nangcae han van hoiah takaw kho baktiah kang zohsak han; kaminawk to caeh o nasoe loe, nito caak kakhawt ah takaw to akhui o nasoe; ka paek ih lok tahngai o maw, tahngai o ai, tito hae tiah ka tanoek han.
5 Ní ọjọ́ kẹfà, ki wọn kó ìlọ́po méjì èyí tiwọn ń ko ni ojoojúmọ́ tẹ́lẹ̀.”
Ni tarukto naah loe, ni kalah ah akhuih ih pongah kamtlai alet hnetto ah akhui o nasoe loe, suem o nasoe, tiah a naa.
6 Mose àti Aaroni sọ fún gbogbo àwọn ọmọ Israẹli pé, “Ní ìrọ̀lẹ́, ẹ̀yin yóò mọ̀ pé Olúwa ni ó mú un yín jáde láti Ejibiti wá.
To pongah Mosi hoi Aaron mah Israel kaminawk boih khaeah, Izip prae thung hoi nangcae zaehoikung loe Angraeng ni, tito vai duem ah na panoek o tih;
7 Ní òwúrọ̀, ẹ̀yin yóò ri ògo Olúwa, nítorí òun ti gbọ́ kíkùn tí ẹ kùn sí i. Ta ni àwa ti ẹ̀yin yóò máa kùn sí wa?”
akhawnbang ah doeh Angraeng lensawkhaih to na hnu o tih; na laisaep o haih to Angraeng mah thaih boeh; kaihnik loe kawbang maw ka oh hoi moe, nang laisaep o thuih? tiah a naa hoi.
8 Mose tún wí pé, “Ẹ̀yin yóò mọ pé Olúwa ni, nígbà ti ó bá fún un yín ni ẹran ni ìrọ̀lẹ́ àti gbogbo oúnjẹ ti ẹ̀yin ń fẹ́ ni òwúrọ̀, nítorí kíkùn ti ẹ̀yin ń kùn sí i. Ta ni àwa? Ẹ̀yin kò kùn sí àwa, Olúwa ni ẹ̀yin kùn sí i.”
Mosi mah, Angraeng mah caak han ih moi to duembang ah na paek o ueloe, akhawnbang ah zok amhah hanah takaw to na paek o tih; to naah, Na laisaep o haih lok Angraeng mah thaih boeh, tiah thuih ih lok to akoep tih; kaihnik loe kawbang maw ka oh hoi moe, nang laisaep o thuih? Laisaep kaminawk loe kaihnik laisaep thuih ai ah, Angraeng ni na laisaep o thuih, tiah a naa hoi.
9 Nígbà náà ni Mose sọ fún Aaroni pe, “Sọ fún gbogbo ìjọ àwọn ọmọ Israẹli pe, ‘Ẹ wá sí iwájú Olúwa, nítorí òun ti gbọ́ kíkùn yín.’”
To naah Mosi mah Aaron khaeah, Na laisaep o haih lok to Angraeng mah thaih boeh pongah, anih khaeah angzo oh, tiah thuih pae han a naa.
10 Ó sì ṣe bí Aaroni ti ń bá gbogbo ìjọ àwọn ọmọ Israẹli sọ̀rọ̀, wọn si bojú wo ìhà ijù, sì kíyèsi ògo Olúwa si farahàn ni àwọsánmọ̀.
Aaron mah amkhueng Israel kaminawk boih khaeah lok to thuih pae, nihcae praezaek bangah doeng o naah, tamai nuiah Angraeng lensawkhaih to amtueng.
11 Olúwa sọ fún Mose pé,
Angraeng mah Mosi khaeah,
12 “Èmi ti gbọ́ kíkùn àwọn ọmọ Israẹli. Sọ fun wọn, ‘Ní àṣálẹ́, ẹ̀yin yóò jẹ ẹran, àti ni òwúrọ̀ ni ẹ̀yin yóò jẹ oúnjẹ. Nígbà náà ni ẹ̀yin yóò mọ̀ pé Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín.’”
Israel kaminawk laisaephaih lok to ka thaih boeh; nihcae khaeah, Duembang ah moi to na caa o ueloe, akhawnbang ah takaw to zok kamhah ah na caa o tih; to naah kai loe nangcae ih Angraeng Sithaw ah ka oh, tito na panoek o tih, tiah thui paeh, tiah a naa.
13 Ní àṣálẹ́ ọjọ́ náà ni àwọn àparò fò dé, wọ́n sì bo àgọ́ mọ́lẹ̀, ní òwúrọ̀ ìrì sì sẹ̀ yí gbogbo àgọ́ náà ká.
To na ni duembang ah kuikoemnawk loe nihcae ohhaih ahmuen taeng koimong ah angzoh o tahang; akhawnbang ah loe misatuh kaminawk ataihaih ahmuen taengah dantui to krak.
14 Nígbà tí ìrì tí ó sẹ̀ bo ilẹ̀ ti lọ, kíyèsi i, ohun tí ó dì, tí ó sì ń yooru bí i yìnyín wà lórí ilẹ̀.
Dantui anghmat pacoengah, khenah, praezaek ih long nui ah, dantui baktih kangbuet luet tetta kaom, hmuen to oh.
15 Nígbà tí àwọn ọmọ Israẹli rí i, wọ́n bi ara wọn léèrè pé, “Kí ni èyí?” Nítorí pé wọn kò mọ ohun tí i ṣe. Mose sì wí fún wọn pé, “Èyí ni oúnjẹ tí Olúwa fi fún un yín láti jẹ.
To hmuen to Israel kaminawk mah hnuk o naah, hae loe manna maw? tiah maeto hoi maeto a thuih o. To hmuen loe timaw, tito panoek o ai. Mosi mah nihcae khaeah, Hae loe na caak o hanah Angraeng mah paek ih takaw ni.
16 Èyí ni ohun tí Olúwa ti pàṣẹ, ‘Kí olúkúlùkù máa kó èyí ti ó tó fún un láti jẹ. Ẹ mú òsùwọ̀n omeri kan fún ẹnìkọ̀ọ̀kan ti ó wà nínú àgọ́ yín.’”
Angraeng mah, Kami boih mah caak kakhawt ah akhui oh; kahni im ah kaom a caanawk caak khawt ah, kami maeto mah omer maeto akhui o hanah a thuih pae.
17 Àwọn ọmọ Israẹli sì ṣe bí a ti sọ fún wọn; àwọn kan kó púpọ̀, àwọn kan kó kékeré.
A thuih ih lok baktih toengah Israel kaminawk mah sak o; thoemto kaminawk loe kapop ah akhuih o, thoemto kaminawk mah loe zetta ah akhuih o.
18 Nígbà tí wọ́n fi òsùwọ̀n omeri wọ̀n-ọ́n, ẹni tí ó kó púpọ̀ kò ní púpọ̀ jù, bẹ́ẹ̀ ni ẹni tí ó kó ìwọ̀nba kò ní kéré jù. Ẹnìkọ̀ọ̀kan kó ìwọ̀nba ti ó tó fún un.
To tiah akhui o ih manna to omer hoi tah o naah, kapop ah akhui kami doeh amtlai ai; zetta akhui kami doeh vawt ai; kami boih mah caak khawt ah akhuih o.
19 Mose sì wí fún wọ́n pé, “Kí ẹnikẹ́ni ó má ṣe kó pamọ́ lára rẹ̀ di òwúrọ̀ ọjọ́ kejì.”
To naah Mosi mah nihcae khaeah, Mi kawbaktih doeh akhawnbang khoek to amtlai o sak hmah, tiah a naa.
20 Ṣùgbọ́n, àwọn kan nínú wọn kò fetí sí Mose, wọ́n kó lára rẹ̀ pamọ́ di òwúrọ̀ ọjọ́ kejì, ohun ti wọ́n kó pamọ́ kún fún ìdin, ó sì ti bẹ̀rẹ̀ sí ní rùn. Nítorí náà Mose bínú sí wọn.
Toe thoemto kaminawk mah Mosi mah thuih ih lok to tahngai o ai; akhawnbang khoek to a suek o; toe qong moe, ahmui set pae; to pongah Mosi loe nihcae nuiah palungphui.
21 Ní òwúrọ̀, ni ojoojúmọ́ ni ẹnìkọ̀ọ̀kan ń lọ kó ìwọ̀nba ti ó tó fún un láti jẹ, bí oòrùn bá sì mú, a sì yọ́.
Akhawnbang kruek kami boih mah angmacae caak khawt ah akhui o; ni bet naah loe, amkaw boih.
22 Ní ọjọ́ kẹfà, wọ́n kó ìlọ́po méjì èyí tiwọn ń kó tẹ́lẹ̀: òsùwọ̀n omeri méjì fún ẹnìkọ̀ọ̀kan; àwọn olórí ìjọ ènìyàn sì wá, wọ́n sì sọ èyí fún Mose.
Ni tarukto naah loe kaminawk mah takaw baktiah alet hnetto kamtlai ah akhui o; kami maeto hanah omer hnetto akhuih o; rangpui ukkungnawk loe caeh o moe, to hmuen to Mosi khaeah thuih pae o.
23 Ó sì wí fún wọn pé, “Èyí ni ohun tí Olúwa pàṣẹ: ‘Ọ̀la jẹ́ ọjọ́ ìsinmi, ìsinmi mímọ́ fún Olúwa. Ẹ yan èyí ti ẹ̀yin ní yan, kí ẹ sì bọ èyí ti ẹ̀yin ní bọ̀. Ẹ tọ́jú èyí ti ó kù sílẹ̀, kí ẹ pa á mọ́ di òwúrọ̀.’”
Mosi mah nihcae khaeah, Angraeng mah, khawnbang loe kaciim Angraeng anghakhaih ni, Sabbath ah oh, to pongah hmai paaem koi hmuen to hmai paaem oh ah loe, bueh koi to buet o coek ah; kamtlai to akhawnbang khoek to kahoih ah pakuem oh, tiah a thuih, tiah a naa.
24 Wọ́n sì tọ́jú rẹ̀ di òwúrọ̀ bí Mose ti pàṣẹ; kò sì rùn bẹ́ẹ̀ ni kò sì ní ìdin.
To pongah Mosi mah thuih ih lok baktih toengah, akhawnbang caak hanah a suek o; toe hmuisae ai, qong doeh qong ai.
25 Mose sì wí fún wọn pé, “Ẹ jẹ ẹ́ ní òní nítorí òní jẹ́ ọjọ́ ìsinmi Olúwa. Ẹ̀yin kò ni rí i ni orí ilẹ̀ ní ọjọ́ òní.
Mosi mah nihcae khaeah, to takaw to vaihniah caa oh; vaihni loe Angraeng ih Sabbath ah oh pongah, to hmuen to long ah na hnu o mak ai.
26 Ní ọjọ́ mẹ́fà ni kí ẹ fi kó o, ṣùgbọ́n ni ọjọ́ keje ọjọ́ ìsinmi, kò ní sí i fún un yín ni ọjọ́ náà.”
Ni tarukto naah akhui oh loe patung oh; toe ni sarihto Sabbath niah loe maeto doeh na hnu o mak ai, tiah a naa.
27 Síbẹ̀síbẹ̀ àwọn ènìyàn kan jáde lọ ní ọjọ́ keje láti kó o, ṣùgbọ́n wọn kò ri nǹkan kan kó.
Toe thoemto kaminawk loe akhuih han caeh o nganga; toe maeto doeh hnu o ai.
28 Olúwa sì sọ fún Mose pé, “Yóò ti pẹ́ tó ti ẹ ó kọ̀ láti pa àṣẹ mi àti ìlànà mi mọ́?
To naah Angraeng mah Mosi khaeah, Nangcae mah nasetto maw kang paek o ih lok hoi kai ih kaalok to na aek o han vop?
29 Wò ó? Olúwa ti fún un yín ni ọjọ́ ìsinmi, nítorí náà, ni ọjọ́ kẹfà, ó fún un yín ni oúnjẹ ọjọ́ méjì; kí ẹnìkọ̀ọ̀kan dúró ni ibi tí ó gbé wà; kí ẹ má ṣe kúrò ni ibi tí ẹ wà ni ọjọ́ keje.”
Angraeng mah Sabbath to ang paek o; to pongah ni tarukto ni ah ni hnetto caak hanah takaw to ang paek o; kami boih ni sarihto naah loe angmah ohhaih ahmuen ah om o boih nasoe loe, mi doeh a ohhaih ahmuen hoi tasa bangah tacawt hmah nasoe, tiah a naa.
30 Nítorí náà, àwọn ènìyàn sinmi ní ọjọ́ keje.
To pongah kaminawk loe ni sarihto naah anghak o.
31 Àwọn ènìyàn Israẹli sì pe oúnjẹ náà ní manna. Ó funfun bí irúgbìn korianderi, ó sì dùn bí àkàrà fẹ́lẹ́fẹ́lẹ́ ti a fi oyin ṣe.
Israel kaminawk mah to ih takaw to manna, tiah kawk o; to takaw loe coriander amu baktiah oh, anglung moe, khoitui hoi sak ih takaw baktiah luep.
32 Mose wí pé, “Èyí ni ohun tí Olúwa pàṣẹ, ‘Ẹ mú òsùwọ̀n omeri manna kí ẹ sì pa á mọ́ de àwọn ìran ti ń bọ̀, kí wọn kí ó lè rí oúnjẹ ti èmi fi fún un yín jẹ ní ijù, nígbà tí mo mú un yín jáde ni ilẹ̀ Ejibiti.’”
Mosi mah Angraeng mah paek ih lok loe hae tiah oh; Izip prae thung hoiah kang zaeh o naah, praezaek ah kang pacah o ih takaw to angzo han koi na caanawk mah hnuk o thai hanah, manna to omer maeto kakoi ah suem oh, tiah a thuih, tiah a naa.
33 Nígbà náà ni Mose sọ fún Aaroni pe, “Mú ìkòkò kan, kí o sì kó manna tí ó kún òsùwọ̀n omeri kan sí inú rẹ̀, kí o sì gbé e kalẹ̀ ni iwájú Olúwa láti tọ́jú rẹ̀ pamọ́ de àwọn ìran ti ń bọ̀.”
To pongah Mosi mah Aaron khaeah, Boengloeng maeto la ah loe, to thungah manna omer maeto kakoi ah thaeng ah; na caanawk han pakuem pae hanah, Angraeng hmaa ah suem ah, tiah a naa.
34 Bí Olúwa ti pàṣẹ fún Mose, Aaroni gbé manna sí iwájú ẹ̀rí láti pa á mọ́.
Angraeng mah Mosi khaeah thuih ih lok baktih toengah pakuem hanah, hnukung hmaa ah Aaron mah thaengh.
35 Àwọn ará Israẹli jẹ manna fún ogójì ọdún títí wọ́n fi dé ilẹ̀ Kenaani ni ibi ti èso ti wà fún wọn láti jẹ, wọ́n jẹ manna títí tí wọ́n fi dé ilẹ̀ agbègbè Kenaani.
Anghakhaih prae pha o ai karoek to Israel kaminawk mah saning qui palito thung manna to caak o; Kanaan prae phak khoek to manna to a caak o.
36 (Òsùwọ̀n omeri kan sì jẹ́ ìdákan nínú ìdámẹ́wàá efa.)
Ephah hato thungah maeto loe omer maeto ah oh.

< Exodus 16 >