< Exodus 15 >

1 Nígbà náà ni Mose àti àwọn ọmọ Israẹli kọ orin yìí sí Olúwa, Èmi yóò kọrin sí Olúwa, nítorí òun pọ̀ ní ògo. Ẹṣin àti ẹni tí ó gùn ún ni ó ti sọ sínú Òkun.
Tad Mozus un Israēla bērni dziedāja Tam Kungam šo dziesmu un sacīja: es dziedāšu Tam Kungam, jo Viņš ir ļoti paaugstinājies: zirgus un viņu jātniekus Viņš iegāzis jūrā.
2 Olúwa ni agbára àti orin mi; òun ti di Olùgbàlà mi, òun ni Ọlọ́run mi, èmi ó yìn ín, Ọlọ́run baba mi, èmi ó gbé e ga.
Tas Kungs ir mans spēks un mana dziesma, un Viņš man bijis par pestīšanu: Viņš ir mans stiprais Dievs, es Viņu pagodināšu; Viņš ir mana tēva Dievs, es Viņu paaugstināšu.
3 Ológun ni Olúwa, Olúwa ni orúkọ rẹ,
Tas Kungs ir karavīrs, Kungs ir Viņa vārds.
4 kẹ̀kẹ́ ogun Farao àti ogun rẹ̀ ni ó mú wọ inú Òkun. Àwọn ọmọ-ogun Farao tó jáfáfá jùlọ ni ó rì sínú Òkun Pupa.
Faraona ratus un viņa spēku Viņš iemetis jūrā, un viņa izlasītie virsnieki apslīkuši niedru jūrā.
5 Ibú omi bò wọ́n mọ́lẹ̀; wọ́n sì rì sí ìsàlẹ̀ omi òkun bí òkúta.
Dziļumi tos apklājuši, tie dibenā nogrimuši kā akmens.
6 “Ọwọ́ ọ̀tún rẹ, Olúwa, pọ̀ ní agbára. Ọwọ́ ọ̀tún rẹ, Olúwa, fọ́ àwọn ọ̀tá túútúú.
Ak Kungs! Tava labā roka ir pagodināta caur spēku, Tava labā roka, ak Kungs, ienaidniekus salauzījusi.
7 “Nínú agbára ńlá rẹ ti ó tóbi ìwọ bi àwọn ti ó dìde sí ọ ṣubú. Ìwọ rán ìbínú gbígbóná rẹ; tí ó run wọ́n bí àgémọ́lẹ̀ ìdí koríko.
Un Savā lielā augstumā Tu esi nogāzis Savus pretiniekus, Tu esi izlaidis Savu bardzību, kas tos aprijusi kā rugājus.
8 Pẹ̀lú èémí imú rẹ ni omi fi ń wọ́jọ pọ̀. Ìṣàn omi dìde dúró bí odi; ibú omi sì dìpọ̀ láàrín Òkun.
Un caur Tavu nāšu pūšanu sacēlās ūdeņi, strauti sastājās kā kopā, ūdeņi sastinga jūras vidū.
9 Ọ̀tá ń gbéraga, ó ń wí pé, ‘Èmi ó lépa wọn, èmi ó bá wọn. èmi ó pín ìkógun; èmi ó tẹ́ ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ mi lọ́run lára wọn. Èmi yóò fa idà mi yọ, ọwọ́ mi yóò pa wọ́n run.’
Ienaidnieks sacīja: es dzīšos pakaļ, es panākšu, es dalīšu laupījumu, mana dvēsele pie tiem atriebsies. Es izvilkšu savu zobenu, un mana roka tos izdeldēs.
10 Ìwọ fẹ́ èémí rẹ, òkun ru bò wọ́n mọ́lẹ̀. Wọ́n rì bí òjé ni àárín omi ńlá.
Tu Savu dvašu esi pūtis, jūra tos apklājusi, tie nogrimuši kā svins varenos ūdeņos.
11 Ta ni nínú àwọn òrìṣà tó dàbí rẹ, Olúwa? Ta ló dàbí rẹ: ní títóbi, ní mímọ́ Ẹlẹ́rù ni yìn, tí ń ṣe ohun ìyanu?
Ak Kungs! Kas ir tāds kā Tu? Kas ir tāds kā Tu starp tiem dieviem, pagodināts svētībā, cienījams ar teikšanām, brīnumu darītājs?
12 “Ìwọ na apá ọ̀tún rẹ, ilẹ̀ si gbé wọn mì.
Tu esi izstiepis Savu labo roku, zeme tos aprijusi.
13 Nínú ìfẹ́ rẹ ti kì í sákí Ìwọ ṣe amọ̀nà àwọn ènìyàn náà tí Ìwọ ti rà padà. Nínú agbára rẹ Ìwọ yóò tọ́ wọn, lọ sí ibi ìjókòó rẹ mímọ́.
Tu caur Savu žēlastību esi vadījis šos ļaudis, ko Tu atpestījis, Tu tos esi vadījis caur Savu spēku uz Tavas svētības mājas vietu.
14 Orílẹ̀-èdè yóò gbọ́ wọn yóò wárìrì. Ìkáàánú yóò mi àwọn ènìyàn Filistia.
Tautas to dzird un trīc, bailība tos aizņēmusi, kas Fīlistejā mājo.
15 Ìbẹ̀rù yóò mú àwọn ìjòyè Edomu, àwọn olórí Moabu yóò wárìrì. Àwọn ènìyàn Kenaani yóò sì yọ́ dànù.
Tad Edoma virsnieki iztrūcinājās, trīcēšana aizņem Moaba varenos, sirds izkūst visiem, kas Kanaānā dzīvo.
16 Ìbẹ̀rù bojo yóò ṣubú lù wọ́n, nítorí nína títóbi apá rẹ̀ wọn yóò dúró jẹ́ẹ́ láì mira bí i òkúta, títí àwọn ènìyàn rẹ yóò fi rékọjá, Olúwa, títí tí àwọn ènìyàn tí o ti rà yóò fi rékọjá.
Iztrūcināšana un bailība krīt uz tiem, caur Tava elkoņa lielumu tie paliek klusu kā akmens, tiekams Tavi ļaudis pārstaigās cauri, ak Kungs, tiekams tie ļaudis pārstaigās, ko Tu Sev esi mantojis.
17 Ìwọ yóò mú wọn wá láti gbìn wọ́n ni orí òkè ti ìwọ jogún, ní ibi ti ìwọ ṣe fún ara rẹ, Olúwa. Láti máa gbé ibi mímọ́ ti ìwọ fi ọwọ́ rẹ gbé kalẹ̀, Olúwa.
Tu tos vedi un stādi Savas mantības kalnā, tai vietā, ko Tu, Kungs, esi darījis par Savu mājas vietu, tai svētā vietā, ko Tavas rokas, ak Kungs, ir cēlušas.
18 “Olúwa yóò jẹ ọba láé àti láéláé.”
Tas Kungs ir ķēniņš mūžīgi mūžam.
19 Nígbà ti ẹṣin Farao, kẹ̀kẹ́ ogun àti àwọn ẹlẹ́ṣin rẹ̀ wọ inú Òkun, Olúwa mú kí omi òkun padà bò wọ́n mọ́lẹ̀, ṣùgbọ́n àwọn ọmọ Israẹli rìn lórí ìyàngbẹ ilẹ̀ la òkun kọjá.
Jo Faraona zirgi ar viņa ratiem un ar viņa jātniekiem ir nākuši jūrā, un Tas Kungs jūras ūdenim ir licis pār tiem atpakaļ griezties, bet Israēla bērni caur jūras vidu izgājuši sausām kājām.
20 Miriamu wòlíì obìnrin, arábìnrin Aaroni, mú ohun èlò orin ni ọwọ́ rẹ̀, gbogbo àwọn obìnrin sì jáde tẹ̀lé e pẹ̀lú ìlù òun ijó.
Un Mirjame, tā praviete, Ārona māsa, ņēma bungas savā rokā, un visas sievas izgāja viņai pakaļ ar bungām un diešanu.
21 Miriamu kọrin sí wọn báyìí pé, “Ẹ kọrin sí Olúwa, nítorí òun ni ológo jùlọ. Ẹṣin àti ẹni tí ó gùn ún, ni òun bi ṣubú sínú Òkun.”
Tad Mirjame tiem atbildēja: dziedāt Tam Kungam, jo Viņš ir ļoti paaugstinājies: zirgus un viņu jātniekus Viņš ir iegāzis jūrā.
22 Nígbà náà ni Mose ṣe amọ̀nà àwọn ènìyàn Israẹli jáde láti Òkun Pupa lọ sínú ijù Ṣuri. Wọ́n lọ ní ìrìn ọjọ́ mẹ́ta sínú ijù náà, wọn kò sì rí omi.
Pēc tam Mozus Israēlim lika aiziet no niedru jūras, un tie izgāja līdz Šur tuksnesim un gāja trīs dienas tuksnesī un neatrada ūdeni.
23 Nígbà tí wọ́n dé Mara, wọn kò lè mu omi Mara nítorí omi náà korò. (Nítorí náà ni a ṣe pe ibẹ̀ ni Mara: ibi ìkorò.)
Tad tie nāca uz Māru, bet Māras ūdeni nevarēja dzert, jo tas bija rūgts, tāpēc viņas vārdu nosauc Māra (rūgtums).
24 Àwọn ènìyàn ń kùn sí Mose wí pé, “Kí ni àwa yóò mu?”
Tad tie ļaudis kurnēja pret Mozu un sacīja: ko mēs dzersim?
25 Mose sì ké pe Olúwa, Olúwa sì fi igi kan hàn án, ó sì sọ igi náà sínú omi, omi náà sì dùn. Níbẹ̀ ni Olúwa ti gbé ìlànà àti òfin kalẹ̀ fún wọn, níbẹ̀ ni ó sì ti dán wọn wò.
Un viņš brēca uz To Kungu un Tas Kungs viņam rādīja koku, to viņš ielika tai ūdenī, tad tas ūdens tapa salds.
26 Ó wí pé, “Bí ìwọ bá fetísílẹ̀ dáradára sí òfin Olúwa Ọlọ́run, ti ìwọ sì ṣe ohun tí ó tọ́ ni ojú rẹ̀, ti ìwọ sì tẹ̀lé ohun tí ó pàṣẹ, ti ìwọ si pa ìlànà rẹ̀ mọ́. Èmi kì yóò jẹ́ kí èyíkéyìí nínú àwọn ààrùn wọ̀n-ọn-nì ti mo mú wá sórí àwọn ará Ejibiti wá sí ara rẹ, nítorí Èmi ni Olúwa ti ó mú ọ láradá.”
Tur viņš tiem iecēla likumu un tiesu, un tur viņš tos pārbaudīja un sacīja: ja jūs tikuši(uzmanīgi) klausīsiet Tā Kunga, sava Dieva, balsi, un darīsiet, kas tiesa ir Viņa acīs, un liksiet vērā Viņa baušļus un sargāsiet visus Viņa likumus, tad Es uz jums nelikšu nekādu vājību, ko Es esmu licis uz Ēģipti; jo Es esmu Tas Kungs tavs ārsts.
27 Nígbà ti wọ́n dé Elimu, níbi ti kànga omi méjìlá àti àádọ́rin ọ̀pẹ gbé wà, wọ́n pàgọ́ síbẹ̀ ni etí omi.
Tad tie nāca uz Elim, un tur bija divpadsmit avoti un septiņdesmit palmas, un tie tur apmeta lēģeri pie ūdens.

< Exodus 15 >