< Exodus 15 >

1 Nígbà náà ni Mose àti àwọn ọmọ Israẹli kọ orin yìí sí Olúwa, Èmi yóò kọrin sí Olúwa, nítorí òun pọ̀ ní ògo. Ẹṣin àti ẹni tí ó gùn ún ni ó ti sọ sínú Òkun.
Ana hige'za Mosese'ene Israeli vahe'mo'za ama'na zagame Ra Anumzamofonte hu'za amanage hu'naze, Nagra Ra Anumzamofonte zagame hugahue, na'ankure Agra tusi'a ha' hu agatereneno, mareri sga hu'ne. Hagi hosi agumpi mani'za aza vahera zamasga huno hagerimpi matevutre'ne.
2 Olúwa ni agbára àti orin mi; òun ti di Olùgbàlà mi, òun ni Ọlọ́run mi, èmi ó yìn ín, Ọlọ́run baba mi, èmi ó gbé e ga.
Ra Anumzamo'a hankveni'ane zagame'ni'a mani'neno, Agra nagu'vazi'ne. Agra nagri Anumza mani'negu, agi hentesga nehue. Nenfa Anumzamofona agi'a hentesga hugahue.
3 Ológun ni Olúwa, Olúwa ni orúkọ rẹ,
Ra Anumzamo'a harafa nere, Ra Anumzana agri agi me'ne.
4 kẹ̀kẹ́ ogun Farao àti ogun rẹ̀ ni ó mú wọ inú Òkun. Àwọn ọmọ-ogun Farao tó jáfáfá jùlọ ni ó rì sínú Òkun Pupa.
Ferone sondia vahe'amokizmine karisi ziminena, hagerimpi zmamahere'ne. Ave'masinezmantea kva vahe'amo'za koranke hagerimpi ti nakri'naze.
5 Ibú omi bò wọ́n mọ́lẹ̀; wọ́n sì rì sí ìsàlẹ̀ omi òkun bí òkúta.
Zamagra amefenkame hagerimofo agu'afina havemo hiaza hu'za urami'naze.
6 “Ọwọ́ ọ̀tún rẹ, Olúwa, pọ̀ ní agbára. Ọwọ́ ọ̀tún rẹ, Olúwa, fọ́ àwọn ọ̀tá túútúú.
Kagri kzan tmagamo'a Ra Anumzamoka hanavenentake hu'negenka, ha' vaheka'a zamahenati tre'nane.
7 “Nínú agbára ńlá rẹ ti ó tóbi ìwọ bi àwọn ti ó dìde sí ọ ṣubú. Ìwọ rán ìbínú gbígbóná rẹ; tí ó run wọ́n bí àgémọ́lẹ̀ ìdí koríko.
Kagra himamuka'areti'ene fatgo kavukavaka'areti ha'ma hugante ku'ma haza vahera zamazeri agatenerane. Krimpa teveha'zamo'a, ha' vahe ka'a tevemo traza tefanene hiaza huno tefanane nehie.
8 Pẹ̀lú èémí imú rẹ ni omi fi ń wọ́jọ pọ̀. Ìṣàn omi dìde dúró bí odi; ibú omi sì dìpọ̀ láàrín Òkun.
Kagona gampinti himamu kasimu zaho'mo tina azerimohihi higeno marerigeno, tima enevia timo'a moriri huno mareri'ne.
9 Ọ̀tá ń gbéraga, ó ń wí pé, ‘Èmi ó lépa wọn, èmi ó bá wọn. èmi ó pín ìkógun; èmi ó tẹ́ ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ mi lọ́run lára wọn. Èmi yóò fa idà mi yọ, ọwọ́ mi yóò pa wọ́n run.’
Ha' vahetimo'za hu'za, zmarotago huta ome zamazeri ta feno zazmia refako hanune hu'naze. Zamagrama antahizaza hunerante'za, kazinteti tahe nefriza zmazanu tahe frinaku hu'naze.
10 Ìwọ fẹ́ èémí rẹ, òkun ru bò wọ́n mọ́lẹ̀. Wọ́n rì bí òjé ni àárín omi ńlá.
Kagra zaho ka'a huhu hankeno hagerimo'a refite'zamante'ne. Zamagra tusi'a hanavenentake timofo agu'a tami'naze.
11 Ta ni nínú àwọn òrìṣà tó dàbí rẹ, Olúwa? Ta ló dàbí rẹ: ní títóbi, ní mímọ́ Ẹlẹ́rù ni yìn, tí ń ṣe ohun ìyanu?
Iza anumza tamimpintira magora Kagrikna Anumzana mani'ne, Ra Anumzamoka? Iza magora Kagrikna huno Hankveka'ane Ruotgera hu'ne? Nagru hu'nanke'za Kagi hesga nehazagenka, Kagra kaguvaza nehane?
12 “Ìwọ na apá ọ̀tún rẹ, ilẹ̀ si gbé wọn mì.
Kagra tamaga kazana rusutankeno, mopamo'a zamazeri nakri'ne.
13 Nínú ìfẹ́ rẹ ti kì í sákí Ìwọ ṣe amọ̀nà àwọn ènìyàn náà tí Ìwọ ti rà padà. Nínú agbára rẹ Ìwọ yóò tọ́ wọn, lọ sí ibi ìjókòó rẹ mímọ́.
Kagrama vaheku'ma kavesi zmantenka kasuma tagizmante kavukava zanka'areti, mizasenka zmavre'nana vahera zmavrenka vu'nane. Kagraka'a hankave ka'afi kegava huzmantenka nagru hu'nea kumate ome zamante'nane.
14 Orílẹ̀-èdè yóò gbọ́ wọn yóò wárìrì. Ìkáàánú yóò mi àwọn ènìyàn Filistia.
Vahe'mo'za ana agenkema nentahi'za zmahirahiku hu'naze. Filistia vahe'mo'za tusi'a zamanogu hu'naze.
15 Ìbẹ̀rù yóò mú àwọn ìjòyè Edomu, àwọn olórí Moabu yóò wárìrì. Àwọn ènìyàn Kenaani yóò sì yọ́ dànù.
Itomu kumate ugagota hu'naza vahe'mo'za, tusi koro hu'naze, Moapu kumate kegava hu'naza vahe'mofona, tusi zamano vazi'ne, mika Keneni nemaniza vahe'mofo zamagu'amo'a, ti se'ne.
16 Ìbẹ̀rù bojo yóò ṣubú lù wọ́n, nítorí nína títóbi apá rẹ̀ wọn yóò dúró jẹ́ẹ́ láì mira bí i òkúta, títí àwọn ènìyàn rẹ yóò fi rékọjá, Olúwa, títí tí àwọn ènìyàn tí o ti rà yóò fi rékọjá.
Ra Anumzamoka tusi'a hankave ka'a zamagra nege'za, tusi korozamo zmagrira refitezmantege'za, kaza osu'naze. Zamagra zafa mneankna hu'nenageta, Kagri vahe'mota vugahune. Ra Anumzamoka isipiti tavrenka anketa kinafintira katufeta e'none.
17 Ìwọ yóò mú wọn wá láti gbìn wọ́n ni orí òkè ti ìwọ jogún, ní ibi ti ìwọ ṣe fún ara rẹ, Olúwa. Láti máa gbé ibi mímọ́ ti ìwọ fi ọwọ́ rẹ gbé kalẹ̀, Olúwa.
Kagra zamavarenka erisanti harerantenku'ma hu'nana kumakare emetantegahane. Kagraka'a manigahue hunka kazanuma tro'ma hu'nana kumapi, Ra Anumzamoka ome tantegahane.
18 “Olúwa yóò jẹ ọba láé àti láéláé.”
Ra Anumzamo'a kinia manivava hugahie.
19 Nígbà ti ẹṣin Farao, kẹ̀kẹ́ ogun àti àwọn ẹlẹ́ṣin rẹ̀ wọ inú Òkun, Olúwa mú kí omi òkun padà bò wọ́n mọ́lẹ̀, ṣùgbọ́n àwọn ọmọ Israẹli rìn lórí ìyàngbẹ ilẹ̀ la òkun kọjá.
Na'ankure hosifi maniza nevaza Fero sondia vahe'mo'za hagerimpi ufrazageno, Ra Anumzamo'a hagerina atregeno refitezmante'ne. Hianagi Israel vahe'mo'za hagerimofo amu'nompi hagege hu'nege'za vu'naze.
20 Miriamu wòlíì obìnrin, arábìnrin Aaroni, mú ohun èlò orin ni ọwọ́ rẹ̀, gbogbo àwọn obìnrin sì jáde tẹ̀lé e pẹ̀lú ìlù òun ijó.
Kasnampa a' Miriamu, Aroni nesaro'a nase'nasepa azampi erige'za, mika a'nemo'za nase'nasepa erihanati'za nase'nasepa ati'za avo hage'naze.
21 Miriamu kọrin sí wọn báyìí pé, “Ẹ kọrin sí Olúwa, nítorí òun ni ológo jùlọ. Ẹṣin àti ẹni tí ó gùn ún, ni òun bi ṣubú sínú Òkun.”
Higeno Miriamu'a mago zagame huno, Ra Anumzamofonku zagame hiho, na'ankure Agra marerisga hu'ne. Hosi agumpi mani'naza vahe'ene hosizmine hagerimpi zamasgahu re'ne.
22 Nígbà náà ni Mose ṣe amọ̀nà àwọn ènìyàn Israẹli jáde láti Òkun Pupa lọ sínú ijù Ṣuri. Wọ́n lọ ní ìrìn ọjọ́ mẹ́ta sínú ijù náà, wọn kò sì rí omi.
Ananteti Mosese'a koranke hagerina atreno Israeli vahe'mo'za Sulue nehaza ka'ma kopi zamavareno, 3'a zageferu nevige'za, tina ke'za erifore osu'naze.
23 Nígbà tí wọ́n dé Mara, wọn kò lè mu omi Mara nítorí omi náà korò. (Nítorí náà ni a ṣe pe ibẹ̀ ni Mara: ibi ìkorò.)
Zamagra Marae nehazare'ma ne-eza tina Maratira one'naze. Na'ankure ana timo'a aka hu'ne, E'ina hu'negu (aka hu'ne) Mare hu'za hu'naze,
24 Àwọn ènìyàn ń kùn sí Mose wí pé, “Kí ni àwa yóò mu?”
Ana hige'za vahe'mo'za Mosesena kehakare hunte'za anage hu'naze, ina'na ti negahune?
25 Mose sì ké pe Olúwa, Olúwa sì fi igi kan hàn án, ó sì sọ igi náà sínú omi, omi náà sì dùn. Níbẹ̀ ni Olúwa ti gbé ìlànà àti òfin kalẹ̀ fún wọn, níbẹ̀ ni ó sì ti dán wọn wò.
Anage hazageno Mosese'a Ra Anumzamofo antahigegeno, Anumzamo'a mago zafa averi higeno hantagino ana timpi atregeno, ana timo'a knare hige'za ne'naze. Anante Ra Anumzamo'a mago'a tra kenenteno amage'ma antesagu rezamaheno ke'ne.
26 Ó wí pé, “Bí ìwọ bá fetísílẹ̀ dáradára sí òfin Olúwa Ọlọ́run, ti ìwọ sì ṣe ohun tí ó tọ́ ni ojú rẹ̀, ti ìwọ sì tẹ̀lé ohun tí ó pàṣẹ, ti ìwọ si pa ìlànà rẹ̀ mọ́. Èmi kì yóò jẹ́ kí èyíkéyìí nínú àwọn ààrùn wọ̀n-ọn-nì ti mo mú wá sórí àwọn ará Ejibiti wá sí ara rẹ, nítorí Èmi ni Olúwa ti ó mú ọ láradá.”
Ana nehuno anante Ra Anumzamo'a anage hu'ne, Rantimi Anumzamofo ageru'ma antahitama fatgo zama Agri avufima nehutma, kasege'agu'ma tamagesa anteta nentahitma, mika ke'ama amage'antesazana, magore hu'na kria tamavatera ontegahue, Isipi vahe'ma zmi'noankna kria ontamigahue. Na'ankure Nagra Ra Anumzamo'na, kritamima eri netromo'ne.
27 Nígbà ti wọ́n dé Elimu, níbi ti kànga omi méjìlá àti àádọ́rin ọ̀pẹ gbé wà, wọ́n pàgọ́ síbẹ̀ ni etí omi.
Ananteti Elimie nehaza kumate 12fu'a ti nehanatigeno, 70'a tona'zafa me'nere nona emeki'za tinkenare mani'naze.

< Exodus 15 >