< Exodus 14 >

1 Olúwa sọ fún Mose pé,
Na ka korero a Ihowa ki a Mohi, ka mea,
2 “Sọ fún àwọn ọmọ Israẹli kí wọn padà sẹ́yìn, kí wọ́n sì pàgọ́ sí tòsí Pi-Hahirotu láàrín Migdoli òun Òkun, kí wọn kí ó pàgọ́ sí ẹ̀bá Òkun, ní òdìkejì Baali-Ṣefoni.
Korero ki nga tama a Iharaira, kia tahuri, kia noho ki te ritenga atu o Pihahirota, i waenganui o Mikitoro, o te moana, ki te ritenga o Paarahepona: hei te wahi e hangai tonu ana ki reira, hei te taha o te moana koutou noho ai.
3 Farao yóò ronú pé àwọn ọmọ Israẹli ń ráre káàkiri ní ìdààmú ni àti wí pé aginjù náà ti sé wọn mọ́.
A e kiia nga tama a Iharaira e Parao, E pohehe ana ratou i te whenua, kua tutakina mai ratou e te koraha.
4 Èmi yóò sé ọkàn Farao le ti yóò fi lépa wọn. Ṣùgbọ́n èmi yóò gba ògo fún ará mi láti ìpàṣẹ Farao àti ogun rẹ̀, àti pé àwọn ará Ejibiti yóò mọ̀ pé Èmi ni Olúwa.” Àwọn Israẹli sì ṣe bẹ́ẹ̀.
A maku e whakapakeke te ngakau o Parao, kia wahi ai ia i a ratou: a ka whai kororia ahau i a Parao ratou ko tona nuinga katoa; a ka mohio nga Ihipiana ko Ihowa ahau; a pera ana ratou.
5 Nígbà tí wọ́n sọ fún ọba Ejibiti pé àwọn ènìyàn náà ti sálọ, ọkàn Farao àti àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ yí padà sí àwọn ènìyàn, wọ́n sì wí pé, “Kí ni ohun tí àwa ṣe yìí? Àwa ti jẹ́ kí àwọn ọmọ Israẹli kí ó lọ, a sì ti pàdánù ìsìnrú wọn.”
A ka korerotia ki te kingi o Ihipa, kua whati te iwi: na ka puta ke te ngakau o Parao ratou ko ana tangata, ki te iwi, a ka mea ratou, He aha tenei mahi a tatou, i tukua atu ai a Iharaira i a tatou mahi?
6 Ó sì di kẹ̀kẹ́-ẹṣin rẹ̀, ó sì kó àwọn ọmọ-ogun rẹ̀ pẹ̀lú rẹ̀,
Na ka here ia i tana hariata, i mauria ano hoki e ia tona iwi:
7 ó mú ẹgbẹ̀ta ọmọ-ogun oníkẹ̀kẹ́ tí ó jáfáfá jùlọ àti gbogbo ọmọ-ogun oníkẹ̀kẹ́ mìíràn ní Ejibiti, olórí sì wà fún olúkúlùkù wọn.
A takiritia ake e ia e ono rau hariata, whiriwhiri rawa, me nga hariata katoa o Ihipa, rite katoa i te rangatira.
8 Olúwa sé ọkàn Farao ọba Ejibiti le, ó sì bẹ̀rẹ̀ sí lépa àwọn ọmọ Israẹli ti ń jáde lọ ní àìbẹ̀rù.
Na whakapakeke ana a Ihowa i te ngakau o Parao kingi o Ihipa, ko te tino whainga i muri i nga tama a Iharaira: tena ko nga tama a Iharaira, kei runga tonu te ringaringa i haere atu ai ratou.
9 Àwọn ará Ejibiti ń lépa wọn pẹ̀lú gbogbo ẹṣin kẹ̀kẹ́ ogun Farao àti àwọn ẹlẹ́ṣin rẹ̀, wọ́n sì lé wọn bá ni ibi tí wọ́n pa àgọ́ sí lẹ́bàá òkun ní ìhà Pi-Hahirotu, ni òdìkejì Baali-Ṣefoni.
Na whai ana nga Ihipiana i a ratou, nga hoiho katoa, nga hariata a Parao, me ana hoia eke hoiho, me ana mano, a mau rawa ratou, i a ratou e noho ana i te tahatai, i Pihahirota, e titiro atu nei ki Paarahepona.
10 Bí Farao ti súnmọ́ tòsí ọ̀dọ̀ wọn, àwọn ọmọ Israẹli gbé ojú wọn sókè, wọn sì rí àwọn ará Ejibiti tó súnmọ́ wọn. Ẹ̀rù ńlá sì bá àwọn ará Israẹli, wọ́n kígbe sókè sí Olúwa.
A, i te whakatatanga mai o Parao, na ka anga ake nga kanohi o nga tama a Iharaira, na, ko nga Ihipiana e whai ana i muri i a ratou; a tino wehi ana ratou: na ka karanga nga tama a Iharaira ki a Ihowa.
11 Wọ́n sọ fún Mose pé, “Ṣe nítorí pé kò sí ibojì ni Ejibiti ní ìwọ ṣe mú wa wá láti kú sínú aginjù? Kí ni èyí tí ìwọ ṣe sí wa ti ìwọ fi mú wa jáde láti Ejibiti wá?
A ka mea ratou ki a Mohi, He onge koia no te urupa o Ihipa i kahaki mai ai koe i a matou ki te koraha mate ai? He aha ra tenei mahi au ki a matou, i arahina mai ai matou e koe i Ihipa?
12 Ǹjẹ́ èyí kọ́ ni àwa sọ fún ọ ni Ejibiti, ‘Fi wá sílẹ̀, jẹ́ kí àwa máa sin ará Ejibiti’? Nítorí kò bá sàn fún wa kí a sin àwọn ará Ejibiti ju kí a kú sínú aginjù yìí lọ!”
Ehara koia tenei i ta matou kupu i ki ra ki a koe i Ihipa, i mea ra, Waiho ra matou kia whakamahia ana e nga Ihipiana? Pai ke kia whakamahia matou e nga Ihipiana i to matou mate ki te koraha.
13 Nígbà náà ni Mose sọ fún àwọn ènìyàn náà pé, “Ẹ má bẹ̀rù, ẹ dúró ṣinṣin kí ẹ sì rí ìdáǹdè tí Olúwa yóò fi fún un yín lónìí, àwọn ará Ejibiti ti ẹ̀yin rí lónìí ni ẹ kò ni tún padà rí wọn mọ́.
Na ka mea a Mohi ki te iwi, Kaua e wehi; tu marie, ka titiro atu ki te whakaoranga a Ihowa e whakaputaina mai e ia ki a koutou i tenei ra: no ko nga Ihipiana e kitea atu ra e koutou i tenei ra, e kore e kitea ano e koutou a muri ake nei.
14 Olúwa yóò jà fún un yín; kí ẹ̀yin kí ó sá à mu sùúrù.”
Ma Ihowa ta koutou pakanga; ko koutou ia e kore e hamumu.
15 Nígbà náà ni Olúwa sọ fún Mose pé, “Èéṣe tí ìwọ fi ń ké pè mí? Sọ fún àwọn ará Israẹli kí wọn máa tẹ̀síwájú.
Na ka mea a Ihowa ki a Mohi, He aha koe i karanga ai ki ahau? Ki atu ki nga tama a Iharaira kia maro te haere:
16 Ṣùgbọ́n, gbé ọ̀pá rẹ̀ sókè, kí o sì na ọwọ́ rẹ sí orí omi Òkun, kí ó lè pín ní yà kí àwọn ọmọ Israẹli lè la òkun kọjá ni orí ìyàngbẹ ilẹ̀.
Na hapainga e koe tau tokotoko, ka whakamaro atu ai i tou ringa ki runga ake i te moana, kia wehea ai; na ka haere atu nga tama a Iharaira ma waenga moana, i te wahi maroke.
17 Nígbà náà ni èmi yóò sé ọkàn àwọn ará Ejibiti le, wọn yóò sì máa lépa wọn; Èmi yóò gba ògo fún ara mi lórí Farao; lórí gbogbo ogun rẹ̀, lórí kẹ̀kẹ́ ogun àti lórí àwọn ẹlẹ́ṣin rẹ̀.
A ko ahau, ina, maku e whakapakeke nga ngakau o nga Ihipiana, a ka whai ratou i muri i a ratou: a ka whai kororia ahau i a Parao, i ana mano, i ana hariata, i ana hoia eke hoiho.
18 Àwọn ará Ejibiti yóò mọ̀ pé Èmi ni Olúwa nígbà ti èmi bá gba ògo fún ara mi lórí Farao: lórí kẹ̀kẹ́ ogun rẹ̀ àti lórí àwọn ẹlẹ́ṣin rẹ̀.”
A ka mohio nga Ihipiana ko Ihowa ahau, ina whai kororia ahau i a Parao, i ana hariata, i ana hoia eke hoiho.
19 Nígbà náà ni angẹli Ọlọ́run tó ti ń ṣáájú ogun Israẹli lọ, padà o sì rìn ni ẹ̀yìn wọn; Òpó ìkùùkuu tí ń rìn ni iwájú wọn sì padà sí í rìn ni ẹ̀yìn wọn.
Na ka whakatika te anahera a te Atua, i haere ra i mua i te ope o Iharaira, a haere ana ki muri i a ratou; i neke atu ano te pou kapua i to ratou aroaro, a tu ana i muri i a ratou:
20 Ó sì wà láàrín àwọn ọmọ-ogun Ejibiti àti Israẹli. Ìkùùkuu sì ṣú òkùnkùn sí àwọn ará Ejibiti ni òru náà. Ṣùgbọ́n ó tan ìmọ́lẹ̀ sí àwọn Israẹli ni òru náà, ọ̀kan kò sì súnmọ́ èkejì ni gbogbo òru náà.
I haere hoki ki waenganui o te nohoanga o nga Ihipiana, o te nohoanga hoki o Iharaira; a tera te kapua me te pouri, otiia e whakamarama ana ia i te po: a kihai tetahi i whakatata ki tetahi a pau katoa te po.
21 Nígbà náà ni Mose na ọwọ́ rẹ̀ sí orí Òkun, ni gbogbo òru náà ni Olúwa fi lé òkun sẹ́yìn pẹ̀lú ìjì líle láti ìlà-oòrùn wá, ó sì sọ ọ́ di ìyàngbẹ ilẹ̀. Omi òkun sì pínyà,
Na torona atu ana e Mohi tona ringa ki runga i te moana; a panaia ana ki muri e Ihowa te moana ki tetahi hau nui, ki te marangai, a pau noa taua po, na kua maroke te moana, kua tuwhera nga wai.
22 àwọn ọmọ Israẹli sì la ìyàngbẹ ilẹ̀ kọjá nínú òkun pẹ̀lú ògiri omi ní ọ̀tún àti òsì.
A haere ana nga tama a Iharaira i waenga moana ra te wahi maroke: hei taiepa ano nga wai ki a ratou i te taha ki matau, ki maui.
23 Àwọn ará Ejibiti sì ń lépa wọn, gbogbo ẹṣin Farao, kẹ̀kẹ́ ogun àti àwọn ẹlẹ́ṣin rẹ̀ wọ́ tọ̀ wọ́n lọ sínú òkun.
Na ka whai nga Ihipiana, a haere ana i muri i a ratou, nga hoiho katoa a Parao, ana hariata, me ana hoia eke hoiho, ki waenga moana.
24 Ní ìṣọ́ òwúrọ̀ Olúwa bojú wo ogun àwọn ará Ejibiti láàrín ọ̀wọ̀n iná àti ìkùùkuu, ó sì kó ìpayà bá àwọn ọmọ-ogun Ejibiti.
A, i to te ata whakaaraara, na, ka titiro a Ihowa ki te ope o nga Ihipiana, i roto i te pou ahi, i te pou kapua, ka whakararu hoki i te ope o nga Ihipiana,
25 Ó sì yọ àgbá ẹsẹ̀ kẹ̀kẹ́ ogun wọn kí ó bá à le ṣòro fún wọn láti fi kẹ̀kẹ́ ogun náà rìn. Àwọn ará Ejibiti wí pé, “Ẹ jẹ́ kí a sá àsálà kúrò ní iwájú àwọn ará Israẹli nítorí Olúwa ń bá wa jà nítorí wọn.”
A whakamareretia ana e ia nga wira o nga hariata, kia puhoi ai te haere: a ka mea nga Ihipiana, Kia oma atu tatou i te aroaro o Iharaira: kei a ratou hoki a Ihowa e whawhai mai ana ki nga Ihipiana.
26 Olúwa sì wí fún Mose pé, “Na ọwọ́ rẹ sí orí òkun kí omi òkun lè ya padà sórí àwọn ará Ejibiti, kẹ̀kẹ́ ogun wọn àti sórí ẹlẹ́ṣin wọn.”
Na ka mea a Ihowa ki a Mohi, Whakamarokia tou ringa ki runga i te moana, kia hoki ai nga wai ki runga ki nga Ihipiana, ki a ratou hariata, ki a ratou hoia eke hoiho.
27 Mose sì na ọwọ́ rẹ̀ sí orí òkun, òkun sì padà bọ́ sí ipò rẹ̀ nígbà ti ilẹ̀ mọ́. Àwọn ará Ejibiti ń sá fún omi òkun, Olúwa sì gbá wọn sínú òkun.
A, ko te whakamarokanga o te ringa o Mohi ki runga i te moana, na takiri rawa ake te ata, kua hoki te moana ki tona tuturutanga; tutataki pu ki nga Ihipiana e rere ana; a taia iho nga Ihipiana e Ihowa ki waenga moana.
28 Omi òkun sì ya padà, ó sì bo kẹ̀kẹ́ ogun àti àwọn ẹlẹ́ṣin: àní, gbogbo ọmọ-ogun Farao tiwọn wọ inú òkun tọ àwọn ọmọ Israẹli lọ kò sí ọ̀kan nínú wọn tí ó yè.
A hoki ana nga wai, taupokina iho nga hariata, me nga hoia eke hoiho, me te ope katoa o Parao, i haere i muri i a ratou ki te moana: kihai rawa tetahi o ratou i toe.
29 Ṣùgbọ́n àwọn ará Israẹli la òkun kọjá lórí ìyàngbẹ ilẹ̀ pẹ̀lú ògiri omi ni ọ̀tún àti òsì wọn.
Tena ko nga tama a Iharaira, i haere ratou ra te wahi maroke i waenganui o te moana; ko nga wai hoki hei taiepa ki a ratou, ki te taha matau, ki te taha maui.
30 Ni ọjọ́ yìí ni Olúwa gba Israẹli là kúrò lọ́wọ́ àwọn ará Ejibiti; Israẹli sì rí òkú àwọn ará Ejibiti ni etí òkun.
A, whakaorangia ana e Ihowa a Iharaira i taua ra i nga ringa o nga Ihipiana; a ka kite a Iharaira i nga Ihipiana i te tahatai, he tupapaku katoa.
31 Nígbà ti àwọn ọmọ Israẹli rí iṣẹ́ ìyanu ńlá ti Olúwa ṣe fún wọn lára àwọn ará Ejibiti, àwọn ènìyàn bẹ̀rù Olúwa, wọ́n sì gba Olúwa àti Mose ìránṣẹ́ rẹ gbọ́.
A i kite a Iharaira i te mahi nui i mahia e Ihowa ki nga Ihipiana: a ka wehi te iwi a Ihowa, whakapono ana ki a Ihowa, ki tana pononga hoki, ki a Mohi.

< Exodus 14 >