< Exodus 14 >

1 Olúwa sọ fún Mose pé,
BOEIPA loh Moses te a voek tih,
2 “Sọ fún àwọn ọmọ Israẹli kí wọn padà sẹ́yìn, kí wọ́n sì pàgọ́ sí tòsí Pi-Hahirotu láàrín Migdoli òun Òkun, kí wọn kí ó pàgọ́ sí ẹ̀bá Òkun, ní òdìkejì Baali-Ṣefoni.
Israel ca rhoek te thui pah lamtah mael uh saeh. Te dongah Pihahiroth dan kah Migdol laklo neh Baalzephon dan kah tuipuei laklo ah rhaeh uh saeh. Te kah a dan tuipuei taengah khaw rhaeh uh.
3 Farao yóò ronú pé àwọn ọmọ Israẹli ń ráre káàkiri ní ìdààmú ni àti wí pé aginjù náà ti sé wọn mọ́.
Te vaengah Pharaoh loh, “Israel ca rhoek tah khohmuen ah amamih a lukil uh tih khosoek ah a det,” ti saeh.
4 Èmi yóò sé ọkàn Farao le ti yóò fi lépa wọn. Ṣùgbọ́n èmi yóò gba ògo fún ará mi láti ìpàṣẹ Farao àti ogun rẹ̀, àti pé àwọn ará Ejibiti yóò mọ̀ pé Èmi ni Olúwa.” Àwọn Israẹli sì ṣe bẹ́ẹ̀.
Te vaengah Pharaoh lungbuei te ka moem pah vetih amih te a hloem ni. Tedae Pharaoh neha thadueng cungkuem rhangneh kamah ka thangpom vetih Egypt rhoek loh kai he Yahweh la a ming uh ni,” a ti nah tih a saii uh tangloeng.
5 Nígbà tí wọ́n sọ fún ọba Ejibiti pé àwọn ènìyàn náà ti sálọ, ọkàn Farao àti àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ yí padà sí àwọn ènìyàn, wọ́n sì wí pé, “Kí ni ohun tí àwa ṣe yìí? Àwa ti jẹ́ kí àwọn ọmọ Israẹli kí ó lọ, a sì ti pàdánù ìsìnrú wọn.”
Tedae pilnam yong te Egypt manghai taengla a puen pah vaengah tah Pharaoh neh a sal rhoek loh pilnam taengah thinko a maelh uh tih, “Israel he mamih ham a thotat khui lamloh n'hlah coeng dongah balae n'saii uh he,” a ti uh.
6 Ó sì di kẹ̀kẹ́-ẹṣin rẹ̀, ó sì kó àwọn ọmọ-ogun rẹ̀ pẹ̀lú rẹ̀,
Te dongaha leng te a khih tih amah pilnam te amah taengla a loh.
7 ó mú ẹgbẹ̀ta ọmọ-ogun oníkẹ̀kẹ́ tí ó jáfáfá jùlọ àti gbogbo ọmọ-ogun oníkẹ̀kẹ́ mìíràn ní Ejibiti, olórí sì wà fún olúkúlùkù wọn.
Te phoeiah leng a coelh ya rhuk neh Egypt leng boeiha boeilu boeih te khaw a loh.
8 Olúwa sé ọkàn Farao ọba Ejibiti le, ó sì bẹ̀rẹ̀ sí lépa àwọn ọmọ Israẹli ti ń jáde lọ ní àìbẹ̀rù.
BOEIPA loh Egypt manghai Pharaoh kah lungbuei te a moem pah dongah Israel ca rhoek te a hloem. Tedae Israel ca rhoek kut thoh nen ni a khong uh.
9 Àwọn ará Ejibiti ń lépa wọn pẹ̀lú gbogbo ẹṣin kẹ̀kẹ́ ogun Farao àti àwọn ẹlẹ́ṣin rẹ̀, wọ́n sì lé wọn bá ni ibi tí wọ́n pa àgọ́ sí lẹ́bàá òkun ní ìhà Pi-Hahirotu, ni òdìkejì Baali-Ṣefoni.
Amih hnuk te Egypt rhoek loh a hloem uh tangloeng tih tuipuei taengah a rhaeh vaengah amih te a kae uh. Pharaoh kah marhang leng boeih neha marhang caem khaw, anih kah caem khaw, Baalzephon dan kah Pihahiroth la pawk.
10 Bí Farao ti súnmọ́ tòsí ọ̀dọ̀ wọn, àwọn ọmọ Israẹli gbé ojú wọn sókè, wọn sì rí àwọn ará Ejibiti tó súnmọ́ wọn. Ẹ̀rù ńlá sì bá àwọn ará Israẹli, wọ́n kígbe sókè sí Olúwa.
Pharaoh loh a paan vaengah Israel ca rhoek loh a mik te a huel uh. Egypt rhoek te a hnukah tarha a caeh pah vaengah tah bahoeng a rhih dongah Israel ca rhoek te BOEIPA taengah pang uh.
11 Wọ́n sọ fún Mose pé, “Ṣe nítorí pé kò sí ibojì ni Ejibiti ní ìwọ ṣe mú wa wá láti kú sínú aginjù? Kí ni èyí tí ìwọ ṣe sí wa ti ìwọ fi mú wa jáde láti Ejibiti wá?
Moses taengah khaw, “Egypt ah phuel om voel pawt tih nim khosoek ah duek sak ham kaimih nang khuen, Egypt lamloh kaimih nang khuen neh kaimih ham banim na saii he?
12 Ǹjẹ́ èyí kọ́ ni àwa sọ fún ọ ni Ejibiti, ‘Fi wá sílẹ̀, jẹ́ kí àwa máa sin ará Ejibiti’? Nítorí kò bá sàn fún wa kí a sin àwọn ará Ejibiti ju kí a kú sínú aginjù yìí lọ!”
Egypt ah nang hma kan thui uh te ol pawt nim. Kaimih he tamah laeh saeh ka ti. Egypt taengah thotat palueng sih, khosoek kah duek lakah Egypt taengah thohtat he kaimih ham then ngai,” a ti uh.
13 Nígbà náà ni Mose sọ fún àwọn ènìyàn náà pé, “Ẹ má bẹ̀rù, ẹ dúró ṣinṣin kí ẹ sì rí ìdáǹdè tí Olúwa yóò fi fún un yín lónìí, àwọn ará Ejibiti ti ẹ̀yin rí lónìí ni ẹ kò ni tún padà rí wọn mọ́.
Tedae Moses loh pilnam te, “Rhih uh boeh, pai uh lamtah hmu uh. BOEIPA kah khangnah nangmih ham tihnin ah a saii bitni. Tihnin kah na hmuh Egypt rhoek he koep hmuh ham kumhal duela na khoep uh voel mahpawh.
14 Olúwa yóò jà fún un yín; kí ẹ̀yin kí ó sá à mu sùúrù.”
BOEIPA loh nangmih ham a vathoh bitni, nangmih duem om uh,” a ti nah.
15 Nígbà náà ni Olúwa sọ fún Mose pé, “Èéṣe tí ìwọ fi ń ké pè mí? Sọ fún àwọn ará Israẹli kí wọn máa tẹ̀síwájú.
Te dongah BOEIPA loh Moses te, “Balae tih kai taengah na pang, Israel ca rhoek te thui pah lamtah ana cet uh saeh.
16 Ṣùgbọ́n, gbé ọ̀pá rẹ̀ sókè, kí o sì na ọwọ́ rẹ sí orí omi Òkun, kí ó lè pín ní yà kí àwọn ọmọ Israẹli lè la òkun kọjá ni orí ìyàngbẹ ilẹ̀.
Nang te na conghol thoh lamtah tuipuei soah na kut thueng laeh. Tuipuei te a phih daengah ni Israel ca te tuipuei khui kah laiphuei dongah a caeh uh eh.
17 Nígbà náà ni èmi yóò sé ọkàn àwọn ará Ejibiti le, wọn yóò sì máa lépa wọn; Èmi yóò gba ògo fún ara mi lórí Farao; lórí gbogbo ogun rẹ̀, lórí kẹ̀kẹ́ ogun àti lórí àwọn ẹlẹ́ṣin rẹ̀.
Kai kamah long ni Egypt lungbuei te ka moem pah. Amih te a hloem vaengah ni Pharaoh so neha caem boeih so lamloh, a leng so neha marhang caem so lamloh kamah ka thangpom uh eh.
18 Àwọn ará Ejibiti yóò mọ̀ pé Èmi ni Olúwa nígbà ti èmi bá gba ògo fún ara mi lórí Farao: lórí kẹ̀kẹ́ ogun rẹ̀ àti lórí àwọn ẹlẹ́ṣin rẹ̀.”
Pharaoh so neh a leng soaha marhang caem soah kamah ka thangpom uh vaengah kai Yahweh he Egypt loh a ming bitni,” a ti nah.
19 Nígbà náà ni angẹli Ọlọ́run tó ti ń ṣáájú ogun Israẹli lọ, padà o sì rìn ni ẹ̀yìn wọn; Òpó ìkùùkuu tí ń rìn ni iwájú wọn sì padà sí í rìn ni ẹ̀yìn wọn.
Te phoeiah Israel lambong hmai ah aka cet Pathen puencawn khoe uh tih amih hnuk la cet. Cingmai tung khaw amih hmai lamloh thoeih tih amih hnuk ah pai.
20 Ó sì wà láàrín àwọn ọmọ-ogun Ejibiti àti Israẹli. Ìkùùkuu sì ṣú òkùnkùn sí àwọn ará Ejibiti ni òru náà. Ṣùgbọ́n ó tan ìmọ́lẹ̀ sí àwọn Israẹli ni òru náà, ọ̀kan kò sì súnmọ́ èkejì ni gbogbo òru náà.
Te vaengah Egypt lambong laklo neh Israel lambong laklo la pawk. Cingmai khaw a hmuep la om dae khoyin ah sae. Te dongah khoyin khing a taengla pha thai pawh.
21 Nígbà náà ni Mose na ọwọ́ rẹ̀ sí orí Òkun, ni gbogbo òru náà ni Olúwa fi lé òkun sẹ́yìn pẹ̀lú ìjì líle láti ìlà-oòrùn wá, ó sì sọ ọ́ di ìyàngbẹ ilẹ̀. Omi òkun sì pínyà,
Te vaengah Moses loh a kut te tuipuei soah a thueng tih BOEIPA loh tuipuei te khoyin puet khothoeng yilh tlung neh a yah pah. Te dongah tuipuei te lanhak la poeh tih tui te phik uh.
22 àwọn ọmọ Israẹli sì la ìyàngbẹ ilẹ̀ kọjá nínú òkun pẹ̀lú ògiri omi ní ọ̀tún àti òsì.
Te vaengah Israel ca rhoek te tuipuei laklung kah laiphuei dongah cet uh tih tui khaw amih ham a banvoei neh a bantang ah vongtung la a om pah.
23 Àwọn ará Ejibiti sì ń lépa wọn, gbogbo ẹṣin Farao, kẹ̀kẹ́ ogun àti àwọn ẹlẹ́ṣin rẹ̀ wọ́ tọ̀ wọ́n lọ sínú òkun.
Egypt rhoek a hloem uh vaengah Pharaoh kah marhang leng boeih neha marhang caem khaw amih hnukah tuipuei tuilung la kun uh.
24 Ní ìṣọ́ òwúrọ̀ Olúwa bojú wo ogun àwọn ará Ejibiti láàrín ọ̀wọ̀n iná àti ìkùùkuu, ó sì kó ìpayà bá àwọn ọmọ-ogun Ejibiti.
Mincang khopo a pha vaengah BOEIPA loh hmai tung neh cingmai dong lamloh Egypt lambong te a dan tih Egypt lambong te a khawkkhek.
25 Ó sì yọ àgbá ẹsẹ̀ kẹ̀kẹ́ ogun wọn kí ó bá à le ṣòro fún wọn láti fi kẹ̀kẹ́ ogun náà rìn. Àwọn ará Ejibiti wí pé, “Ẹ jẹ́ kí a sá àsálà kúrò ní iwájú àwọn ará Israẹli nítorí Olúwa ń bá wa jà nítorí wọn.”
A leng dongkah lengkho te a tling pah tih hnorhih laa hmaithawn. Te dongah Egypt loh, “Israel mikhmuh lamloh rhaelrham pawn sih, BOEIPA loh amih ham Egypt a vathoh thil,” a ti.
26 Olúwa sì wí fún Mose pé, “Na ọwọ́ rẹ sí orí òkun kí omi òkun lè ya padà sórí àwọn ará Ejibiti, kẹ̀kẹ́ ogun wọn àti sórí ẹlẹ́ṣin wọn.”
Te vaengah BOEIPA loh Moses te, “Tuipuei soah na kut te thueng lamtah tui loh Egypt neh a leng neha marhang caem soah et saeh,” a ti nah.
27 Mose sì na ọwọ́ rẹ̀ sí orí òkun, òkun sì padà bọ́ sí ipò rẹ̀ nígbà ti ilẹ̀ mọ́. Àwọn ará Ejibiti ń sá fún omi òkun, Olúwa sì gbá wọn sínú òkun.
Moses loh a kut te tuipuei soah a thueng tangloeng tih mincang vikvak ah tuipuei khaw amah thim la mael. Te long te amah coeng dongah Egypt rhoek khaw rhaelrham uh dae BOEIPA loh Egypt rhoek te tuipuei khui la a khoek.
28 Omi òkun sì ya padà, ó sì bo kẹ̀kẹ́ ogun àti àwọn ẹlẹ́ṣin: àní, gbogbo ọmọ-ogun Farao tiwọn wọ inú òkun tọ àwọn ọmọ Israẹli lọ kò sí ọ̀kan nínú wọn tí ó yè.
Tui a mael vaengah leng neh marhang caem te a et pah. Amih hnuk ah tuipuei la aka pawk Pharaoh caem boeih te pakhat pataeng sueng pawh.
29 Ṣùgbọ́n àwọn ará Israẹli la òkun kọjá lórí ìyàngbẹ ilẹ̀ pẹ̀lú ògiri omi ni ọ̀tún àti òsì wọn.
Tedae Israel ca rhoek tah tuipuei tuilung kah laiphuei dongah cet uh tih tui te amih kah a banvoei, a bantang ah vongtung la pah.
30 Ni ọjọ́ yìí ni Olúwa gba Israẹli là kúrò lọ́wọ́ àwọn ará Ejibiti; Israẹli sì rí òkú àwọn ará Ejibiti ni etí òkun.
Tekah khohnin ah BOEIPA loh Israel te Egypt kut lamkah a khang tangloeng tih Israel loh tuipuei tuikaeng ah Egypt a duek te a hmuh.
31 Nígbà ti àwọn ọmọ Israẹli rí iṣẹ́ ìyanu ńlá ti Olúwa ṣe fún wọn lára àwọn ará Ejibiti, àwọn ènìyàn bẹ̀rù Olúwa, wọ́n sì gba Olúwa àti Mose ìránṣẹ́ rẹ gbọ́.
BOEIPA tanglue kut neh Egypt soah a saii te Israel loh a hmuh. Te daengah pilnam loh BOEIPA te a rhih tih BOEIPA neha sal Moses te a tangnah uh.

< Exodus 14 >