< Exodus 13 >

1 Olúwa sọ fún Mose pé,
Nake Jehova akĩĩra Musa atĩrĩ,
2 “Ẹ ya àwọn àkọ́bí yín ọkùnrin sọ́tọ̀ fún mi. Èyí ti ó bá jẹ́ àkọ́bí láàrín àwọn ọmọ Israẹli jẹ́ tèmi, ìbá à ṣe ènìyàn tàbí ẹranko.”
“Nyamũrĩra marigithathi mothe ma twana twa tũhĩĩ. Maciaro ma mbere ma nda o yothe gatagatĩ-inĩ ka andũ a Isiraeli nĩ makwa, marĩ ma mũndũ kana ma nyamũ.”
3 Nígbà náà ni Mose sọ fún àwọn ènìyàn náà pé, “Ẹ rántí ọjọ́ òní, ọjọ́ ti ẹ jáde kúrò ni ilẹ̀ Ejibiti, kúrò ní ilẹ̀ tí ẹ̀yin ti ń ṣe ẹrú, nítorí Olúwa mú un yín jáde kúrò ni inú rẹ̀ pẹ̀lú ọwọ́ agbára. Ẹ má ṣe jẹ ohunkóhun tí ó ni ìwúkàrà nínú.
Nake Musa akĩĩra andũ atĩrĩ, “Ririkanagai mũthenya ũyũ, mũthenya ũrĩa mwoimire bũrũri wa Misiri, mũkiuma bũrũri wa ũkombo, tondũ Jehova nĩamũrutire kuo na guoko kwa hinya. Mũtikarĩĩage kĩndũ kĩrĩ na ndawa ya kũimbia.
4 Òní, ní oṣù Abibu (oṣù kẹta ọdún tiwa) lónìí ẹ̀yin ń jáde kúrò ní Ejibiti.
Ũmũthĩ, mweri-inĩ ũyũ wa Abibu, nĩguo mũroimagara mũthiĩ.
5 Ní ìgbà tí Olúwa mú un yín jáde wá sí ilẹ̀ Kenaani, Hiti, Amori, Hifi àti ilẹ̀ àwọn Jebusi; ilẹ̀ tí ó ti ṣe búra láti fi fún àwọn baba ńlá yín, ilẹ̀ tí ó ń sàn fún wàrà àti oyin, ẹ ni láti pa ìsìn yìí mọ́ ní oṣù yìí.
Rĩrĩa Jehova akaamũkinyia bũrũri wa Akaanani, na Ahiti, na Aamori, na Ahivi, na Ajebusi bũrũri ũrĩa eehĩtire mbere ya maithe manyu ma tene atĩ nĩakamũhe bũrũri ũrĩ bũthi wa iria na ũũkĩ-rĩ, mũkaamenyagĩrĩra gĩathĩ gĩkĩ mweri-inĩ ũyũ:
6 Fún ọjọ́ méje ni ìwọ yóò fi jẹ àkàrà tí kò ní ìwúkàrà nínú àti pé ní ọjọ́ keje ni àjọ yóò wà fún Olúwa.
Ihinda rĩa mĩthenya mũgwanja mũkaarĩĩaga mĩgate ĩtarĩ mĩĩkĩre ndawa ya kũimbia na mũthenya wa mũgwanja mũthondeke iruga inene nĩ ũndũ wa Jehova.
7 Kí ẹ̀yin ó jẹ àkàrà tí kò ní ìwúkàrà fún ọjọ́ méje yìí; kó má ṣe sí ohunkóhun tí a fi ìwúkàrà ṣe ní sàkání yín.
Rĩĩagai mĩgate ĩtarĩ mĩĩkĩre ndawa ya kũimbia ihinda rĩa mĩthenya ĩyo mũgwanja; gũtikoneke kĩndũ kĩrĩ na ndawa ya kũimbia gatagatĩ kanyu, kana ndawa ya kũimbia yoneke handũ o hothe mĩhaka-inĩ yanyu.
8 Ní ọjọ́ náà, ìwọ yóò sì sọ fún àwọn ọmọ rẹ ọkùnrin, ‘Mo ń ṣe èyí nítorí ohun tí Olúwa ṣe fún mi nígbà tí èmi jáde kúrò ni ilẹ̀ Ejibiti.’
Mũthenya ũcio o mũndũ ere mũriũ atĩrĩ, ‘Ndĩreka ũũ tondũ wa ũrĩa Jehova aanjĩkĩire rĩrĩa ndoimire bũrũri wa Misiri.’
9 Ṣíṣe èyí yóò wà fún àmì ní ọwọ́ rẹ, àti bí àmì ìrántí ni iwájú orí rẹ, tí yóò máa rán ọ létí òfin Olúwa ní ẹnu rẹ. Nítorí Olúwa mú ọ jáde láti ilẹ̀ Ejibiti pẹ̀lú ọwọ́ agbára ńlá rẹ̀.
Kũmenyerera mũthenya ũyũ nĩkuo kũrĩtuĩkaga ta rũũri guoko-inĩ gwaku, na kĩririkania ũthiũ-inĩ waku, atĩ watho wa Jehova nĩũrĩikaraga iromo-inĩ ciaku. Nĩgũkorwo Jehova nĩakũrutire bũrũri wa Misiri na guoko gwake kwa hinya.
10 Ìwọ gbọdọ̀ pa òfin náà mọ́ ní àkókò tí a yàn bí ọdún tí ń gorí ọdún.
No nginya mũrũmie watho ũyũ mwathane ihinda rĩaguo rĩakinya, mwaka o mwaka.
11 “Lẹ́yìn tí Olúwa tí mú ọ wá sí ilẹ̀ àwọn ará Kenaani tí ó sì fi fún ọ gẹ́gẹ́ bí òun ti ṣe ìlérí pẹ̀lú ìbúra fún ọ àti fún àwọn baba ńlá rẹ̀,
“Thuutha wa Jehova kũmũkinyia bũrũri wa Akaanani na amũhe guo, o ta ũrĩa eeranĩire na mwĩhĩtwa kũrĩ inyuĩ o na maithe manyu ma tene-rĩ,
12 ìwọ yóò fi àkọ́bí inú rẹ fún Olúwa. Gbogbo àkọ́bí ti ó jẹ́ akọ ti ẹran ọ̀sìn rẹ ní ó jẹ́ ti Olúwa.
nĩmũkahe Jehova maciaro ma mbere ma nda ciothe. Marigithathi ma njamba mothe ma ũhiũ wanyu nĩ ma Jehova.
13 Ìwọ yóò fi ọ̀dọ́-àgùntàn ra àkọ́bí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ padà, ṣùgbọ́n bí ìwọ kò bá rà á padà, ǹjẹ́ kí ìwọ ṣẹ́ ẹ ní ọrùn, gbogbo àkọ́bí ọkùnrin ni kí ìwọ kí ó rà padà.
Mũgaakũũraga irigithathi o rĩothe rĩa ndigiri na gatũrũme, no mũngĩaga kũrĩkũũra-rĩ, mũriune ngingo. Kũũragai marigithathi mothe manyu ma aanake.
14 “Yóò sí ṣe ní àwọn ọjọ́ tí ń bọ̀, ní ìgbà tí àwọn ọmọ yín yóò béèrè lọ́wọ́ yín, ‘Kí ni èyí túmọ̀ sí?’ Kí ìwọ kí ó sọ fún wọn pé, ‘Pẹ̀lú ọwọ́ agbára ní Olúwa fi mú wa jáde kúrò ni ilẹ̀ Ejibiti, kúrò ní oko ẹrú.
“Matukũ-inĩ marĩa magooka, rĩrĩa mũrũguo agaakũũria atĩrĩ, ‘Ũũ nĩ kuuga atĩa?’ mwĩre atĩrĩ, ‘Jehova aatũrutire bũrũri wa Misiri, agĩtũruta bũrũri wa ũkombo, na guoko gwake kwa hinya.
15 Ní ìgbà ti Farao ṣe orí kunkun, ti ó kọ̀ láti jẹ́ kí a lọ, Olúwa pa gbogbo àwọn àkọ́bí ilẹ̀ Ejibiti, àti ènìyàn àti ẹranko. Ìdí èyí ni àwa fi ń fi gbogbo àkọ́bí tí í ṣe akọ rú ẹbọ sí Olúwa láti fi ṣe ìràpadà fún àwọn àkọ́bí wa ọkùnrin.’
Rĩrĩa Firaũni omirie mũtwe akĩrega gũtũrekereria-rĩ, Jehova nĩooragire marigithathi ma bũrũri wa Misiri mothe, andũ o na nyamũ. Ũndũ ũcio nĩguo ũtũmaga ndutĩre Jehova igongona rĩa njamba ciothe iria ciambaga kuuma nda, na ngakũũra mũriũ wakwa wothe wa irigithathi.
16 Èyí yóò sì jẹ́ àmì ni ọwọ́ yín àti àmì ní iwájú orí yín pé Olúwa mú wa jáde láti ilẹ̀ Ejibiti wá pẹ̀lú ọwọ́ agbára ńlá.”
Naguo ũndũ ũcio ũrĩtuĩkaga ta rũũri guoko-inĩ gwaku, o na ũtuĩkage kĩonania gĩĩkĩrĩtwo ũthiũ-inĩ waku, atĩ Jehova nĩatũrutire bũrũri wa Misiri na guoko gwake kwa hinya.’”
17 Ní ìgbà tí Farao jẹ́ kí àwọn ènìyàn ó lọ, Ọlọ́run kò mú wọn tọ ojú ọ̀nà ti ó la orílẹ̀-èdè àwọn Filistini kọjá, bí o tilẹ̀ jẹ́ pé ọ̀nà náà kúrú. Nítorí Ọlọ́run sọ pé, “Bí wọ́n bá dojúkọ ogun, wọ́n lè yí ọkàn wọn padà kí wọ́n padà sí ilẹ̀ Ejibiti.”
Rĩrĩa Firaũni aarekereirie andũ a Isiraeli mathiĩ-rĩ, Ngai ndaamatongoreirie njĩra-inĩ ya kũhĩtũkĩra bũrũri wa Afilisti, o na gũtuĩka ĩyo nĩyo yarĩ njĩra ĩrĩa nguhĩ. Nĩgũkorwo Ngai oigire atĩrĩ, “Mangĩcemania na mbaara-rĩ, maahota kwĩricũkwo, macooke bũrũri wa Misiri.”
18 Nítorí náà Ọlọ́run darí àwọn ènìyàn rọkọ gba ọ̀nà aginjù ní apá Òkun Pupa. Àwọn ọmọ Israẹli jáde kúrò ní ilẹ̀ Ejibiti pẹ̀lú ìmúra fún ogun.
Nĩ ũndũ ũcio Ngai agĩgĩtongoria andũ acio mathiũrũrũkĩire njĩra ya werũ-inĩ merekeire Iria Itune. Andũ a Isiraeli maambatire makiuma bũrũri wa Misiri meeohete indo cia mbaara.
19 Mose kó egungun Josẹfu pẹ̀lú rẹ̀ nítorí Josẹfu tí mú kí àwọn ọmọ Israẹli búra. Ó ti wí pé, “Dájúdájú Ọlọ́run yóò dìde fún ìrànlọ́wọ́ yín ẹ sì gbọdọ̀ kó egungun mi lọ pẹ̀lú yín kúrò níhìn-ín yìí.”
Musa nĩakuuire mahĩndĩ ma Jusufu, nĩ ũndũ Jusufu nĩehĩtithĩtie ariũ a Isiraeli na mwĩhĩtwa. Oigĩte atĩrĩ, “Ti-itherũ Ngai nĩakamũteithia, na inyuĩ hĩndĩ ĩyo no nginya mũgaakuua mahĩndĩ makwa kuuma kũndũ gũkũ.”
20 Wọ́n sì mú ọ̀nà wọn pọ̀n láti Sukkoti lọ, wọ́n sì pàgọ́ sí Etamu ní etí aginjù.
Thuutha wa kuuma Sukothu maambire kambĩ ciao Ethamu ndeere-inĩ cia werũ.
21 Olúwa sì ń lọ níwájú wọn, nínú ọ̀wọ̀n ìkùùkuu ní ọ̀sán láti máa ṣe amọ̀nà wọn àti ní òru nínú ọ̀wọ̀n iná láti máa tan ìmọ́lẹ̀ fún wọn, kí wọn lè máa lọ nínú ìrìnàjò wọn ní tọ̀sán tòru.
Mũthenya, Jehova aathiiaga mbere yao arĩ gĩtugĩ-inĩ gĩa itu gĩa kũmoonereria njĩra, na ũtukũ-rĩ, aathiiaga mbere yao arĩ gĩtugĩ-inĩ kĩa mwaki amamũrĩkĩire njĩra, nĩgeetha mahote gũthiĩ mũthenya o na ũtukũ.
22 Ìkùùkuu náà kò kúrò ní ààyè rẹ̀ ní ọ̀sán, bẹ́ẹ̀ ni, ọ̀wọ̀n iná kò kúrò ní ààyè rẹ̀ ni òru, ní iwájú àwọn ènìyàn náà.
Gĩtugĩ gĩa itu mũthenya kana gĩtugĩ kĩa mwaki ũtukũ, gũtirĩ kĩeheraga handũ hakĩo mbere ya andũ acio.

< Exodus 13 >