< Exodus 10 >
1 Nígbà náà ni Olúwa sọ fún Mose pé, “Lọ sí ọ̀dọ̀ Farao, mo ti ṣé àyà Farao le àti àyà àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀, kí èmi kí o ba le ṣe àwọn iṣẹ́ ìyanu mi láàrín wọn.
Ningĩ Jehova akĩĩra Musa atĩrĩ, “Thiĩ kũrĩ Firaũni, nĩgũkorwo nĩnyũmĩtie ngoro yake na ngoro cia anene ake nĩgeetha ninge ciama ici ciakwa gatagatĩ-inĩ kao;
2 Kí ẹ̀yin ki ó le sọ fún àwọn ọmọ yín àti àwọn ọmọ ọmọ yín; bí mo ti jẹ àwọn ará Ejibiti ní yà àti bí mo ti ṣe àwọn iṣẹ́ ìyanu láàrín wọn. Kí ìwọ ba á le mọ̀ pé Èmi ni Olúwa.”
nĩguo mũkeeraga ciana cianyu na ciana ciacio ũrĩa ndokĩrĩire andũ a Misiri, na ũrĩa ndaringire ciama ciakwa gatagatĩ-inĩ kao, nĩguo mũmenye atĩ niĩ nĩ niĩ Jehova.”
3 Nígbà náà ni Mose àti Aaroni tọ Farao lọ, tiwọn sí wí fún un pé, “Èyí ni Olúwa, Ọlọ́run àwọn Heberu sọ, ‘Yóò ti pẹ́ to ti ìwọ yóò kọ̀ láti tẹrí ara rẹ ba ní iwájú mi? Jẹ́ kí àwọn ènìyàn mi kí ó lọ, kí wọn kí ó sìn mi.
Nĩ ũndũ ũcio Musa na Harũni magĩthiĩ kũrĩ Firaũni makĩmwĩra atĩrĩ, “Jehova Ngai wa Ahibirania ekuuga ũũ: ‘Ũgũikara nginya rĩ ũregete kũnjĩnyiihĩria? Rekereria andũ akwa mathiĩ, nĩgeetha makandungatĩre.
4 Bí ìwọ bá kọ̀ láti jẹ́ kí wọn lọ, èmi yóò mú eṣú wa sí orílẹ̀-èdè rẹ ní ọ̀la.
Warega kũmarekereria-rĩ, rũciũ nĩngarehithia ngigĩ bũrũri ũyũ wanyu.
5 Wọn yóò bo gbogbo ilẹ̀. Wọn yóò ba ohun gbogbo tí ó kù fún ọ lẹ́yìn òjò yìnyín jẹ́, tí ó fi dórí gbogbo igi tí ó ń dàgbà ni ilẹ̀ rẹ.
Ikaiyũra thĩ, imĩhumbĩre yage kuoneka. Nĩikarĩa kĩrĩa gĩothe gĩtigĩtio nĩ mbura ya mbembe, o na irĩe mĩtĩ yothe ĩrĩa ĩrakũra mĩgũnda-inĩ yanyu.
6 Wọn yóò kún gbogbo ilé rẹ àti ilé àwọn ìjòyè rẹ àti ilé gbogbo àwọn ará Ejibiti. Ohun ti baba rẹ tàbí baba baba rẹ kò tí ì rí láti ìgbà tí wọ́n ti wà ní ilẹ̀ náà títí di àkókò yìí.’” Nígbà náà ni Mose pẹ̀yìndà kúrò níwájú Farao.
Ikaiyũra nyũmba ciaku, na cia anene aku, na cia andũ othe a Misiri, ũndũ maithe manyu kana maguuka manyu matarĩ mona kuuma rĩrĩa mambĩrĩirie gũtũũra bũrũri ũyũ nginya rĩu.’” Nake Musa akĩgarũrũka akĩeherera Firaũni.
7 Àwọn ìjòyè Farao sọ fún un, “Yóò ti pẹ́ to tí ọkùnrin yìí yóò máa jẹ́ ìkẹ́kùn fún wa? Jẹ́ kí àwọn ènìyàn yìí lọ, kí wọn kí ó le sìn Olúwa Ọlọ́run wọn. Ṣe ìwọ kò ṣe àkíyèsí síbẹ̀ pé, ilẹ̀ Ejibiti ti parun tán?”
Anene a Firaũni makĩmwĩra atĩrĩ, “Nĩ nginya rĩ mũndũ ũyũ egũtũũra arĩ mũtego harĩ ithuĩ? Rekereria andũ aya mathiĩ, nĩgeetha makahooe Jehova Ngai wao. Ndũramenya atĩ bũrũri wa Misiri nĩwanangĩtwo?”
8 Nígbà náà ni a mú Aaroni àti Mose padà wá sí iwájú Farao ó sì wí fún wọn pé, “Ẹ lọ sìn Olúwa Ọlọ́run yín. Ṣùgbọ́n àwọn ta ni nínú yín ni yóò ha lọ.”
Musa na Harũni magĩcookio kũrĩ Firaũni. Nake akĩmeera atĩrĩ, “Thiĩi mũkahooe Jehova Ngai wanyu; no rĩrĩ, nĩ arĩkũ megũthiĩ?”
9 Mose dáhùn ó wí pé, “A ó lọ pẹ̀lú àwọn ọmọdé àti àgbà wa, pẹ̀lú àwọn ọmọ wa ọkùnrin àti ọmọ wa obìnrin pẹ̀lú agbo àgùntàn wa àti agbo màlúù wa nítorí pé a gbọdọ̀ ṣe àjọ fún Olúwa.”
Musa akĩmũcookeria atĩrĩ, “Tũgũthiĩ na andũ aitũ arĩa ethĩ o na arĩa akũrũ, tũthiĩ na aanake na airĩtu aitũ, na tũthiĩ na ũhiũ witũ wothe, tondũ tũrathiĩ gũkũngũĩra Jehova na iruga inene.”
10 Farao sì wí pé, “Mo fi Olúwa búra pé èmi kí yóò jẹ́ kí ẹ lọ, pẹ̀lú àwọn obìnrin yín àti àwọn ọmọ wẹ́wẹ́, dájúdájú èrò ibi ní ń bẹ nínú yín.
Firaũni akiuga atĩrĩ, “Hĩ! Kaĩ Jehova arogĩikara na inyuĩ ingĩmũrekereria mũthiĩ na atumia anyu na ciana cianyu-ĩ! Hatirĩ nganja mũrĩ na muoroto mũũru.
11 Rárá! Ọkùnrin yín nìkan ni kí ó lọ, láti lọ sin Olúwa, níwọ̀n ìgbà tí ó jẹ́ pé èyí ni ẹ̀yin ń béèrè fún.” Wọ́n sì lé Mose àti Aaroni kúrò ní iwájú Farao.
Aca! Thiĩi o arũme oiki, mũthiĩ mũhooe Jehova, nĩgũkorwo ũguo nĩguo mũkoretwo mũkĩenda.” Nao Musa na Harũni makĩingatwo, makĩehera mbere ya Firaũni.
12 Ní ìgbà náà ni Olúwa sọ fún Mose, “Gbé ọwọ́ rẹ sókè lórí Ejibiti kí ọ̀pọ̀lọpọ̀ eṣú bo gbogbo ilẹ̀, kí ó sì ba gbogbo ohun ọ̀gbìn tí ó wà ni inú oko wọn jẹ́, àní gbogbo ohun tí òjò yìnyín kò bàjẹ́ tan.”
Nake Jehova akĩĩra Musa atĩrĩ, “Tambũrũkia guoko gwaku igũrũ rĩa bũrũri wa Misiri nĩgeetha ngigĩ ciũke ciyũre bũrũri ũyũ wothe, nacio irĩe kĩndũ gĩothe kĩrakũra mĩgũnda-inĩ, kĩrĩa gĩothe gĩatigirio nĩ mbura ya mbembe.”
13 Nígbà náà ni Mose na ọ̀pá ọwọ́ rẹ̀ sórí ilẹ̀ Ejibiti, Olúwa sì mú kí afẹ́fẹ́ láti ìlà-oòrùn fẹ́ kọjá lórí ilẹ̀ náà ni gbogbo ọ̀sán àti ni gbogbo òru ni ọjọ́ náà. Ní òwúrọ̀ afẹ́fẹ́ náà ti gbá ọ̀pọ̀lọpọ̀ eṣú wá;
Nĩ ũndũ ũcio Musa agĩtambũrũkia rũthanju rwake igũrũ rĩa bũrũri wa Misiri, nake Jehova agĩtũma rũhuho ruumĩte irathĩro rũhurutane kũu bũrũri ũcio mũthenya wothe na ũtukũ wothe. Gũgĩkinya rũciinĩ rũhuho rũu nĩ rwarehete ngigĩ.
14 wọ́n sì bo gbogbo ilẹ̀ Ejibiti, wọ́n wà ní ibi gbogbo ní orí ilẹ̀ ní àìmoye, ṣáájú àkókò yìí kò sí irú ìyọnu eṣú bẹ́ẹ̀ rí, kò sì ní sí irú rẹ mọ́ lẹ́yìn èyí.
Nacio ngigĩ icio ikĩhithũkĩra bũrũri wa Misiri wothe na igĩikara kũndũ guothe bũrũri-inĩ irĩ nyingĩ mũno. Mbere ĩyo gũtiagĩte mũthiro wa ngigĩ ta ũcio na gũtikagĩa ũngĩ ta ũcio.
15 Wọ́n bo gbogbo ilẹ̀ tí ilẹ̀ fi di dúdú. Wọ́n ba gbogbo ohun tókù ní orí ilẹ̀ lẹ́yìn òjò yìnyín jẹ́; gbogbo ohun ọ̀gbìn tí ó wà ní inú oko àti gbogbo èso tí ó wà lórí igi. Kò sí ewé tí ó kù lórí igi tàbí lórí ohun ọ̀gbìn ní gbogbo ilẹ̀ Ejibiti.
Ikĩhumbĩra thĩ yothe o nginya ĩkĩira. Ikĩrĩa kĩrĩa gĩothe gĩatigarĩtio nĩ mbura ya mbembe, kĩrĩa gĩothe gĩakũraga mĩgũnda o na matunda marĩa maarĩ mĩtĩ-inĩ. Gũtirĩ kĩndũ kĩigũ gĩatigarire mũtĩ-inĩ kana mũmera bũrũri-inĩ wothe wa Misiri.
16 Farao yára ránṣẹ́ pe Mose àti Aaroni, ó sì sọ fún wọn pé, “Èmi ti ṣẹ̀ sí Olúwa Ọlọ́run yín àti sí i yín pẹ̀lú.
Nake Firaũni agĩĩta Musa na Harũni narua, akĩmeera atĩrĩ, “Nĩnjĩhĩirie Jehova Ngai wanyu, o na inyuĩ nĩndĩmwĩhĩirie.
17 Nísinsin yìí ẹ dáríjì mi lẹ́ẹ̀kan sí i kí ẹ sì gbàdúrà sí Olúwa Ọlọ́run yín kí ó lè mú ìpọ́njú yìí kúrò ní ọ̀dọ̀ mi.”
Rĩu ndekerai mehia makwa o rĩngĩ na mũhooe Jehova Ngai wanyu anjehererie mũthiro ũyũ mũũru.”
18 Nígbà náà ni Mose kúrò ní iwájú Farao ó sì gbàdúrà sí Olúwa.
Hĩndĩ ĩyo Musa akĩeherera Firaũni agĩthiĩ akĩhooya Jehova.
19 Olúwa sì yí afẹ́fẹ́ náà padà di afẹ́fẹ́ líle láti apá ìwọ̀-oòrùn wá láti gbá àwọn eṣú náà kúrò ní orí ilẹ̀ Ejibiti lọ sínú Òkun Pupa. Bẹ́ẹ̀ ni ẹyọ eṣú kan kò ṣẹ́kù sí orí ilẹ̀ Ejibiti.
Nake Jehova akĩgarũra rũhuho, akĩrũtua rũhuho rũnene rwa kuuma ithũĩro, naruo rũkĩũmbũra ngigĩ icio, rũgĩcitwara Iria-inĩ Itune. Gũtirĩ gakigĩ o na kamwe gaatigarire bũrũri wa Misiri.
20 Síbẹ̀ Olúwa ṣe àyà Farao le, kò sì jẹ́ kí àwọn ọmọ Israẹli lọ.
No Jehova akĩũmia ngoro ya Firaũni, nake akĩrega kũrekereria andũ a Isiraeli mathiĩ.
21 Nígbà náà ni Olúwa sọ fún Mose pé, “Gbé ọwọ́ rẹ sókè sí ojú ọ̀run kí òkùnkùn bá à le bo gbogbo ilẹ̀ Ejibiti; àní òkùnkùn biribiri.”
Ningĩ Jehova akĩĩra Musa atĩrĩ, “Tambũrũkia guoko ũkũroretie igũrũ matu-inĩ nĩgeetha nduma ĩiyũre bũrũri wa Misiri, nduma ĩngĩhutĩka.”
22 Nígbà náà ni Mose gbé ọwọ́ rẹ sókè sí ojú ọ̀run, òkùnkùn biribiri sì bo gbogbo ilẹ̀ Ejibiti fún ọjọ́ mẹ́ta. Ṣùgbọ́n àwọn ọmọ Israẹli ní ìmọ́lẹ̀ ní ibi tí wọn ń gbé.
Nĩ ũndũ ũcio Musa agĩtambũrũkia guoko akũroretie igũrũ matu-inĩ, nayo nduma nene ĩkĩiyũra bũrũri wa Misiri mĩthenya ĩtatũ.
23 Kò sí ẹni tí ó le è ríran rí ẹlòmíràn tàbí kí ó kúrò ní ibi tí ó wà fún ọjọ́ mẹ́ta. Síbẹ̀ àwọn ọmọ Israẹli ni ìmọ́lẹ̀ ni gbogbo ibi tí wọ́n ń gbé.
Gũtirĩ mũndũ ũngĩahotire kuona ũrĩa ũngĩ kana oime gwake handũ ha mĩthenya ĩtatũ. No andũ a Isiraeli, othe kũrĩa maikaraga kwarĩ na ũtheri.
24 Farao sì ránṣẹ́ pe Mose ó sì wí fún un pé, “Lọ sin Olúwa, kódà àwọn obìnrin àti àwọn ọmọdé lè lọ pẹ̀lú yín, ṣùgbọ́n kí ìwọ kí ó fi agbo àgùntàn àti agbo màlúù yín sílẹ̀.”
Ningĩ Firaũni agĩĩta Musa, akĩmwĩra atĩrĩ, “Thiĩi mũkahooe Jehova. O na atumia anyu na ciana no mathiĩ na inyuĩ; no rĩrĩ, mũtige ndũũru cianyu cia mbũri na cia ngʼombe.”
25 Ṣùgbọ́n Mose sọ pé, “Ìwọ gbọdọ̀ fún wa láààyè láti rú ẹbọ àti ọrẹ ẹbọ sísun ní iwájú Olúwa Ọlọ́run wa.
No Musa akĩmwĩra atĩrĩ, “No nginya ũtwĩtĩkĩrie tũkarutĩre Jehova Ngai witũ magongona na maruta ma njino.
26 Àwọn ohun ọ̀sìn wa gbọdọ̀ lọ pẹ̀lú wa, a kì yóò fi pátákò ẹsẹ̀ ẹran sílẹ̀. A ní láti lò lára wọn fún sínsin Olúwa Ọlọ́run wa, ìgbà tí a bá sì dé ibẹ̀ ni a ó to mọ̀ ohun ti a ó lò láti fi sin Olúwa.”
Ũhiũ witũ no nginya tũthiĩ naguo; gũtirĩ o na ihũngũ tũgũtiga na thuutha. No nginya tũhũthĩre imwe ciacio tũkĩhooya Jehova Ngai witũ, na tũtingĩmenya nĩ irĩkũ irĩbatarania mahooya-inĩ nginya tũkinye kũu.”
27 Ṣùgbọ́n Olúwa sé ọkàn Farao le, kò sì ṣetán láti jẹ́ kí wọn lọ.
No Jehova akĩũmia ngoro ya Firaũni, nake akĩrega kũmarekereria mathiĩ.
28 Farao sọ fún Mose pé, “Kúrò ní iwájú mi! Rí i dájú pé o kò wá sí iwájú mi mọ́! Ọjọ́ tí ìwọ bá rí ojú mi ni ìwọ yóò kùú.”
Firaũni akĩĩra Musa atĩrĩ, “Uma, ũnjeherere! Wĩmenyerere ndũkanooke mbere yakwa rĩngĩ! Mũthenya ũrĩa ũkoona ũthiũ wakwa, no gũkua ũgaakua.”
29 Mose sì dáhùn pé, gẹ́gẹ́ bí ìwọ ti wí, “Èmi kí yóò wá sí iwájú rẹ mọ́.”
Musa akĩmũcookeria atĩrĩ, “O ta ũguo woiga, ndigooka mbere yaku rĩngĩ.”